< Yosiua 22 >

1 Amalalu, Yosiua da Liubene fi, Ga: de fi amola Eso Mabadi la: idi Mana: se fi huluane gilisima: ne sia: i.
Joṣua sì pe àwọn ẹ̀yà Reubeni, ẹ̀yà Gadi àti ìdajì ẹ̀yà Manase
2 E da ilima amane sia: i, “Dilia da liligi huluane amo Hina Gode Ea hawa: hamosu dunu Mousese dilima hamoma: ne sia: i amo huluane hamoi dagoi. Amola dilia da na hamoma: ne sia: i huluane nabasu.
ó sì sọ fún wọn pé, “Ẹ̀yin ti ṣe gbogbo èyí tí Mose ìránṣẹ́ Olúwa pàṣẹ, ẹ sì ti ṣe ìgbọ́ràn sí ohun gbogbo tí mo pàṣẹ.
3 Eso huluane, dilia da dilia na: iyado Isala: ili dunu amo hame yolesi. Dilia da dawa: iwane Gode Ea sia: nabawane hamonanusu.
Ẹ kò fi àwọn arákùnrin yín sílẹ̀ láti ìgbà yí títí di òní, ṣùgbọ́n ẹ ti kíyèsára láti pa òfin Olúwa Ọlọ́run yín mọ́.
4 Be wali, dilia Hina Gode da Ea ilegele sia: i defele, dilia Isala: ili yolalali ilima olofosu i dagoi. Amaiba: le, soge amo Yodane Hano eso mabadi la: idi amo dilia ilegei amola Hina Gode Ea hawa: hamosu dunu Mousese da dilima i, amo sogega buhagima.
Nísinsin yìí tí Olúwa Ọlọ́run yín ti fún àwọn arákùnrin yín ní ìsinmi gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣèlérí, ẹ padà sí ilẹ̀ yín níbi tí Mose ìránṣẹ́ Olúwa fi fún yin ní òdìkejì Jordani.
5 Dilia hamoma: ne sia: i amo Mousese da dilima olelei amo noga: le nabima. Dilia Hina Godema asigima, Ea hanai hamoma, Ea hamoma: ne sia: i noga: le nabima amola mae fisili, dilia dogoga, dilia asigi dawa: suga amola dilia da: i hodo huluane amoga Ea hawa: asigiwane hamoma.
Ṣùgbọ́n ẹ ṣọ́ra gidigidi láti pa àṣẹ àti òfin tí Mose ìránṣẹ́ Olúwa fi fún yin mọ́. Láti fẹ́ràn Olúwa Ọlọ́run yín, láti rìn nínú gbogbo ọ̀nà rẹ̀, láti gbọ́rọ̀ sí àṣẹ rẹ̀, láti dìímú ṣinṣin àti láti sìn ín pẹ̀lú gbogbo ọkàn yín àti gbogbo àyà yín.”
6 Yosiua da ili asunasi. E da Gode Ea hahawane dogolegelewane fidisu ilima sia: i. E amane sia: i, “Dilia da bagadewane gaguiwane dilia sogega masunu. Dilia da ohe fi, silifa, gouli, balasi, ouli amola abula bagohame gala. Dilia sogega ahoasea, dilia fi dunu eno ilima dilia liligi dilima ha lai dunuma lai amo mogili ilima ima.” Amalalu, ilia da fisili ilia sogega masunusa: asi. Mousese da soge amo Yodane Hano eso mabadi la: idi amo mogili Ma: na: se fi la: idi ilima i. Be Ma: na: se fi la: idi eno ilima Yosiua da soge Yodane eso dabe la: idi amo ilima i. Amola e da soge eno Isala: ili fi ilima i.
Nígbà náà ni Joṣua súre fún wọn, ó sì jẹ́ kí wọn máa lọ sí ilẹ̀ wọn.
7
(Mose ti fi ilẹ̀ fún ìdajì ẹ̀yà Manase ní Baṣani, Joṣua sì ti fún ìdajì ẹ̀yà yòókù ní ilẹ̀ ní ìwọ̀-oòrùn Jordani, pẹ̀lú àwọn arákùnrin wọn). Joṣua súre fún wọn ó sì jẹ́ kí wọn máa lọ sí ilẹ̀ wọn,
8
Ó sì wí pé, “Ẹ padà sí ilẹ̀ ẹ yín pẹ̀lú ọrọ̀ púpọ̀ yín, pẹ̀lú agbo ẹran ọ̀sìn, pẹ̀lú fàdákà, wúrà, idẹ àti irin, àti ọ̀pọ̀lọpọ̀ aṣọ, kí ẹ sì pín ìkógun tí ẹ rí gbà láti ọ̀dọ̀ àwọn ọ̀tá yín pẹ̀lú àwọn arákùnrin yín.”
9 Amaiba: le, Liubene, Ga: de amola Eso Mabadi Mana: se, amo fi dunu da ilia sogega buhagi. Ilia da Siailou moilai bai bagade Ga: ina: ne soge ganodini, amoga Isala: ili dunu eno fisili, ilia soge amoga doaga: musa: asi. Ilia soge da Gilia: de. Ilia da amo soge, Hina Gode da Mousesema sia: i defele, lai dagoi.
Báyìí ni àwọn ẹ̀yà Reubeni, ẹ̀yà Gadi àti ìdajì ẹ̀yà Manase fi àwọn ará Israẹli sílẹ̀ ní Ṣilo ní Kenaani láti padà sí Gileadi, ilẹ̀ wọn, èyí tí wọ́n ti gbà gẹ́gẹ́ bí àṣẹ Olúwa láti ẹnu Mose wá.
10 Liubene fi, Ga: de fi amola Eso Mabadi Ma: na: se fi da Gilailode sogebiga doaga: loba (Gilailode da Yodane Hano eso dabe la: idi galu), ilia da hano bega: oloda bagade hamoi.
Nígbà tí wọ́n wá dé Geliloti ní ẹ̀bá Jordani ní ilẹ̀ Kenaani, àwọn ẹ̀yà Reubeni, ẹ̀yà Gadi àti ìdajì ẹ̀yà Manase mọ pẹpẹ ńlá tí ó tóbi kan ní ẹ̀bá Jordani.
11 Ba: su dunu da Isala: ili fi dunu eno ilima amane sia: ne iasu, “Nabima! Liubene, Ga: de amola Eso Mabadi Mana: se amo fi dunu da Gilailode sogebi amo Yodane ninia la: idi amoga oloda hamoi dagoi.”
Nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli gbọ́ pé àwọn ọmọ Reubeni, àti àwọn ọmọ Gadi àti ìlàjì ẹ̀yà Manase mọ pẹpẹ kan dojúkọ ilẹ̀ Kenaani ní Geliloti ní ẹ̀bá Jordani ní ìhà kejì àwọn ọmọ Israẹli,
12 Isala: ili dunu da amo sia: nababeba: le, dunu huluane da Siailou moilaiga amo eso mabadili fi ilima gegemusa: gilisi.
gbogbo àjọ Israẹli péjọ ní Ṣilo láti lọ bá wọn jagun.
13 Amalalu, Isala: ili dunu da gobele salasu dunu Elia: isa amo ea mano Finia: se, amo Liubene, Ga: de amola Eso Mabadi Ma: na: se fi dunuma sia: ma: ne asunasi.
Àwọn ọmọ Israẹli rán Finehasi ọmọ Eleasari àlùfáà, sí ilẹ̀ Gileadi, sí Reubeni, sí Gadi àti sí ìdajì ẹ̀yà Manase.
14 Isala: ili bisilua dunu nabuane gala da Finia: se sigi asi. Eso dabe laidi fi nabuane gala da afae afae fi bisilua dunu afadafa ilia fi amoga asunasi.
Pẹ̀lú rẹ̀ wọ́n rán àwọn ọkùnrin olóyè mẹ́wàá, ẹnìkan fún ẹ̀yà Israẹli kọ̀ọ̀kan, olórí ọ̀kọ̀ọ̀kan tiwọn jẹ́ olórí ìdílé láàrín àwọn ọmọ Israẹli.
15 Ilia da Liubene, Ga: de amola Eso Mabadi Mana: se fi dunu ilia soge Gilia: de amoga doaga: i.
Nígbà tí wọ́n lọ sí Gileadi—sí Reubeni, Gadi àti ìdajì ẹ̀yà Manase—wọ́n sì sọ fún wọn pé,
16 Ilia da eso mabadi la: idi fi ilima amane sia: i, “Hina Gode Ea fi gilisi huluane da amane sia: sa, ‘Dilia da abuliba: le Isala: ili Hina Godema amo wadela: i hou hamobela: ? Dilisu da oloda hamobeba: le, Gode Ea sia: hame nabasu. Dilia da Ema fa: no bobogesu hou yolesi dagoi.
“Gbogbo àjọ ènìyàn Olúwa wí pe, ‘A fẹ́ mọ ìdí tí ẹ fi sẹ̀ sí Ọlọ́run Israẹli nípa yíyí padà kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀ tí ẹ sì kọ́ pẹpẹ ìṣọ̀tẹ̀ ní ìlòdì sí Olúwa?
17 Ninia wadela: i hou Bio goumia hamoi amo bu dawa: ma! Hina Gode da ninima olo bagade iabeba: le, ninia se bagade nabi. Amo se nabasu da wali diala. Bu wadela: le hamomu da hamedei.
Ẹ̀ṣẹ̀ Peori kò ha tó fún wa bí? Títí di òní yìí àwa kò tí ì wẹ ara wa mọ́ kúrò nínú ẹ̀ṣẹ̀ náà, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àjàkálẹ̀-ààrùn ti jà láàrín ènìyàn Olúwa!
18 Dilia da wali Ema fa: no bobogemu higama: bela: ? Dilia da wali eso Ema odoga: sea, E da aya Isala: ili dunu huluane ilima ougimu.
Ṣé ẹ tún wá ń padà kúrò lẹ́yìn Olúwa ni báyìí? “‘Tí ẹ̀yin bá ṣọ̀tẹ̀ sí Olúwa ní òní, ní ọ̀la ní òun o bínú sí gbogbo ìpéjọpọ̀ Israẹli.
19 Defea! Dilia soge amo ganodini dilia da Hina Godema nodone sia: ne gadomusa: defele hame o ledo gala ba: sea, Hina Gode Ea soge eso dabe la: ididili (amo ganodini Ea Da: bena: gele abula diasu diala), amoga misa. Ninia gilisisu ganodini soge ilegema. Be dilia Godema hame nabasu hou hamosa: besa: le amola E da ninia da hame nabasu dunu dawa: sa: besa: le, ninia Hina Godema oloda eno mae hamoma. Ea olodadafa da gagui dagoi.
Bí ilẹ̀ ìní yín bá di àìmọ́, ẹ wá sí orí ilẹ̀ ìní Olúwa, ní ibi tí àgọ́ Olúwa dúró sí, kí ẹ sì pín ilẹ̀ náà pẹ̀lú wa. Ṣùgbọ́n kí ẹ má ṣe ṣọ̀tẹ̀ sí Olúwa tàbí sí wa nípa mímọ pẹpẹ fún ara yín, lẹ́yìn pẹpẹ Olúwa Ọlọ́run wa.
20 Sela ea mano A: iga: ne bu dawa: ma! E da Gode Ea sia: i amo liligi huluane da wadela: musa: ilegei dagoi, amo hame nabasu. Ea wadela: i houba: le, Hina Gode da Isala: ili dunu huluanema se iasu. A: iga: ne fawane hame be eno dunu amolawane, da ea wadela: le hou hamoiba: le bogoi.”
Nígbà tí Akani ọmọ Sera ṣe àìṣòótọ́ nípa ohun ìyàsọ́tọ̀, ǹjẹ́ ìbínú kò wá sí orí gbogbo àjọ ènìyàn Israẹli nítorí rẹ̀ bí? Òun nìkan kọ́ ni ó kú fún ẹ̀ṣẹ̀ ẹ rẹ̀.’”
21 Liubene, Ga: de amola Eso Mabadi Ma: na: se fi dunu da Yodane Hano eso dabe la: idi fi amo bisilua dunuma bu adole i,
Nígbà náà ni Reubeni, Gadi àti ẹ̀yà Manase sọ nínú ìdáhùn wọn fún àwọn olórí Israẹli pé.
22 “Gasa Bagadedafa Gode da Hinadafa! Gasa Bagadedafa Gode da Hina Godedafa! Ninia amo hou hamoi E dawa: , amola dilia amolawane dawa: mu ninia da hanai. Ninia da hame nabasu hou hamoi ganiaba amola dafawaneyale dawa: su hou fisiagai ganiaba, dilia da nini medole legemu da defea gala: loba.
Olúwa Ọlọ́run àwọn ọlọ́run! Olúwa Ọlọ́run àwọn ọlọ́run, Òun mọ̀, jẹ́ kí Israẹli pẹ̀lú kí ó mọ̀! Bí èyí bá wà ní ìṣọ̀tẹ̀ tàbí àìgbọ́ràn sí Olúwa, ẹ má ṣe gbà wa ní òní yìí.
23 Ninia da Hina Gode Ea sia: mae nabawane ninisu oloda gobele sanasimusa: o gagoma amola hahawane gilisisu iasu hahamoma: ne hamoi ganiaba, Hina Gode Hisu da ninima se imunu da defea gala: loba.
Bí àwa bá ti mọ pẹpẹ wa láti yí padà kúrò ní ọ̀dọ̀ Olúwa àti láti rú ẹbọ sísun àti ẹbọ oúnjẹ jíjẹ, tàbí ẹbọ àlàáfíà ní orí rẹ, kí Olúwa fún ara rẹ̀ gba ẹ̀san.
24 Be hame mabu! Diligaga fi da hobea ninigaga fi ilima sia: sa: besa: le, ninia da beda: iba: le agoane hamosu. Ilia da ninigaga fi ilima agoane sia: sa: besa: le amane, ‘Ninia Isala: ili Hina Gode da dilia Gode hame.
“Bẹ́ẹ̀ kọ́! Àwa ṣe èyí ní ìbẹ̀rù pé ní ọjọ́ tí àwọn ọmọ yín yóò wí fún wa pé, ‘Kí ni ẹ̀yin ní ṣe pẹ̀lú Olúwa, Ọlọ́run Israẹli?
25 E da Yodane Hano alalo amo da afafasu alalo, ninia amola dilia Liubene amola Ga: de amo afafama: ne ilegei dagoi.’ Amasea, diligaga fi da ninigaga fi ilia Hina Godema nodone sia: ne gadosu logo hedofasa: besa: le, ninia agoane hamoi.
Olúwa ti fi Jordani ṣe ààlà láàrín àwa àti ẹ̀yin—àwọn ọmọ Reubeni àti àwọn ọmọ Gadi! Ẹ kò ni ní ìpín nínú Olúwa.’ Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọmọ yín lè mú kí àwọn ọmọ wa dẹ́kun láti máa bẹ̀rù Olúwa.
26 Amaiba: le, ninia da oloda hamoi. Gobele salimusa: o Hina Godema iasu hamoma: ne hame hamoi.
“Nítorí èyí ni àwa ṣe wí pé, ‘Ẹ jẹ́ kí àwa múra láti mọ pẹpẹ kan, ṣùgbọ́n kì í ṣe fún ẹbọ sísun, tàbí fún àwọn ìrúbọ.’
27 Be amo da ninima, dilima amola ninigaga fi huluane ilima dawa: digima: ne olelesu agoane dialoma: ne hamoi. Amo wanonesisu ea olelesu da ninia eso mabadi fi da dafawane Hina Gode Ea ilegei sogebi amoga Ea hadigi abula diasuga Ema nodone sia: ne gadolala amola Ema Hahawane Gilisili Olofole Iasu amola Wadela: i Hou Dabe Ima: ne gobele salasu iaha. Diligaga fi da ninigaga fi Hina Godema afafai, amo ilia sia: sa: besa: le agoane hamoi.
Ní ọ̀nà mìíràn, yóò jẹ́ ẹ̀rí kan láàrín àwa àti ẹ̀yin àti àwọn ìran tí ń bọ̀, pé àwa yóò jọ́sìn fún Olúwa ní ibi mímọ́ rẹ̀ pẹ̀lú ẹbọ sísun wa, ẹbọ àti ọrẹ àlàáfíà. Nígbà náà ni ẹ̀yìn ọ̀la, àwọn ọmọ yín kò ní lè sọ fún tiwa pé, ‘Ẹ kò ní ìpín nínú ti Olúwa.’
28 Ninia da agoane dawa: i galu. Amo hou fa: no agoane ba: loba, ninigaga fi da amane sia: la: loba, ‘Ba: ma! Ninia aowalali da oloda amo Hina Gode Ea olodadafa defele hamosu. Amo da hahawane iasu o gobele salasu hamoma: ne hame hamoi. Be ninia dunu amola dilia dunu nini huluanema dawa: digima: ne olelesu dialoma: ne.’
“Àwa sì wí pé, ‘Tí wọ́n bá tilẹ̀ sọ èyí fún wa, tàbí sí àwọn ọmọ wa, a ó dáhùn pé, “Ẹ wo àpẹẹrẹ pẹpẹ Olúwa, èyí tí àwọn baba wa mọ, kì í ṣe fún ẹbọ sísun àti ẹbọ ṣùgbọ́n fún ẹ̀rí láàrín àwa àti ẹ̀yin.”’
29 Ninia da Hina Godema odoga: su hou hame hamomu. Ninia da Hina Godema fa: no bobogesu hou fisili, oloda amo da: iya Wadela: i Hou Dabe Ima: ne gobele salasu amola Hahawane Gilisili Olofole Iasu hamoma: ne hamedafa hamomu. Ninia olodadafa afae fawane da ninia Hina Gode Ea olodadafa amo da Ea esalebe Da: bena: gele abula diasu ea midadi lela.”
“Kí Ọlọ́run má jẹ́ kí àwa kí ó ṣọ̀tẹ̀ sí Olúwa, kí àwa sì yípadà kúrò ní ọ̀dọ̀ rẹ ní òní nípa mímọ pẹpẹ ẹbọ sísun, ọrẹ oúnjẹ jíjẹ àti ẹbọ lẹ́yìn pẹpẹ Olúwa Ọlọ́run wa tí ó dúró níwájú àgọ́ rẹ̀.”
30 Gobele salasu dunu Finia: se amola Isala: ili fi eso dabe la: idi esalebe bisilua dunu nabuane gala da Liubene, Ga: de amola Eso Mabadi Ma: na: se fi dunu ilia sia: nababeba: le, olofoi galu.
Nígbà tí Finehasi àlùfáà àti àwọn olórí ìjọ ènìyàn, àwọn olórí ìdílé Israẹli gbọ́ ohun tí Reubeni, Gadi àti Manase ti sọ, ó dùn mọ́ wọn.
31 Gobele salasu dunu Elia: isa ea mano Finia: se, da ilima amane sia: i, “Wali ninia dawa: ! Hina Gode da nini sigi esala! Dafawane! Dilia da Ema hame nabasu hou hame hamoi. Amaiba: le, Isala: ili da Hina Gode Ea se iasu hame ba: mu.”
Finehasi ọmọ Eleasari, àlùfáà wí fún Reubeni, Gadi àti Manase pé, “Ní òní ni àwa mọ̀ pé Olúwa wà pẹ̀lú wa, nítorí tí ẹ̀yin kò hùwà àìṣòótọ́ sí Olúwa ní orí ọ̀rọ̀ yí nísinsin yìí, ẹ̀yin ti yọ àwọn ará Israẹli kúrò ní ọwọ́ Olúwa”.
32 Amalalu, Finia: se amola Isala: ili bisilua dunu da Liubene fi amola Ga: de fi Gilia: de sogega esalu fisili, Ga: ina: ne sogega buhagi.
Nígbà náà ni Finehasi ọmọ Eleasari àlùfáà àti àwọn olórí padà sí Kenaani láti ibi ìpàdé wọn pẹ̀lú àwọn ẹ̀yà Reubeni àti ẹ̀yà Gadi ní Gileadi, wọ́n sì mú ìròyìn tọ àwọn ọmọ Israẹli lọ.
33 Isala: ili dunu da hahawane ba: i amola Godema nodosu. Ilia musa: sia: amo gegemusa: amola soge amoga Liubene dunu amola Ga: de dunu da fi galu amo wadela: musa: , amo sia: yolesi dagoi.
Inú wọn sì dùn láti gbọ́ ìròyìn náà, wọ́n sì yin Ọlọ́run. Wọn kò sì sọ̀rọ̀ mọ́ nípa lílọ bá wọn jagun láti run ilẹ̀ tí àwọn ẹ̀yà Reubeni àti ẹ̀yà Gadi ń gbé.
34 Liubene fi dunu amola Ga: de fi dunu da amane sia: i, “Amo oloda da Hina Gode da Godedafa amo ninia huluanema dawa: digima: ne olelesu ba: su agoane.” Amaiba: le, ilia amo olodama “Dawa: digima: ne Olelesu Ba: su” dio asuli.
Ẹ̀yà Reubeni àti ẹ̀yà Gadi sì fún pẹpẹ náà ní orúkọ yìí, “Ẹ̀rí láàrín wa pé Olúwa ni Ọlọ́run.”

< Yosiua 22 >