< Yosiua 6 >

1 Yeligou dunu da Isala: ili fi dunu ilima beda: iba: le, ilia moilai bai bagade gagoi logo ga: su da noga: le ga: i dagoi ba: i. Dunu da gadili masunu o ganodini misunu da hamedei.
Wàyí o, a ti há Jeriko mọ́lé gágá nítorí àwọn ọmọ Israẹli, ẹnikẹ́ni kò jáde, ẹnikẹ́ni kò sì wọlé.
2 Hina Gode da Yosiuama amane sia: i, “Na da Yeligou moilai bai bagade amola Yeligou hina bagade amola ea dadi gagui dunu huluane dima imunu.
Nígbà náà ni Olúwa wí fún Joṣua pé, “Wò ó, mo ti fi Jeriko lé ọ lọ́wọ́ pẹ̀lú ọba rẹ̀ àti àwọn jagunjagun rẹ̀.
3 Di amola dia dadi gagui dunu amo sisiga: le masa. Eso gafeyale ganodini agoane hamoma.
Ẹ wọ́de ogun yí ìlú náà ká lẹ́ẹ̀kan pẹ̀lú gbogbo àwọn jagunjagun. Ẹ ṣe èyí fún ọjọ́ mẹ́fà.
4 Gobele salasu dunu fesuale amo afae afae dalabede gaguli da Gode Ea Gousa: su Sema Gagili amoga bisili masunu. Eso fesuga dilia da Yeligou moilai bai bagade amo fesuale agoane sisiga: ma. Amola ahoasea, gobele salasu dunu da dalabede fulaboma: mu.
Jẹ́ kí àwọn àlùfáà méje gbé fèrè ìwo àgbò ní iwájú àpótí ẹ̀rí. Ní ọjọ́ keje, ẹ wọ́de ogun yí ìlú náà ká ní ìgbà méje, pẹ̀lú àwọn àlùfáà tí ń fọn fèrè.
5 Amasea, ilia da dalabede ha: giwane sedagawane afadafa fulaboma: mu. Amo nabasea, dunu huluane da gilisili ha: giwane wele sia: ma: mu. Amasea, Yeligou moilai bai bagade gagoi amo da mugululi dagoi ba: mu. Amasea, dilia dadi gagui dunu huluane da hedolo moilai bai bagade fane legemusa: masa: mu.”
Nígbà tí ẹ bá gbọ́ ohùn fèrè náà, kí àwọn ènìyàn hó yèè ní igbe ńlá, nígbà náà ni odi ìlú náà yóò sì wó lulẹ̀, àwọn ènìyàn yóò sì lọ sí òkè, olúkúlùkù yóò sì wọ inú rẹ̀ lọ tààrà.”
6 Yosiua da gobele salasu dunu gilisili ilima amane sia: i, “Dilia Gode Ea Gousa: su Sema Gagili lale, dili dunu fesuale dalabede gaguiwane amoga bisili masa.”
Bẹ́ẹ̀ ni Joṣua ọmọ Nuni pe àwọn àlùfáà ó sì wí fún wọn pé, “Ẹ gbé àpótí ẹ̀rí Olúwa náà kí àwọn àlùfáà méje tí ó ru fèrè ìwo wà ní iwájú u rẹ̀.”
7 Amalalu, e da dunu huluane ilima amane sia: i, “Defea! Gusuba: i masa! Ilegei dunu dadi gaguiwane Gode Ea Gousa: su Sema Gagili bisima. Eno dunu huluane fa: no bobogele moilai sisiga: ma.”
Ó sì pàṣẹ fún àwọn ènìyàn náà pé, “Ẹ lọ, kí ẹ sì yí ìlú náà ká pẹ̀lú àwọn olùṣọ́ tí ó hámọ́ra kọjá ní iwájú àpótí ẹ̀rí Olúwa.”
8
Nígbà tí Joṣua ti bá àwọn ènìyàn sọ̀rọ̀ tán, àwọn àlùfáà méje tí wọ́n gbé fèrè méje ní iwájú Olúwa kọjá sí iwájú, wọ́n sì fọn fèrè wọn, àpótí ẹ̀rí Olúwa sì tẹ̀lé wọn.
9 Yosiua ea sia: i defele, ilegei sosodo aligisu dunu da bisili, fa: no gobele salasu dunu fesuale da Gode Ea Gousa: su Sema Gagili gaguli amola dalabede fulabosa asi. Amola fa: no dunu huluane da asili, Yeligou moilai bai bagade sisiga: le asi. Dalabede sia: bagade nabi.
Àwọn olùṣọ tí ó hámọ́ra sì lọ níwájú àwọn àlùfáà tí ń fọn fèrè, olùṣọ́ ẹ̀yìn sì tẹ̀lé àpótí ẹ̀rí náà. Ní gbogbo àsìkò yìí fèrè sì ń dún.
10 Be Yosiua da dunu huluane ilima ouiya: ma: ne sia: beba: le, e da ilima bu sia: beba: le fawane wele sia: ma: ne sia: i.
Ṣùgbọ́n Joṣua tí pàṣẹ fún àwọn ènìyàn pé, “Ẹ kò gbọdọ̀ kígbe ogun, ẹ kò gbọdọ̀ gbé ohùn yín sókè, ẹ má ṣe sọ ọ̀rọ̀ kan títí ọjọ́ tí èmi yóò sọ fún un yín pé kí ẹ hó. Nígbà náà ni ẹ̀yin yóò sì hó!”
11 Dunu da Hina Gode Ea Gousa: su Sema Gagili gaguli afae fawane moilai bai bagade sisiga: mu sia: i. Amalalu, ilia da abula diasu gilisisuga bu misini, golai.
Bẹ́ẹ̀ ni ó mú kí àpótí ẹ̀rí Olúwa yí ìlú náà ká, ó sì yí i ká lẹ́ẹ̀kan. Nígbà náà ni àwọn ènìyàn náà padà sí ibùdó, wọ́n sì gbé ibẹ̀ fún alẹ́ náà.
Joṣua sì dìde ní kùtùkùtù òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, àwọn àlùfáà sì gbé àpótí ẹ̀rí Olúwa.
13 Yosiua da golale, hahabedafa wa: legadole, gobele salasu amola dadi gagui da ilia musa: hamoi defele, Yeligou moilai bai bagade sisiga: i. Ilegei dadi gagui bisili, amalalu gobele salasu fesuale dalabede fulabolala asi, amalu gobele salasu dunu Hina Gode Ea Gousa: su Sema Gagili gaguli asili, fa: no dunu huluane. Dalabede da fulabosa dalebe nabi.
Àwọn àlùfáà méje tí ó gbé ìpè ìwo àgbò méje ń lọ níwájú àpótí ẹ̀rí Olúwa, wọ́n sì ń fọ́n àwọn ìpè: àwọn tí ó hámọ́ra ogun ń lọ níwájú u wọn; àwọn ọmọ tó wà lẹ́yìn sì ń tọ àpótí ẹ̀rí Olúwa lẹ́yìn, àwọn àlùfáà sì ń fọn ìpè bí wọ́n ti ń lọ.
14 Eso ageyaduga ilia da Yeligou moilai bai bagade afae fawane sisiga: le, abula diasuga buhagi. Ilia da eso gafeyale amoga agoane hou hamosu.
Ní ọjọ́ kejì, wọ́n yí ìlú náà ká lẹ́ẹ̀kan wọ́n sì padà sí ibùdó. Wọ́n sì ṣe èyí fún ọjọ́ mẹ́fà.
15 Eso fesuga ilia da hahabedafa wa: legadole, ilia musa: hou defele Yeligou moilai bai bagade amo fesuale agoane sisiga: i.
Ní ọjọ́ keje, wọ́n dìde ní kùtùkùtù òwúrọ̀ ní àfẹ̀mọ́júmọ́, wọ́n sì wọ́de ogun yí ìlú náà ká ní ìgbà méje, gẹ́gẹ́ bí i ti ìṣáájú, ní ọjọ́ keje nìkan ṣoṣo ni wọ́n wọ́de ogun yí ìlú náà ká nígbà méje.
16 Amo esoha, ilia da fesuale sisiga: lala, Yosiua da dunu huluane wele sia: ma: ne sia: i. E da ilima amane sia: i, “Hina Gode da Yeligou moilai bai bagade dilima i dagoi.
Ní ìgbà keje, nígbà tí àwọn àlùfáà fọn fèrè, Joṣua pàṣẹ fún àwọn ènìyàn pé, “Ẹ hó! Nítorí pé Olúwa ti fún un yín ní ìlú náà.
17 Moilai bai bagade amola liligi huluane amo ganodini diala amo Godema gobele salasu agoane ima: ne, wadela: lesima. Be hina: da: i bidi lasu uda La: iha: be amola ea sosogo fi, amo fawane mae medole legema. Bai e da ninia desega ahoasu dunu ela wamolegei.
Ìlú náà àti gbogbo ohun tí ó wà níbẹ̀ ni yóò jẹ́ ìyàsọ́tọ̀ fún Olúwa. Rahabu tí ó jẹ́ panṣágà nìkan àti gbogbo àwọn tí ó wà pẹ̀lú u rẹ̀ ni a ó dá sí; nítorí tí ó pa àwọn ayọ́lẹ̀wò tí á rán mọ́.
18 Be liligi huluane wadela: lesima. Dilia liligi mae lama. Agoane hamosea, Isala: ili dunu huluane da se bagade nabimu.
Ẹ pa ara yín mọ́ kúrò nínú ohun ìyàsọ́tọ̀ fún ìparun, kí ẹ̀yin kí ó má ba à ṣojú kòkòrò nípa mímú nínú àwọn ohun ìyàsọ́tọ̀. Bí kò ṣe bẹ́ẹ̀ ẹ ó sọ ibùdó Israẹli di ìparun. Kí ẹ sì mú wàhálà wá sórí i rẹ̀.
19 Be liligi eno amo da silifa, gouli o balasi amoga hamoi, amo huluane da Hina Godema ima: ne ilegei. Amo huluane dilia Hina Gode Ea muni ligisisu ganodini salima.
Gbogbo fàdákà àti wúrà àti ohun èlò idẹ àti irin jẹ́ mímọ́ fún Olúwa, wọ́n yóò wá sínú ìṣúra Olúwa.”
20 Amasea, gobele salasu dunu da dalabede fulaboi. Amo nababeba: le, dunu huluane da ha: giwane wele sia: i. Amalalu, Yeligou ea gagoi da mugululi sa: i dagoi. Amalalu, Isala: ili dadi gagui dunu huluane da moloiwane agoloba: le heda: le, Yeligou moilai bai bagade doagala: le lai dagoi.
Nígbà tí àwọn àlùfáà fọn ìpè, àwọn ènìyàn náà sì hó. Ó sì ṣe, bí àwọn ènìyàn ti gbọ́ ìró ìpè, tí àwọn ènìyàn sì hó ìhó ńlá, odi ìlú náà wó lulẹ̀ bẹẹrẹ; bẹ́ẹ̀ ni olúkúlùkù ya wọ inú ìlú náà lọ tààrà, wọ́n sì kó ìlú náà.
21 Ilia da dunu, uda amola mano huluane moilai bai bagade ganodini esala, amo gobiheiga medole legei dagoi. Ilia da bulamagau, sibi amola dougi huluane medole legei.
Wọ́n ya ìlú náà sọ́tọ̀ fún Olúwa àti fún ìparun, wọ́n sì fi idà run gbogbo ohun alààyè ní ìlú náà—ọkùnrin àti obìnrin, ọ́mọdé, àti àgbà, màlúù, àgùntàn àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́.
22 Amalalu, Yosiua da musa: desega ahoasu dunu aduna elama amane sia: i, “Alia amo musa: wadela: i hamosu uda amo ea diasuga asili, e amola ea sosogo fi ali da ema sia: i defele, gadili oule misa.”
Joṣua sì sọ fún àwọn ọkùnrin méjì tí wọ́n ti wá ṣe ayọ́lẹ̀wò ilẹ̀ náà pé, “Ẹ lọ sí ilé panṣágà nì, kí ẹ sì mu jáde àti gbogbo ohun tí í ṣe tirẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ẹ tí búra fún un.”
23 Amaiba: le, ela da asili, La: iha: be, ea eda, ame, yolalali amola sosogo fi gadili oule misi. Ili gaga: ma: ne, ela da sosogo fi amola ilia udigili hawa: hamosu dunu amo Isala: ili abula diasu gilisisuga oule asi.
Bẹ́ẹ̀ ní àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin tí ó lọ ṣe ayọ́lẹ̀wò wọlé lọ, wọ́n sì mú Rahabu jáde, baba rẹ̀, ìyá rẹ̀, àwọn arákùnrin rẹ̀ àti ohun gbogbo tí ó ní. Wọ́n sì mú gbogbo ìdílé rẹ̀ jáde, wọ́n sì fi wọ́n sí ibìkan ní ìta ibùdó àwọn ará Israẹli.
24 Amalalu, Isala: ili dunu da Yeligou moilai bai bagade amola liligi huluane amo ganodini diala amo laluga gobesi dagoi. Be liligi amo gouli, silifa, balasi amola amoga hamoi huluane ilia da lale, Hina Gode Ea muni ligisisu ganodini sali.
Nígbà náà ni wọ́n sun gbogbo ìlú náà àti gbogbo ohun tí ó wà nínú u rẹ̀, ṣùgbọ́n wọ́n fi fàdákà, wúrà ohun èlò idẹ àti irin sínú ìṣúra ilé Olúwa.
25 Be Yosiua da musa: wadela: le hamosu uda La: iha: be amola ea sosogo fi hame medole legei. Bai e da desega ahoasu dunu amo Yosiua da Yeligou moilai bai bagadega asunasi, amo wamoaligi. (La: iha: be egaga fi da Isala: ili soge ganodini esalu amola wali eso esalebe.)
Ṣùgbọ́n Joṣua dá Rahabu panṣágà pẹ̀lú gbogbo ìdílé e rẹ̀ àti gbogbo ẹni tí í ṣe tirẹ̀ sí nítorí pé, ó pa àwọn ọkùnrin tí Joṣua rán gẹ́gẹ́ bí ayọ́lẹ̀wò sí Jeriko mọ́. Ó sì ń gbé láàrín ará Israẹli títí di òní yìí.
26 Amo esoha, Yosiua da sisasu olelei, amane, “Nowa dunu da Yeligou moilai bai bagade bu gagusia da Hina Gode Ea gagabusu aligima: ne ba: mu. Nowa da amo moilai bai bagade ea bai gagusia da ea magobo mano fisi dagoi ba: mu. Amola nowa da amo moilai bai bagade ea gagoi logo ga: su gagusia da ea ufi mano fisi dagoi ba: mu.”
Ní àkókò náà Joṣua sì búra pé, “Ègún ni fún ẹni náà níwájú Olúwa tí yóò dìde, tí yóò sì tún ìlú Jeriko kọ́: “Pẹ̀lú ikú àkọ́bí ọmọ rẹ̀ ni yóò fi pilẹ̀ rẹ̀; ikú àbíkẹ́yìn rẹ̀ ní yóò fi gbé ìlẹ̀kùn bodè rẹ̀ ró.”
27 Hina Gode da Yosiua fidimusa: sigi esalu. Soge huluane amo ganodini, dunu huluane da Yosiua ea gasa bagade hou nabi dagoi.
Bẹ́ẹ̀ ni Olúwa wà pẹ̀lú Joṣua; òkìkí rẹ̀ sì kàn ká gbogbo ilẹ̀ náà.

< Yosiua 6 >