< Yelemaia 50 >

1 Hina Gode da Ba: bilone moilai bai bagade fi ilima Ea sia: ne iasu ilegei amo nama amane olelei,
Èyí ni ọ̀rọ̀ tí Olúwa fi sẹ́nu wòlíì Jeremiah láti sọ fún ará ilẹ̀ Babeli:
2 “Fifi asi gala ilima olelema! Ha: giwane sisia: ma! Dawa: digima: ne hahamosu olelelalu, sisia: ma! Amo sia: mae wamolegema! Ba: bilone da dafai dagoi! Ea ogogosu ‘gode’ Madage da goudane sali! Ba: bilone loboga hamoi ogogosu ‘gode’ da gogosiasu lai dagoi! Ea wadela: idafa loboga hamoi ‘gode’ huluane da goudai dagoi!
“Ẹ sọ ọ́ láàrín àwọn orílẹ̀-èdè, ẹ sì kéde, kí ẹ sì gbé àsíá sókè, ẹ kéde rẹ̀ ẹ má sì ṣe bò ó, wí pé, ‘A kó Babeli, ojú tí Beli, a fọ́ Merodaki túútúú, ojú ti àwọn ère rẹ̀, a fọ́ àwọn òrìṣà rẹ̀ túútúú.’
3 Gagoe (north) esalebe fi da Ba: bilone fi ilima doagala: musa: amola hafoga: i soge defele hamoma: ne wadela: musa: , misi dagoi. Dunu amola ohe da hobeamu, amola dunu da amogawi bu hame esalebe ba: mu.”
Àwọn ìlú ní apá àríwá yóò sì máa gbóguntì wọ́n. Gbogbo àwọn ènìyàn àti ẹranko ni yóò sá kúrò ní ìlú yìí.
4 Hina Gode da amane sia: sa, “Amo eso doaga: sea, Isala: ili fi dunu amola Yuda fi dunu da gilisili, diginiwane, Na, ilia Gode, amo bu hogomusa: misunu.
“Ní ọjọ́ wọ̀nyí àti ní àkókò náà,” ni Olúwa wí, “Àwọn ọmọ Israẹli yóò jùmọ̀ wá, àwọn, àti àwọn ọmọ Juda, wọn yóò lọ pẹ̀lú ẹkún láti ṣàfẹ́rí Olúwa Ọlọ́run wọn.
5 Ilia da Saione Goumi amoga ahoasu logo Nama adole ba: mu. Amola ilia da amo logoga masunu. Ilia da eso huluane dialoma: ne Gousa: su Nama hamomu, amola ilia da amo hamedafa fimu.
Wọn ó máa béèrè ọ̀nà Sioni, ojú wọn yóò sì yí síhà ibẹ̀, wí pé ẹ wá, ẹ jẹ́ kí a darapọ̀ mọ́ Olúwa ní májẹ̀mú ayérayé, tí a kì yóò gbàgbé.
6 Na fi dunu da sibi amo ilia ouligisu dunu da noga: le hame ouligibiba: le, goumia fisi dagoi agoane ba: sa. Ilia da sibi agoane, goumi afae yolesili, eno goumia ahoasu, agoane asili, ilia da ilia sogebidafa amo gogolei dagoi.
“Àwọn ènìyàn mi ti jẹ́ àgùntàn tí ó sọnù, àwọn olùṣọ́-àgùntàn wọn ti jẹ́ kí wọn ṣìnà, wọ́n ti jẹ́ kí wọn rìn lórí òkè wọ́n ti lọ láti orí òkè ńlá dé òkè kékeré, wọn ti gbàgbé ibùsùn wọn.
7 Nowa da ili ba: sea da ilima doagala: sa. Ilia ha lai da amane sia: sa, ‘Ilia da ilia Hina Godema wadela: le hamoi dagoi. Amaiba: le, ninia da ilima doagala: mu da defea, wadela: i hame. Ilia aowa fi da Hina Gode Ea hou dafawaneyale dawa: i. Ilia amola da mae yolesili, Ema fa: no bobogemu da defea galu.’
Gbogbo àwọn tí ó rí wọn, ti pa wọ́n jẹ àwọn ọ̀tá wọ́n sì wí pé, ‘Àwa kò jẹ̀bi nítorí pé wọ́n ti ṣẹ̀ sí Olúwa ibùgbé òdodo àti ìrètí àwọn baba wọn.’
8 Isala: ili fi dunu! Ba: bilone soge yolesili, hobeama! Dilia degabo amo soge yolesima!
“Jáde kúrò ní Babeli, ẹ fi ilẹ̀ àwọn ará Kaldea sílẹ̀, kí ẹ sì jẹ́ bí òbúkọ níwájú agbo ẹran.
9 Na da gagoe (north) esalebe fi gilisisu ilima sia: beba: le, ilia da Ba: bilone amoga doagala: musa: misunu. Ilia da gegemusa: dadalele, Ba: bilone fi ilima doagala: le, hasalimu. Ilia da benea ahoasu dunu noga: idafa. Ilia dadiga gala: sea, giadofamu hame dawa:
Nítorí pé èmi yóò ru, bẹ́ẹ̀ ni èmi yóò gbé sókè sí Babeli àwọn orílẹ̀-èdè ńlá láti ilẹ̀ àríwá. Wọn yóò gba àyà wọn lẹ́gbẹ́ rẹ̀; láti àríwá wá, à ó sì mú ọ. Ọfà wọn yóò dàbí ọfà àwọn akọni akíkanjú tí wọn kì í wà lọ́wọ́ òfo.
10 Ilia da Ba: bilone fi ilia liligi huluane gesowale lamu. Ilia hanai liligi ilia da udigili lamu. Na, Hina Gode, da sia: i dagoi.”
A ó dààmú Babeli, gbogbo àwọn tó dààmú rẹ yóò sì mú ìfẹ́ wọn ṣẹ,” ni Olúwa wí.
11 Hina Gode da amane sia: sa, “Ba: bilone fi dunu! Dilia da Na fi dunu ilima doagala: le, ilia liligi huluane gesowale lai dagoi. Dilia da hahawane ahoa. Fedege agoane, dilia da bulamagau amo gagoma ha: i manu lamusa: ososa: gisa o hosi amo da gogona: ahoabe, agoane ba: sa.
“Nítorí pé inú yín dùn nítorí pé ẹ̀yìn yọ̀, ẹ̀yìn olè tí ó jí ìní mi, nítorí tí ẹ̀yìn fi ayọ̀ fò bí ẹgbọrọ abo màlúù sí koríko tútù, ẹ sì ń yan bí akọ ẹṣin.
12 Be dilia moilai bai bagade (Ba: bilone) da dafane gogosia: i dagoi ba: mu. Amola Ba: bilone fi da fifi asi gala amo ganodini gududafa dialebe ba: mu. Ba: bilone soge da wadela: i hafoga: i soge hamoi dagoi ba: mu.
Ojú yóò ti ìyá rẹ, ẹni tí ó bí ọ yóò sì gba ìtìjú. Òun ni yóò jẹ́ kékeré jù nínú àwọn orílẹ̀-èdè, ilẹ̀ aṣálẹ̀ àti aginjù tí kò lọ́ràá.
13 Bai Na da ougi bagadeba: le, dunu afae Ba: bilone soge ganodini esalebe da hame ba: mu. Ba: bilone da mugului dagoi dialebe ba: mu, amola nowa dunu da amo soge baligimusa: ahoasea, da bagadewane fofogadigimu.
Nítorí ìbínú Olúwa, kì yóò ní olùgbé; ẹnikẹ́ni kò sì ní gbé inú rẹ̀. Gbogbo àwọn tí ó bá kọjá ni Babeli yóò fi ṣe yẹ̀yẹ́ nítorí ọgbẹ́ rẹ̀.
14 Dilia dadi gagui dunu! Ba: bilone amoma doagala: musa: dadalema! E eale sisiga: ma! Dilia dadi huluane amoga, e gala: ma! Bai Ba: bilone fi da Na, Hina Gode, Nama wadela: le hamoi.
“Dúró sí ààyè rẹ ìwọ Babeli àti gbogbo ẹ̀yin tí ẹ n ta ọfà náà. Ẹ ta ọfà náà sí i, nítorí ó ti ṣẹ̀ sí Olúwa.
15 Moilai bai bagade amo eale sisiga: le, gegemusa: halama! Wali Ba: bilone da fama: ne olei dagoi! Ea gagoi dobea da fili, mugului dagoi ba: sa. Na da Ba: bilone fi ilima dabe iaha. Amaiba: le, ha lai dunu! Ilima dabe ima! Ilia da eno dunuma hamoi, amo defele, ilima dabe bu ima.
Kígbe mọ́ ọn ní gbogbo ọ̀nà! Ó tẹríba, òpó rẹ̀ sì yẹ̀, níwọ̀n ìgbà tí ó ti jẹ́ wí pé èyí ni ìgbẹ̀san Olúwa, gbẹ̀san lára rẹ̀. Ṣe sí i gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣe sí àwọn ẹlòmíràn.
16 Amo soge ganodini, ha: i manu bugima: ne amola faima: ne logo mae doasima! Ga fi dunu Ba: bilone soge ganodini esala, ilia da dadi gagui wa: i Ba: bilone fi ilima doagala: musa: manebe, ilima beda: iba: le, hi sogega bu masunu.”
Ké afúnrúgbìn kúrò ní Babeli, àti ẹni tí ń di dòjé mú ní igà ìkórè! Nítorí idà àwọn aninilára jẹ́ kí oníkálùkù padà sí ọ̀dọ̀ àwọn ènìyàn rẹ̀, kí oníkálùkù sì sá padà sí ilẹ̀ rẹ̀.
17 Hina Gode da amane sia: sa, “Isala: ili fi dunu da sibi amo laione wa: mega sefasi amola afagogoi dagoi, amo agoane ba: sa. Degabo, Asilia hina bagade da ilima doagala: i. Amasea, fedege agoane, Ba: bilone hina bagade Nebiuga: denese, da ilia gasa gagisu.
“Israẹli jẹ́ àgùntàn tí ó ṣìnà kiri, kìnnìún sì ti lé e lọ. Níṣàájú ọba Asiria pa á jẹ, àti níkẹyìn yìí Nebukadnessari ọba Babeli fa egungun rẹ̀ ya.”
18 Amaiba: le, Na, Hina Gode Bagadedafa, Isala: ili fi ilia Gode, da Asilia hina bagade ema se iasu defele, hina bagade Nebiuga: denese amola ea fi ilima se imunu.
Nítorí náà, èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Alágbára, Ọlọ́run Israẹli wí, “Ǹ ó fi ìyà jẹ ọba Babeli àti ilẹ̀ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí mo ti ṣe fìyà jẹ ọba, Asiria.
19 Na da Isala: ili fi ilia sogega buhagima: ne, logo doasimu. Ilia da ha: i manu amo da Gamele Goumia amola Ba: isia: ne sogega heda: lebe amo manu, amola ha: i manu bugi Ifala: ime soge amola Gilia: de sogega gala, amoga ilia hanaiga defele manu.
Ṣùgbọ́n, èmi yóò mú Israẹli padà wá pápá oko tútù rẹ̀ òun yóò sì máa bọ́ ara rẹ̀ lórí Karmeli àti Baṣani, a ó sì tẹ́ ọkàn rẹ̀ lọ́rùn ní òkè Efraimu àti ní Gileadi.
20 Amo eso da doaga: sea, Isala: ili fi amola Yuda fi amo ganodini da wadela: i hou dialebe hame ba: mu. Bai dunu amo ilia esalusu Na da gaga: i, ilia wadela: i hou amola Na da gogolema: ne olofomu. Na, Hina Gode, da sia: i dagoi.”
Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì,” ni Olúwa wí, “À ó wá àìṣedéédéé ẹ̀ṣẹ̀ Israẹli, ṣùgbọ́n a ki yóò rí ohun; àti ẹ̀ṣẹ̀ Juda ni a ki yóò sì rí mọ kankan nítorí èmi yóò dáríjì àwọn tí ó ṣẹ́kù tí mo dá sí.
21 Hina Gode da amane sia: sa, “Melada: ime fi amola Bigode fi (ela da Ba: bilone fi) ilima doagala: ma! Ilia huluane medole legele wadela: lesima! Na sia: i liligi huluane hamoma! Na, Hina Gode, da sia: i dagoi.
“Kọlu ilẹ̀ Merataimu àti àwọn tí ó ń gbé ní Pekodi. Lépa rẹ pa, kí o sì parun pátápátá,” ni Olúwa wí, “Ṣe gbogbo ohun tí mo pàṣẹ fún ọ.
22 Ba: bilone soge ganodini gegemusa: ha lasu da naba. Amola wadela: su bagade ba: sa.
Ariwo ogun wà ní ilẹ̀ náà ìrọ́kẹ̀kẹ̀ ìparun ńlá.
23 Ba: bilone da ‘ha: ma’ (hammer) agoane, fifi asi gala huluane fifima: ne fananu. Be wali amo ‘ha: ma’ da fifilasi dagoi. Ema doaga: i hou ba: beba: le, fifi asi gala huluane da bagadewane fofogadigisa.
Báwo ni ó ṣe fọ́, tí ó sì pín yẹ́lẹyẹ̀lẹ tó, lọ́wọ́ òòlù gbogbo ayé! Báwo ní Babeli ti di ahoro ni àárín àwọn orílẹ̀-èdè.
24 Ba: bilone fi! Dilia da nama gegenanu. Be wali dilia da sani amo Na da dili sa: ima: ne gei, amoga sa: i dagoi. Dilia da mae dawa: iwane amoga sa: i dagoi.
Mo dẹ pàkúté sílẹ̀ fún ọ ìwọ Babeli, kí o sì tó mọ ohun tí ó ń ṣẹlẹ̀, o ti kó sínú rẹ̀. A mú ọ nítorí pé o tako Olúwa.
25 Na da Na gegesu liligi lidiligalei diasu amo doasili amola Na da ougiba: le, amo liligi gagui dagoi. Bai Na, Ouligisu Hina Gode Bagadedafa, da Ba: bilone sogega hawa: hamomu galaiou.
Olúwa ti kó àwọn ohun èlò ìjà rẹ̀ jáde, nítorí pé Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun ti ṣiṣẹ́ ní ilẹ̀ Babeli.
26 La: ididili huluane amoga Ba: bilonema doagala: ma! Ea widi amola gagoma legesu diasu fima! Lai liligi amo widi lelegela heda: i agoane lelegela heda: ma! Soge wadela: ma! Liligi huluanedafa wadela: lesima!
Ẹ wá sórí rẹ̀ láti òpin gbogbo, sí ilé ìṣúra rẹ̀ sílẹ̀, ẹ kó o jọ bí òkìtì ọkà, kí ẹ sì yà á sọ́tọ̀ fún ìparun, ẹ má ṣe fí yòókù sílẹ̀ fún un.
27 Ba: bilone dadi gagui dunu huluane medole legema! Medole legema! Ba: bilone dunu da wadela: lesi dagoi ba: mu! Ilima se iasu eso da doaga: i dagoi.
Pa gbogbo àwọn akọ màlúù rẹ, jẹ́ kí a kó wọn lọ ibi tí a ó ti pa wọ́n! Ègbé ní fún wọn! Nítorí ọjọ́ wọn dé, àkókò ìbẹ̀wò wọn.
28 (Mugululi asi dunu da Ba: bilone soge yolesili, hobeale, Yelusaleme diasuga doaga: sa. Ilia da sia: ne iasu amo ninia Hina Gode da Ba: bilone dunu ilima dabe i dagoi - bai ilia da Ea Debolo diasu wadela: lesi - amo ilia da olelesa.)
Gbọ́ ohùn àwọn tí ó sálọ, tí ó sì sálà láti Babeli wá, sì sọ ní Sioni, bí Olúwa Ọlọ́run wa ti gbẹ̀san, ẹ̀san fún tẹmpili rẹ̀.
29 Dadi gagui dunu ilima ilia Ba: bilone fi doagala: ma: ne sia: ma! Dunu huluane amo da dadiga gala: su dawa: , amo gadili asunasima! Moilai sisiga: le, dunu afae mae hobeama: ne, logo huluane ga: ma! Ba: bilone fi ilima dabe ima. Ilia hou eno fi ilima hamoi, amo defele ilima hamoma! Bai ilia da Na, Isala: ili ilia Hadigi Gode, Nama gasa fili hamoi.
“Pe ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn, àní gbogbo tafàtafà, sórí Babeli, ẹ dó tí ì yíkákiri, ma jẹ́ ki ẹnikẹ́ni sálà. Sán fún un gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bi gbogbo èyí tí ó ti ṣe, ẹ ṣe bẹ́ẹ̀ sí i, nítorí tí ó ti gbéraga sí Olúwa, sí Ẹni Mímọ́ Israẹli.
30 Amaiba: le, ilia ayeligi dunu da moilai logoga medole legei dagoi ba: mu. Amola amo esoga, ilia dadi gagui dunu da medole legei dagoi ba: mu. Na, Hina Gode, da sia: i dagoi.
Nítorí náà, àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ yóò ṣubú ní ìgboro, a ó sì pa àwọn ológun lẹ́nu mọ́,” ní Olúwa wí.
31 Ba: bilone! Di da gasa fi hou amoga nabai gala. Amaiba: le, Na, Ouligisudafa Hina Gode Bagadedafa, da dima ha lai hamoi dagoi. Na da dima se imunu eso ilegei, amo da doaga: i dagoi.
“Wò ó, èmi yóò dojú kọ ọ́ ìwọ agbéraga,” ni Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí, “nítorí ọjọ́ rẹ ti dé, àkókò tí èmi ó bẹ̀ ọ wò.
32 Dia hidale hamosu gasa fi da sadenane dafamu. Amola, dunu eno di wa: legadolesimu hamedafa ba: mu. Na da dia moilai bai bagade huluane laluga ulagimu. Amola liligi huluane sisiga: le dialebe da wadela: lesi dagoi ba: mu.”
Onígbèéraga yóò kọsẹ̀, yóò sì ṣubú, kì yóò sì ṣí ẹni tí yóò gbé dìde. Èmi yóò tan iná ní ìlú náà, èyí tí yóò sì jo run.”
33 Hina Gode Bagadedafa da amane sia: sa, “Isala: ili fi amola Yuda fi da banenesiwane esalebe ba: sa. Dunu amo da ili gagulaligi, da ili ha: giwane sosodo aligisa. Amola ilia da ili se iasu udigili hawa: hamosu logo doasimusa: hame dawa:
Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun sọ: “A pọ́n àwọn ènìyàn Israẹli lójú àti àwọn ènìyàn Juda pẹ̀lú. Gbogbo àwọn tí ó kó wọn nígbèkùn dì wọn mú ṣinṣin wọn kò sì jẹ́ kí ó sá àsálà.
34 Be ilia gaga: su dunu da gasa bagadewane esala. Ea dio da Hina Gode Bagadedafa. Hisu da ilimagale gegemu. E da osobo bagade fifi asi gala ilima olofosu iasimu. Be E da Ba: bilone fi ilima bidi hamosu iasimu.”
Síbẹ̀, Olùràpadà wọn, Alágbára, Olúwa Ọlọ́run Alágbára ni orúkọ rẹ̀. Yóò sì gbe ìjà wọn jà, kí ó ba à lè mú wọn wá sinmi ní ilẹ̀ náà; ṣùgbọ́n kò sí ìsinmi fún àwọn tí ó ń gbé Babeli.
35 Hina Gode da amane sia: sa, “Ba: bilone soge da bogosu ba: ma! Ea fi dunu amola ouligisu dunu amola bagade dawa: su dunu da bogosu ba: mu.
“Idà lórí àwọn Babeli!” ni Olúwa wí, “lòdì sí àwọn tó ń gbé ní Babeli, àwọn aláṣẹ àti àwọn amòye ọkùnrin.
36 Ea ogogosu balofede dunu da bogosu ba: mu. Ilia da gagaoui dunu. Ea dadi gagui dunu da bogosu ba: mu. Ilia da bagadewane beda: i.
Idà lórí àwọn wòlíì èké wọn yóò di òmùgọ̀! Idà lórí àwọn jagunjagun, wọn yóò sì kún fún ẹ̀rù.
37 Ea hosi amola sa: liode huluane wadela: lesima! Ea ga fi muni lama: ne hawa: hamosu dadi gagui dunu da bogosu ba: mu. Ilia da gasa hamedafa ba: sa. Ba: bilone liligi ida: iwane gala huluane wadela: lesima! Huluane gesowale lale dagoma!
Idà lórí àwọn kẹ̀kẹ́-ẹṣin rẹ̀ àti àwọn àjèjì nínú ẹgbẹ́ rẹ̀. Wọn yóò di obìnrin. Idà lórí àwọn ohun ìṣúra rẹ̀!
38 Ea sogega esoi bagade iasima. Ea hano huluane hafoga: ma! Ba: bilone soge ganodini da loboga hamoi ogogosu ‘gode’ bagohame. Ea fi dunu da ilima beda: iba: le, gagaoui agoane ba: sa.
Ilẹ̀ gbígbẹ lórí omi rẹ̀; yóò sì gbẹ. Nítorí pé ó jẹ́ ilẹ̀ àwọn ère, àwọn ère tí yóò ya òmùgọ̀ pẹ̀lú ẹ̀rù.
39 Amaiba: le, Ba: bilone soge ganodini, Fio liligi amola wadela: i a: silibu amola ledo hamoi sio bagohame ba: mu. Dunu fi da amo soge ganodini hamedafa esalumu.
“Nítorí náà àwọn ẹranko ijù pẹ̀lú ọ̀wàwà ni yóò máa gbé ibẹ̀, abo ògòǹgò yóò sì máa gbé inú rẹ̀, a kì yóò sì gbé inú rẹ̀ mọ́, láéláé, bẹ́ẹ̀ ni a kì yóò ṣàtìpó nínú rẹ̀ láti ìrandíran.
40 Musa: hemonega, Na da Sodame amola Goumola amola amo sisiga: le dialebe moilai fonobahadi huluane amo wadela: lesi dagoi. Amo hou defele da Ba: bilone fi ilima doaga: mu. Dunu afae da amo ganodini wali amola eso huluane hame esalebe ba: mu. Na, Hina Gode, da sia: i dagoi.
Gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti gba ìjọba Sodomu àti Gomorra pẹ̀lú àwọn ìlú agbègbè wọn,” ni Olúwa wí, “torí náà kò sí ẹnikẹ́ni tí yóò gbé ibẹ̀; ènìyàn ki yóò gbé nínú rè.
41 Gagoe (north) soge amoga fi bagadedafa da gegemusa: manebe. Hina bagade bagohame da gegemusa: momagesa.
“Wò ó! Ọ̀wọ́ ọmọ-ogun láti ìhà àríwá; orílẹ̀-èdè ńlá àti àwọn ọba púpọ̀ ni à ń gbé dìde láti òpin ilẹ̀ ayé.
42 Ilia da ilia dadi amola gegesu gobihei gagui dagoi. Ilia da nimi bagade hame asigi dunu. Ilia da hosi da: iya fila heda: le ahoasea, ilia ha lasu da hano wayabo bagade ea gafululi fugala: sa agoane naba. Ilia da Ba: bilone fi ilima doagala: musa: momagei dagoi.
Wọ́n sì di ìhámọ́ra ọ̀kọ̀ àti ọrun, wọ́n burú wọn kò sì ní àánú. Wọ́n n ké bí i rírú omi bí wọ́n ti ṣe ń gun ẹṣin wọn lọ. Wọ́n wá bí àkójọpọ̀ ogun láti kọlù ọ́, ìwọ ọmọbìnrin Babeli.
43 Ba: bilone hina bagade da ilia manebe sia: nabasea, ea lobo da bodola: le gudusa. E da uda da mano lalelegemu gadenesea se naba, amo defele e da se naba.
Ọba Babeli ti gbọ́ ìròyìn nípa wọn, ọwọ́ wọn sì rọ, ìrora mú wọn bí obìnrin tí ó ń rọbí.
44 Laione wa: me da Yodane Hano bega: iwila amo yolesili, bulamagau ha: i manu mola: ya: i gisi soge amoga manebe, amo defele Na, Hina Gode da Ba: bilone dunu ilima doagala: musa: misunu. Amasea, Ba: bilone dunu da ilia moilai yolesili, hobeamu. Nowa da Na agoanela: ? Nowa da Nama doagala: mu dawa: bela: ? Nowa ouligisu dunu da Nama gegemusa: dawa: bela: ? Nama hasalasimu da hamedeidafa.
Bí i kìnnìún ni òun ó gòkè wá láti igbó Jordani sí orí ilẹ̀ ọlọ́ràá, Èmi ó lé Babeli kúrò ní ilẹ̀ rẹ̀ ní kíákíá. Ta ni àyànfẹ́ náà tí èmi ó yàn sórí rẹ̀? Ta ló dàbí mi, ta ni ó sì pé mi ṣe ẹlẹ́rìí? Ta ni olùṣọ́-àgùntàn náà tí yóò le dúró níwájú mi?”
45 Amaiba: le, Na da Ba: bilone soge amola ea fi dunu ilima hamoma: ne ilegesu amo nabima! Ilia huluane amola ilia mano da ga hiouginana asi dagoi ba: mu. Amasea, dunu huluane da bagadewane beda: mu.
Nítorí náà, gbọ́ ohun tí Olúwa sọ nípa Babeli, ẹni tí ó gbìmọ̀ lòdì sí Babeli: n ó sì pa agbo ẹran wọn run.
46 Ba: bilone da dafasea, sia: bagade nababeba: le, osobo bagade da igugumu. Amola fifi asi gala huluane da ilia beda: ga wele sia: nebe nabimu.
Ní ohùn igbe ńlá pé; a kò Babeli, ilẹ̀ ayé yóò mì tìtì, a sì gbọ́ igbe náà láàrín àwọn orílẹ̀-èdè.

< Yelemaia 50 >