< Yelemaia 9 >

1 Na dialuma da si hano amoga nabai ganumu da defea. Amola na si da si hano amoga nabale bubuga: mu da defea. Amai galea, na da eso amola gasia mae fisili, na fi dunu medole legei amo dawa: ma: ne dinanumu defele ba: mu.
Háà! Orí ìbá jẹ́ orísun omi kí ojú mi sì jẹ́ orísun omijé! Èmi yóò sì sọkún tọ̀sán tòru nítorí ìparun àwọn ènìyàn mi.
2 Na da hafoga: i sogega wamoaligisu sogebi lamu hanai gala. Amoga, na da na fi dunu yolesili masunu da defea. Bai na fi dunu huluane da molole fa: no bobogesu hou hame dawa: Ilia huluane da hohonosu dunu.
Háà, èmi ìbá ní ni aginjù ilé àgbàwọ̀ fún àwọn arìnrìn-àjò, kí n ba à lè fi àwọn ènìyàn mi sílẹ̀ kí n sì lọ kúrò lọ́dọ̀ wọn: nítorí gbogbo wọn jẹ́ panṣágà àjọ aláìṣòótọ́ ènìyàn.
3 Ilia da eso huluane ogogomusa: ouesala. Moloidafa hou hame be ogogosu hou fawane da amo soge ouligisa. Hina Gode da amane sia: sa, “Na fi dunu da wadela: i hou afae hamone, bu wadela: i hou eno hamonana. Ilia da Na da ilia Gode hame ilegesa.”
Wọ́n ti pèsè ahọ́n wọn sílẹ̀ bí ọfà láti fi pa irọ́; kì í ṣe nípa òtítọ́ ni wọ́n fi borí ní ilẹ̀ náà. Wọ́n ń lọ láti inú ẹ̀ṣẹ̀ kan sí òmíràn; wọn kò sì náání mi, ní Olúwa wí.
4 Hohonosu hou da bagade. Amaiba: le, dunu huluane afae afae da ea sama amola ea yolali ilia hou dafawaneyale hame dawa: sa. Yolali fi huluane da Ya: igobe defele, ogogosu dawa: Amola dunu huluane da ea na: iyado ea hou baligiduwane sia: sa.
“Ṣọ́ra fún àwọn ọ̀rẹ́ rẹ; má ṣe gbẹ́kẹ̀lé àwọn arákùnrin rẹ. Nítorí pé oníkálùkù arákùnrin jẹ́ atannijẹ, oníkálùkù ọ̀rẹ́ sì jẹ́ abanijẹ́.
5
Ọ̀rẹ́ ń dalẹ̀ ọ̀rẹ́. Kò sì ṣí ẹni tó sọ òtítọ́, wọ́n ti kọ́ ahọ́n wọn láti máa purọ́. Wọ́n sọ ara wọn di onírẹ̀wẹ̀sì pẹ̀lú ẹ̀ṣẹ̀
6 Ilia da ilia sama dunu huluane ilima ogogosa. Amola ilia moloidafa sia: mu hame dawa: Ilia da ogogole sia: ma: ne, ilia gona: su noga: le olelesa, amola ilia wadela: i hou hamonana amo yolesimu ilia hame dawa: Ilia da nimi bagade fasu hou hamonana, amola ogogosu hou hamonana. Hina Gode da amane sia: sa, “Na fi dunu da Na higale yolesi dagoi.”
Ó ń gbé ní àárín ẹ̀tàn; wọ́n kọ̀ láti mọ̀ mí nínú ẹ̀tàn wọn,” ni Olúwa wí.
7 Amaiba: le, Hina Gode Bagadedafa da amane sia: sa, “Na da Na fi dunu ouli adoba: su hou defele, ili adoba: mu. Bai Na fi dunu da wadela: i hou hamoi dagoi. Amaiba: le, Na da adoba: su hou fawane ilima hamomu.
Nítorí náà, èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Àwọn ọmọ-ogun wí: “Wò ó, èmi dán wọn wo; nítorí pé kí ni èmi tún le è ṣe? Nítorí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn ènìyàn mi?
8 Ilia gona: su da medole legesu dadi ganisi defele gala. Ilia da mae fisili, ogogolala. Dunu huluane da ea na: iyadoma asigi sia: sa. Be e da asigi hame - e da ea na: iyado hohonomusa: dawa:
Ahọ́n wọn dàbí ọfà olóró; ó ń sọ ẹ̀tàn. Oníkálùkù sì ń fi ẹnu rẹ̀ sọ̀rọ̀ àlàáfíà sí aládùúgbò rẹ̀, ní inú ọkàn rẹ̀, ó dẹ tàkúté sílẹ̀.
9 Na da ilima se ima: bela: ? Na da ilia wadela: i hou hamoi, amoma dabe ima: bela: ? Dafawane! Na da se ilima imunu. Na, Hina Gode, da sia: i dagoi.”
Èmi kì yóò ha fi ìyà jẹ wọ́n nítorí èyí?” ni Olúwa wí. “Èmi kì yóò ha gbẹ̀san ara mi lórí irú orílẹ̀-èdè yìí bí?”
10 Na (Yelemaia) da amane sia: i, “Na da dimu amola didigia: mu. Bai gisi da bioi dagoi amola goumi da wadela: lesi, amola amo sogega, dunu eno da hame ahoa. Wali ohe fi ilia sia: da hame naba amola sio fi amola sigua ohe huluane da hobea: i dagoi.”
Èmi yóò sì sọkún, pohùnréré ẹkún fún àwọn òkè àti ẹkún ìrora lórí pápá oko aginjù wọ̀n-ọn-nì. Nítorí wọ́n di ahoro, wọn kò sì kọjá ní ibẹ̀. A kò sì gbọ́ igbe ẹran ọ̀sìn. Àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run sì ti sálọ, bẹ́ẹ̀ náà ni àwọn ẹranko sì ti lọ.
11 Hina Gode da amane sia: sa, “Na da Yelusaleme mugululi, e da isu ligisisu bi defele ba: mu. Amo ganodini, sigua wa: me fawane da esalumu. Yuda moilai bai bagade huluane da hafoga: i wadela: i soge ba: mu amola amo ganodini, dunu da hamedafa esalumu.”
“Èmi yóò sì sọ Jerusalẹmu di òkìtì àlàpà àti ihò àwọn ìkookò. Èmi ó sì sọ ìlú Juda di ahoro tí ẹnikẹ́ni kò sì ní le è gbé.”
12 Na da amane adole ba: i, “Hina Gode! Soge da abuliba: le hafoga: i amola wadela: lesi dagoiba: le, dunu huluane da amoga hame ahoa? Amo bai dawa: ma: ne, dunu huluane ilia asigi dawa: su da defele hame. Di da amo ea bai nowama olelebela: ? Dunu afae da eno dunuma alofele olelema: ne, Di da nowama adobela: ?”
Ta ni ẹni náà tí ó ní ọgbọ́n láti mòye nǹkan wọ̀nyí? Ta ni Olúwa ti sọ èyí fún, tí ó sì lè ṣàlàyé rẹ̀? Èéṣe tí ilẹ̀ náà fi ṣègbé bí aginjù, tí ẹnìkankan kò sì le là á kọjá?
13 Hina Gode da amane bu adole i, “Na fi dunu da Na olelesu amo fisi dagoiba: le, amo hou da ilima doaga: i. Ilia da Na sia: nabawane hame hamosu.
Olúwa sì wí pé, nítorí pé wọ́n ti kọ òfin mi sílẹ̀, èyí tí mo gbé kalẹ̀ níwájú wọn, wọn ṣe àìgbọ́ràn sí wọn, wọn kò sì rìn nínú òfin mi.
14 Be ilia dogo da ga: nasi hamone, ilia da ilia eda ilia olelesu defele, Ba: iele ogogosu loboga hamoi ogogosu ‘gode’ ilima nodone sia: ne gadolalusu.
Dípò èyí, wọ́n ti tẹ̀lé agídí ọkàn wọn, wọ́n ti tẹ̀lé Baali gẹ́gẹ́ bí àwọn baba wọn ṣe kọ́ wọn.
15 Amaiba: le nabima! Na, Hina Gode Bagadedafa, Isala: ili fi ilia Gode, Na da agoane hamomu. Na da Na fi ilima gamogai ha: i manu imunu, amola wadela: i medosu hano ili moma: ne imunu.
Nítorí náà, èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run Israẹli wí, “Wò ó, Èmi yóò mú kí àwọn ènìyàn wọ̀nyí jẹ oúnjẹ kíkorò àti láti mu omi májèlé.
16 Ilia da fifi asi gala amo ilia amola ilia aowalalia da musa: hamedafa dawa: i, amo ganodini esaloma: ne, Na da ili afagogomu. Amola ili dafawanedafa wadela: lesima: ne, Na da dadi gagui wa: i gilisi ilima doagala: ma: ne asunasimu.”
Èmi yóò sì tú wọn ká láàrín àwọn orílẹ̀-èdè, nínú èyí tí àwọn tàbí àwọn baba wọn kò mọ̀. Èmi yóò sì lépa wọn pẹ̀lú idà títí èmi yóò fi pa wọ́n run.”
17 Hina Gode Bagadedafa da amane sia: i, “Wali manebe hou dawa: ma! Didigia: su dawa: uda amo didigia: su gesami hea: lala, amo misa: ne sia: ma!
Èyí sì ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun wí: “Sá à wò ó nísinsin yìí! Ké sí obìnrin ti ń ṣọ̀fọ̀ nì kí ó wá; sì ránṣẹ́ pe àwọn tí ó mòye nínú wọn.
18 Yuda dunu ilia da amane sia: i, “Ilia hedolo misini, ninima idigisa gesami hea: ma: ne sia: ma! Amasea, ninia si da si hanoga nabai amola ninia si abo dibi amoga si abo nanegai ba: mu.”
Jẹ́ kí wọn wá kíákíá, kí wọn wá pohùnréré ẹkún lé wa lórí títí ojú wa yóò fi sàn fún omijé tí omi yóò sì máa sàn àwọn ìpéǹpéjú wa.
19 Saione sogega, didigia: su bagade nabima! “Ninia da wadela: lesi dagoi! Ninia da dafawanedafa gogosiasu nabi dagoi. Ninia soge yolesimu. Bai ninia diasu huluane da mugululi, wadela: lesi dagoi.”
A gbọ́ igbe ìpohùnréré ẹkún ní Sioni: ‘Àwa ti ṣègbé tó! A gbọdọ̀ fi ilẹ̀ wa sílẹ̀, nítorí pé àwọn ilé wa ti parun.’”
20 Na da amane sia: i, “Dilia uda! Hina Gode Ea sia: nabima amola noga: le dawa: digima! Dilia idiwi ilima da: i dioi didigia: su hou olelema! Amola dilia na: iyado ilima idigisa gesami hea: su olelema.
Nísinsin yìí, ẹ̀yin obìnrin ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa; ṣí etí yín sí ọ̀rọ̀ ẹnu rẹ. Kọ́ àwọn ọmọbìnrin yín ní ìpohùnréré ẹkún, kí ẹ sì kọ́ ara yín ní arò.
21 Bogosu da ninia fo misa: ne agenesi amoga golili misi amola ninia hina bagade ilia diasuga golili misi. Ninia mano moilai logoga esalebe amola ayeligi bidi lasu sogebi amoga esala, amoga bogosu da doaga: i dagoi.
Ikú ti gba ojú fèrèsé wa wọlé ó sì ti wọ odi alágbára wa ó ti ké àwọn ọmọ kúrò ní àdúgbò àti àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin kúrò ní gbọ̀ngàn ìta gbangba.
22 Bogoi da: i hodo da iga ligisisu defele soge huluane amoga afagogole dialebe. Bogoi da: i hodo da gagoma amo faisu dunu da udigili damuni, amo defele udigili dialebe ba: sa. Hina Gode da amo sia: dilima alofele sia: ma: ne nama sia: i dagoi.”
Sọ pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa wí: “‘Òkú àwọn ènìyàn yóò ṣubú bí ààtàn ní oko gbangba àti bí ìbùkúnwọ́ lẹ́yìn olùkórè láìsí ẹnìkankan láti kó wọn jọ.’”
23 Hina Gode da amane sia: sa, “Bagade dawa: su dunu da ilia asigi dawa: su dawa: beba: le, hidale sia: mu da defea hame. Amola gasa bagade dunu ilia gasa dawa: beba: le, hidale sia: mu da defea hame. Amola bagade gagui dunu ilia muni amola liligi dawa: beba: le, hidale sia: mu da defea hame.
Èyí ni ohun tí Olúwa wí: “Má ṣe jẹ́ kí ọlọ́gbọ́n yangàn nítorí agbára ọgbọ́n rẹ̀, tàbí alágbára nítorí agbára rẹ̀, tàbí ọlọ́rọ̀ nítorí ọrọ̀ rẹ̀.
24 Nowa da hidale sia: musa: dawa: sea, e da Na dawa: amola Na hou dawa: amo fawane hidale sia: mu da defea. Bai Na asigi hou da eso huluane diala. Amola Na da hou moloidafa fawane hamosa. Agoaiwane hou fawane, Na da hahawane ba: sa. Na, Hina Gode, da sia: i dagoi.”
Ẹ jẹ́ kí ẹni tí ń ṣògo nípa èyí nì wí pé: òun ní òye, òun sì mọ̀ mí wí pé, Èmi ni Olúwa tí ń ṣe òtítọ́, ìdájọ́ àti òdodo ní ayé, nínú èyí ni mo ní inú dídùn sí,” Olúwa wí.
“Ọjọ́ ń bọ̀,” ni Olúwa wí, “tí Èmi yóò fi ìyà jẹ gbogbo àwọn tí a kọ ilà fún nínú ara nìkan.
26 Hina Gode da amane sia: sa, “Eso da doaga: mu, amoga Na da dunu fi huluane Idibidi, Yuda, Idome, A:mone, Moua: be amola hafoga: i soge esalebe dunu (amo da ilia ogogosu ‘gode’ ilima nodone dawa: ma: ne ilia dialuma hinabo dadamusa) amo dunu huluane ilima se imunu. Amo dunu huluane da ilia gadofo damui dagoi ba: sa. Gadofo damusu da Na Gousa: su amo ea dawa: digima: ne olelesu. Be ilia da Na Gousa: su hamedafa dawa: digisa. Amo dunu huluane amola Isala: ili dunu da Na Gousa: su hamedafa dawa: digisa.”
Ejibiti, Juda, Edomu, Ammoni, Moabu àti gbogbo àwọn tí ń gbé ní ọ̀nà jíjìn réré ní aginjù. Nítorí pé gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè wọ̀nyí jẹ́ aláìkọlà gbogbo àwọn ará ilé Israẹli sì jẹ́ aláìkọlà ọkàn.”

< Yelemaia 9 >