< Yone 13 >

1 Aya da Baligisu Lolo Manu galu. E da osobo bagade yolesili, Godema bu heda: mu amo da gadenene, Yesu E dawa: i galu. E da osobo bagadega esaloba, E da Ea hou lalegagui dunu ilima bagadewane asigilalu. E da amo bagade dogolegei hou ilima hamoi, amo hame fisi.
Ǹjẹ́ kí àjọ ìrékọjá tó dé, nígbà tí Jesu mọ̀ pé, wákàtí rẹ̀ dé tan, tí òun ó ti ayé yìí kúrò lọ sọ́dọ̀ Baba, fífẹ́ tí ó fẹ́ àwọn tirẹ̀ tí ó wà ní ayé, ó fẹ́ wọn títí dé òpin.
2 Yesu amola Ea ado ba: su dunu, ilia da gilisili ha: i naha esalu. Sa: ida: ne da Yudase (Saimone Isaga: liode ea mano) amo ea asigi dawa: su oleleiba: le, e da Yesu hohonomu dawa: lalu.
Bí wọ́n sì ti ń jẹ oúnjẹ alẹ́, tí èṣù ti fi í sí ọkàn Judasi Iskariotu ọmọ Simoni láti fi í hàn;
3 Yesu da Ea Ada da Ema gasadafa hou ia dagoi, amo dawa: i galu. E da Godema misi, amola Godema bu masunu, dawa: i galu.
tí Jesu sì ti mọ̀ pé Baba ti fi ohun gbogbo lé òun lọ́wọ́, àti pé lọ́dọ̀ Ọlọ́run ni òun ti wá, òun sì ń lọ sọ́dọ̀ Ọlọ́run;
4 Amalalu, ha: i nanu, E wa: legadole, abula fadegale, doga: su abula lale, amo idiniginisili,
Ó dìde ní ìdí oúnjẹ alẹ́, ó sì fi agbádá rẹ̀ lélẹ̀ ní apá kan; nígbà tí ó sì mú aṣọ ìnura, ó di ara rẹ̀ ní àmùrè.
5 hano dili, gaga ganodini salawane, E da Ea ado ba: su dunu ilia emo muni dodofelalu amola Ea doga: su abula idiniginisi amoga doga: i.
Lẹ́yìn náà, ó bu omi sínú àwokòtò kan, ó sì bẹ̀rẹ̀ sí í máa wẹ ẹsẹ̀ àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ó sì ń fi aṣọ ìnura tí ó fi di àmùrè nù wọ́n.
6 E da Bidama doaga: le, Bida da Ema amane sia: i, “Hina! Dia da na emo abulimusa: dodofema: bela: ?”
Nígbà náà ni ó dé ọ̀dọ̀ Simoni Peteru, òun sì wí fún un pé, “Olúwa, ìwọ yóò ha wẹ ẹsẹ̀ mi?”
7 Yesu da ema bu adole i, “Na hou di wahadafa hame dawa: Be di da hobea dawa: mu.”
Jesu dá a lóhùn, ó sì wí fún un pé, “Ohun tí èmi ń ṣe ni ìwọ kò mọ̀ nísinsin yìí; ṣùgbọ́n yóò yé ọ ní ìkẹyìn.”
8 Bida e bu sia: i, “Na emo Di da hamedafa dodofemu.” Be Yesu E bu adole i, “Dia emo Na hame dodofesea, di da Na fi ganodini esalumu hamedei.” (aiōn g165)
Peteru wí fún un pé, “Ìwọ kì yóò wẹ̀ ẹsẹ̀ mi láé.” Jesu sì dalóhùn pé, “Bí èmi kò bá wẹ̀ ọ́, ìwọ kò ní ìpín ní ọ̀dọ̀ mi.” (aiōn g165)
9 Saimone Bida da bu adole i, “Hina! Na emo fawane hame, be na lobo amola na dialuma, huluane dodofema!”
Simoni Peteru wí fún ún pé, “Olúwa, kì í ṣe ẹsẹ̀ mi nìkan, ṣùgbọ́n àti ọwọ́ àti orí mi pẹ̀lú.”
10 Yesu E amane sia: i, “Nowa da hanoga ulabeba: le, e da fofoloidafa gala. Ea da: i hodo da bu hame dodofele, ea emo fawane bu dodofemu da defea. Dilia huluane da fofoloi dagoi. Be dunu afae fawane da fofoloi hame.”
Jesu wí fún un pé, “Ẹni tí a wẹ̀ kò tún fẹ́ ju kí a ṣan ẹsẹ̀ rẹ̀, ṣùgbọ́n ó mọ́ níbi gbogbo: ẹ̀yin sì mọ́, ṣùgbọ́n kì í ṣe gbogbo yín.”
11 (Ea hohonomu dunu amo dawa: beba: le, Yesu da amane sia: i, “Huluane da fofoloi dagoi. Be afadafa fawane da hame fofoloi.”)
Nítorí tí ó mọ ẹni tí yóò fi òun hàn; nítorí náà ni ó ṣe wí pé, kì í ṣe gbogbo yín ni ó mọ́.
12 Ilia emo dodofelalu, E da Ea abula bu idiniginisili, E da Hi fia sogebi amogai bu fili, amane sia: i, “Na waha hou hamoi dilia dawa: bela: ?
Nítorí náà lẹ́yìn tí ó wẹ ẹsẹ̀ wọn tán, tí ó sì ti mú agbádá rẹ̀, tí ó tún jókòó, ó wí fún wọn pé, “Ẹ̀yin mọ ohun tí mo ṣe sí yín bí?
13 Dilia da Nama Olelesu amola Hina dio asula. Amo da defea. Na da dilia Hina esala.
Ẹ̀yin ń pè mí ní ‘Olùkọ́’ àti ‘Olúwa,’ ẹ̀yin wí rere; bẹ́ẹ̀ ni mo jẹ́.
14 Amaiba: le, Na, dilia Olelesu amola dilia Hina, dilia emo Na dodofeiba: le, dilia eno dunu eno dunu ilia emo dodofemu da defea.
Ǹjẹ́ bí èmi tí í ṣe Olúwa àti olùkọ́ yín bá wẹ ẹsẹ̀ yín, ó tọ́ kí ẹ̀yin pẹ̀lú sì máa wẹ ẹsẹ̀ ara yín.
15 Dilia da Na hou defele hamoma: ne, Na da amo hou dilima olelei.
Nítorí mo fi àpẹẹrẹ fún yín, kí ẹ̀yin lè máa ṣe gẹ́gẹ́ bí mo ti ṣe sí yín.
16 Na dilima dafawane sia: sa. Hawa: hamosu dunu da ea hina ea hou hame baligisa., amola adola ahoasu dunu da asunasisu dunu ea hou hame baligisa.
Lóòótọ́, lóòótọ́ ni mo wí fún yín, ọmọ ọ̀dọ̀ kò tóbi ju ọ̀gá rẹ̀ lọ, bẹ́ẹ̀ ni ẹni tí a rán kò tóbi ju ẹni tí ó rán an lọ.
17 Amo hou dilia dawa: Amaiba: le, dawa: beba: le hamosea, dilia hahawane bagade ba: mu.
Bí ẹ̀yin bá mọ nǹkan wọ̀nyí, alábùkún fún ni yín, bí ẹ̀yin bá ń ṣe wọ́n!
18 Na da dunu huluane ilia hou hame olelesa. Na da Na ilegei dunu ili dawa: Be Gode Sia: da agoane dedei diala, `Na gilisili ha: i nasu na: iyado dunu da bu sinidigili, e da Na higa: i,’ amo sia: da dafawane ba: mu.
“Kì í ṣe ti gbogbo yín ni mo ń sọ, èmi mọ àwọn tí mo yàn, ṣùgbọ́n kí Ìwé Mímọ́ bá à lè ṣẹ, ‘Ẹni tí ń bá mi jẹun pọ̀ sì gbé gìgísẹ̀ rẹ̀ sí mi.’
19 Amo hou da hame doaga: i. Be amo hou doaga: sea, dilia da `Na da Nisu’ amo adoi defele dafawaneyale dawa: ma: ne, Na da hidadea dilima adoi dagoi.
“Láti ìsinsin yìí lọ ni mo wí fún un yín kí ó tó dé, pé nígbà tí ó bá dé, kí ẹ̀yin lè gbàgbọ́ pé èmi ni.
20 Na dilima dafawane sia: sa. Nowa dunu da na hawa: hamomusa: adola ahoasu dunu hahawane yosia: sea, e da Na hahawane yosia: sa., amola nowa da Na hahawane yosia: sea, e da Na Asunasisu Gode hahawane yosia: sa.
Lóòótọ́, lóòótọ́ ni mo wí fún un yín, ẹni tí ó bá gba ẹnikẹ́ni tí mo rán, ó gbà mí; ẹni tí ó bá sì gbà mí, ó gba ẹni tí ó rán mi.”
21 Amo sia: nanu, Yesu da se bagade nabi. E mae wamolegele, amane sia: i, “Na dilima dafawane sia: sa! Dilia fi dunu afadafa da Na hohonomu.”
Nígbà tí Jesu ti wí nǹkan wọ̀nyí tán, ọkàn rẹ̀ dàrú nínú rẹ̀, ó sì jẹ́rìí, ó sì wí pé, “Lóòótọ́ lóòótọ́ ni mo wí fún un yín pé, ọ̀kan nínú yín yóò dà mí.”
22 Ea ado ba: su dunu ilia enoma, enoma ba: lalu, Ea sia: bai hame dawa: beba: le, bagadewane fofogadigi.
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ń wò ara wọn lójú, wọ́n ń ṣiyèméjì ti ẹni tí ó wí.
23 Ado ba: su dunu afadafa, amo da Yesu Ea dogolegei, e da Yesuma dafulili esalu.
Ǹjẹ́ ẹnìkan rọ̀gbọ̀kú sí àyà Jesu, ọ̀kan nínú àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, ẹni tí Jesu fẹ́ràn.
24 Saimone Bida da ema loboga wele, amane sia: i, “Ema adole ba: ma! E da nowa dunu ea hou sia: sa!”
Nítorí náà ni Simoni Peteru ṣàpẹẹrẹ sí i, ó sì wí fún un pé, “Wí fún wa ti ẹni tí o ń sọ.”
25 Amalalu, amo ado ba: su dunu da bu gadenenewane Yesuma asili, Ema adole ba: i, “Amo dunu Dia sia: i da nowala: ?”
Ẹni tí ó ń rọ̀gún ní àyà Jesu wí fún un pé, “Olúwa, ta ni í ṣe?”
26 Yesu da bu adole i, “Na da agi hanoga gele, dunu afae ema imunu. Amo dunu!” Amalalu, E agi lale, hano gele, Yudase (Saimone Isaga: liode ea mano) ema i dagoi.
Nítorí náà Jesu dáhùn pé, “Òun náà ni, ẹni tí mo bá fi àkàrà fún nígbà tí mo bá fi run àwo.” Nígbà tí ó sì fi run ún tan, ó fi fún Judasi Iskariotu ọmọ Simoni.
27 Yudase da agi lalu, Sa: ida: ne da ea dogo ganodini aligila sa: i. Yesu da Yudasema amane sia: i “Dia hanai hawa: hamosu hedolo hamoma!”
Ní kété tí Judasi gba àkàrà náà ni Satani wọ inú rẹ̀ lọ. Nítorí náà Jesu wí fún un pé, “Ohun tí ìwọ ń ṣe nì, yára ṣe é kánkán.”
28 Be gilisili ha: i nanebe dunu ilia da Yesu Ea Yudasema sia: i amo ea bai hame dawa: i.
Kò sì sí ẹnìkan níbi tábìlì tí ó mọ ìdí tí ó ṣe sọ èyí fún un.
29 Yudase da muni salasu gaguiba: le, Yesu da ha: i manu eno bidi lama: ne o hame gagui dunuma ima: ne Yesu da sia: i, eno ado ba: su dunu ilia amane dawa: i galu.
Nítorí àwọn mìíràn nínú wọn rò pé, nítorí Judasi ni ó ni àpò, ni Jesu fi wí fún un pé, ra nǹkan wọ̀n-ọn-nì tí a kò le ṣe aláìní fún àjọ náà; tàbí kí ó lè fi nǹkan fún àwọn tálákà.
30 Yudase da agi lalu, hedolowane gadili asi. Logo doasili, gadili gasi bagade ba: i.
Nígbà tí ó sì ti gbà òkèlè náà tan, ó jáde lójúkan náà àkókò náà si jẹ òru.
31 Yudase da yolesili asi dagoloba, Yesu E amane sia: i, “Wali Dunu Egefe da Ea hadigi lamu galebe. Dunu Egefe da Gode Ea hadigi olelesa.
Nítorí náà nígbà tí ó jáde lọ tan, Jesu wí pé, “Nísinsin yìí ni a yin Ọmọ Ènìyàn lógo, a sì yin Ọlọ́run lógo nínú rẹ̀.
32 Amaiba: le, Dunu Egefe da Gode Ea Hadigi olelemuba: le, Gode da Dunu Egefe ea Hadigi wahawane olelemu.
Bí a bá yin Ọlọ́run lógo nínú rẹ̀, Ọlọ́run yóò sì yìn ín lógo nínú òun tìkára rẹ̀, yóò sì yìn ín lógo nísinsin yìí.
33 Na manolali! Wali Na da dilima fa: bihadi fawane bu gilisili esalumu. Dilia da Na hogoi helemu. Be Na Yu ouligisu dunu ilima sia: i defele, amo dilima bu sia: sa, ‘Na masunu soge amogai dili masunu da hamedei galebe!
“Ẹ̀yin ọmọ mi, nígbà díẹ̀ sí i ni èmi wà pẹ̀lú yín. Ẹ̀yin yóò wá mi, àti gẹ́gẹ́ bí mo ti wí fún àwọn Júù pé, níbi tí èmi gbé ń lọ, ẹ̀yin kì yóò le wà; bẹ́ẹ̀ ni mo sì wí fún yín nísinsin yìí.
34 Wali, Na da sema gaheabolo dilima olelesa. Dilia dunu eno amo dunu eno ilima asigima. Na dogolegei hou dilima amo defele, dilia enoma enoma asigima.
“Òfin tuntun kan ni mo fi fún yín, kí ẹ̀yin kí ó fẹ́ ọmọnìkejì yín; gẹ́gẹ́ bí èmi ti fẹ́ràn yín, kí ẹ̀yin kí ó sì fẹ́ràn ọmọnìkejì yín.
35 Dunu eno da dunu enoma asigidafa hou hamosea, dunu huluane ilia da dili da Na fa: no bobogesu dunudafa, amo noga: le dawa: mu.”
Nípa èyí ni gbogbo ènìyàn yóò fi mọ̀ pé, ọmọ-ẹ̀yìn mi ni ẹ̀yin ń ṣe, nígbà tí ẹ̀yin bá ní ìfẹ́ sí ọmọ ẹnìkejì yín.”
36 Saimone Bida da Ema adole ba: i, “Hina! Di da habidili masa: bela: ?” Yesu E bu adole i, “Na masunu soge amoga di waha fa: no bobogele doaga: mu gogolesa. Be fa: no amo sogega doaga: musa: , di da Nama fa: no bobogemu.”
Simoni Peteru wí fún un pé, “Olúwa, níbo ni ìwọ ń lọ?” Jesu dá a lóhùn pé, “Níbi tí èmi ń lọ, ìwọ kì yóò lè tẹ̀lé mí nísinsin yìí; ṣùgbọ́n ìwọ yóò tọ̀ mí lẹ́yìn ní ìkẹyìn.”
37 Bida e bu adole ba: i, “Hina! Abuliba: le na da wali Dima fa: no bobogemu da hamedebela: ? Na da Di fidima: ne, na da bogoma: ne momagele esala.”
Peteru wí fún un pé, “Olúwa èéṣe tí èmi kò fi le tọ̀ ọ́ lẹ́hìn nísinsin yìí? Èmi ó fi ẹ̀mí mi lélẹ̀ nítorí rẹ.”
38 Yesu E bu adole i, “Di da dafawane Na fidima: ne bogoma: ne momagebela: ? Na dima dafawane sia: sa. Wali gasia, di da hidadea, ‘Na da Yesu hame dawa: ,’ udiana agoane sia: nanu, fa: no gagala gawali ga: be nabimu.”
Jesu dalóhùn wí pé, “Ìwọ ó ha fi ẹ̀mí rẹ lélẹ̀ nítorí mi? Lóòótọ́ lóòótọ́ ni mo wí fún ọ, àkùkọ kì yóò kọ, kí ìwọ kí ó tó ṣẹ́ mi nígbà mẹ́ta!

< Yone 13 >