< Yelemaia 49 >

1 Hina Gode da A: mone fi ilia hou dawa: le, amane sia: i, “Isala: ili dunu da habila: ? Ilia soge gaga: ma: ne, dunu da hame esalabala? Abuliba: le ilia da dunu fi amo da ogogosu ‘gode’ Moulegema nodone sia: ne gadosa, amo Ga: de soge esaloma: ne lamusa: , logo doasibala: ?
Nípa Ammoni. Báyìí ni Olúwa wí, “Israẹli kò ha ní ọmọkùnrin? Israẹli kò ha ní àrólé bí? Nítorí kí ni Malkomu ṣe jogún Gadi? Kí ló dé tí àwọn ènìyàn rẹ̀ ń gbé ìlú rẹ̀?
2 Be eso da misunu, amoga, Na hamobeba: le, moilai bai bagade La: ba amo ea fi dunu da gegemusa: ha lasu nabimu. Amasea, La: ba da mugului dagoi amola ea moilai fonobahadi sisiga: le diala amo laluga nei dagoi ba: mu. Amasea, Isala: ili fi dunu da ilia soge bu samogemu.
Ṣùgbọ́n ọjọ́ náà ń bọ̀,” ni Olúwa wí; “nígbà tí èmi yóò mú kí a gbọ́ ìdágìrì ogun ní Rabba tí Ammoni; yóò sì di òkìtì ahoro, gbogbo ìlú tí ó yí i ká ni a ó jó níná. Nígbà náà ni Israẹli yóò lé wọn, àwọn tí ó ti lé e jáde,” ni Olúwa wí.
3 Hesiabone fi dunu! Wele sia: ma! A: iai moilai bai bagade da wadela: lesi dagoi. La: ba uda dilia! Didigia: ma! Wadela: i eboboi abula salawane, da: i dione didigia: ma! Udigili gagoudusa: ili hehenama! Dilia ogogosu ‘gode’ Moulege amola ea gobele salasu amola ouligisu dunu da gilisili gadili mugululi asi dagoi ba: mu.
“Hu, ìwọ Heṣboni, nítorí Ai tí rún! Kígbe ẹ̀yin olùgbé Rabba! Ẹ wọ aṣọ ọ̀fọ̀ kí ẹ sì ṣọ̀fọ̀. Ẹ sáré sókè sódò nínú ọgbà, nítorí Malkomu yóò lọ sí ìgbèkùn, pẹ̀lú àwọn àlùfáà àti ìjòyè rẹ̀.
4 Dilia hohonosu dunu da abuliba: le hidale sia: sala: ? Dilia gasa da fisilala. Dilia abuliba: le dilia gasa bagadeba: le, dunu eno da dilima beda: iba: le, dilima hame doagala: mu, amo dafawaneyale dawa: beba: le, sia: dalala: ?
Èéṣe tí ìwọ fi ń ṣògo nínú àfonífojì rẹ, ṣògo nínú àfonífojì rẹ fún èso? Ẹ̀yin ọmọbìnrin Ammoni aláìṣòótọ́, ẹ gbẹ́kẹ̀lé ọrọ̀ yín, ẹ sì wí pé, ‘Ta ni yóò kò mí lójú?’
5 Na da ilegeiba: le, beda: su da dilima sisiga: mu. Dilia da hobeamu. Dunu afae afae da hi esalusu gaga: ma: ne hobeamu. Amola dilia dadi gagui dunu bu gilisimusa: , dunu afae da hame ba: mu.
Èmi yóò mu ẹ̀rù wá lórí rẹ láti ọ̀dọ̀ gbogbo àwọn tó yí ọ ká,” ni Olúwa, ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
6 Be amogalu fa: no agoane, Na da A: mone bu bagade gaguiwane hamomu. Na, Hina Gode, da sia: i dagoi.”
“Olúwa àwọn ọmọ-ogun. Gbogbo yín ni ó lé jáde, kò sì ṣí ẹnìkan tí yóò dá ìkólọ Ammoni padà,” ni Olúwa wí.
7 Hina Gode Bagadedafa da Idome fi ilia hou dawa: le, amane sia: i, “Idome fi dunu da ilia noga: i asigi dawa: su fisibala: ? Ilia fada: i sia: su dunu da ilima fada: ne sia: mu gogoleila: ? Ilia asigiga dawa: digisu huluane da fisi dagobela: ?
Nípa Edomu. Èyí ní ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí: “Ṣe kò ha sí ọgbọ́n mọ́ ni Temani? Ṣé a ti ké ìmọ̀ràn kúrò ní ọ̀dọ̀ olóyè? Ṣé ọgbọ́n wọn ti bàjẹ́ bí?
8 Dida: ne dunu! Sinidigili, hobeama! Na da Iso egaga fi amo wadela: lesimu. Bai ilima se imunu eso ilegei da doaga: i dagoi.
Yípadà kí o sálọ, sá pamọ́ sínú ihò, ìwọ tí ó ń gbé ní Dedani, nítorí èmi yóò mú ibi wá sórí Esau, ní àkókò tí èmi ó bẹ̀ ẹ́ wò.
9 Dunu da waini fage faisia, ilia waini fage afae afae waini efega yolesisa. Amola wamolasu dunu da gasia masea, ilia hanai liligi fawane laha.
Tí àwọn tí ń ṣa èso bá tọ̀ ọ́ wá; ǹjẹ́ wọn kò ní fi èso díẹ̀ sílẹ̀? Tí olè bá wá ní òru; ǹjẹ́ wọn kò ní kó gbogbo ohun tí wọ́n bá fẹ́?
10 Be Na da Iso egaga fi huluanedafa fadegai dagoi. Amola Na da ilia wamoaligisu dedebosu huluane, amo ilia bu wamoaligimu hamedei ba: ma: ne, fadegai dagoi. Idome dunu fi huluane da wadela: lesi dagoi. Afae esalebe hame ba: sa.
Ṣùgbọ́n èmi yóò tu Esau sí ìhòhò, èmi ti fi ibi ìkọ̀kọ̀ rẹ̀ hàn, nítorí kí o máa ba à fi ara rẹ pamọ́. Àwọn ọmọ rẹ, ẹbí rẹ àti àwọn ará ilé rẹ yóò parun. Wọn kò sì ní sí mọ́.
11 Dilia guluba: mano huluane Na ouligima: ne yolesima! Dilia didalo uda! Mae dawa: ma! Na da dili noga: le ouligimu.
Fi àwọn ọmọ aláìní baba sílẹ̀ èmi yóò dáàbò bo ẹ̀mí wọn. Àwọn opó rẹ gan an lè gbẹ́kẹ̀lé mi.”
12 Dunu eno da wadela: i hou hame hamosu, amo da se iasu lai dagoi. Amaiba: le, dilia da abuliba: le se iasu hame ba: mu dawa: sala: ? Hame mabu! Dilia da se iasu dafawane ba: mu.
Èyí ni ohun tí Olúwa wí bí ẹnikẹ́ni tí kò bá yẹ kí ó mu ago náà bá mú un, kí ló dé tí ìwọ yóò fi lọ láìjìyà? Ìwọ kò ní lọ láìjìyà; ṣùgbọ́n ìwọ yóò mú un.
13 Na Nisu da ilegei dagoi. Bosela da wadela: i hafoga: i soge agoane ba: mu. Dunu eno da amo beda: iwane fofogadigili ba: muba: le, ilia da ema oufesega: ne, amo ea dioba: le, gagabusu aligima: ne ilegemu. Moilai gagai fonobahadi amo huluane ema gadenene diala da mugululi dagole, eso huluane amaiwane dialebe ba: mu. Na, Hina Gode, da sia: i dagoi.”
Èmi fi ara mi búra ni Olúwa wí, wí pé, “Bosra yóò ba ayé ara rẹ̀ jẹ́. Yóò di ẹni ẹ̀gàn, ẹni èpè àti ẹni ègún, àti gbogbo ìlú rẹ̀ yóò di ìbàjẹ́ títí láé.”
14 Na (Yelemaia) da amane sia: i, “Idome fi dunu! Hina Gode da nama sia: i dagoi. E da sia: adole iasu dunu amo fifi asi gala ilia dadi gagui wa: i gilisili, dilima doagala: musa: momagema: ne amo adomusa: asunasi.
Ní gbígbọ́, èmi ti gbọ́ ìró kan láti ọ̀dọ̀ Olúwa, a rán ikọ̀ kan sí orílẹ̀-èdè pé, ẹ kó ara yín jọ, ẹ wá sórí rẹ̀, ẹ sì dìde láti jagun.
15 Hina Gode da hamobeba: le, dilia da gasa hame ba: mu. Amasea, dunu eno da dilima hame nodomu.
“Ní báyìí, èmi yóò sọ ọ́ di kékeré láàrín orílẹ̀-èdè gbogbo; ẹni ẹ̀gàn láàrín àwọn ènìyàn.
16 Dilia gasa fi hou da dilima ogogoi dagoi. Dilisu da dunu eno da dilima beda: i amo dawa: sa. Be ilia da dilima bagade hame beda: i. Dilia fedege agoane gadodili goumi gafulu amoga buhiba ea esalebe hou defele esala. Be Hina Gode, da dilia dafama: ne hedofamu. Hina Gode da sia: i dagoi.”
Ìpayà tí ìwọ ti fà sínú ìgbéraga ọkàn rẹ sì ti tàn ọ́ jẹ; ìwọ tí ń gbé ní pàlàpálá àpáta, tí o jókòó lórí ìtẹ́ gíga síbẹ̀ o kọ́ ìtẹ́ rẹ ga gẹ́gẹ́ bí ẹyẹ idì; láti ibẹ̀ ni èmi yóò ti mú ọ sọ̀kalẹ̀ wá,” ni Olúwa wí.
17 Hina Gode da amane sia: i, “Na da Idome amo bagadewane wadela: lesimu. Amasea, dunu eno da baligili ahoasea, ilia da beda: iba: le bagadewane fofogadigimu.
“Edomu yóò di ahoro gbogbo àwọn tí ń kọjá yóò jáyà, wọn ó sì fi rẹ́rìn-ín ẹlẹ́yà nítorí gbogbo ìpalára rẹ.
18 Sodame amola Goumola amola moilali ela sisiga: le diala, amo da wadela: lesi dagoi ba: i. Amo wadela: su defele da Idome fi ilima doaga: mu. Amo soge da eso huluane, dunu fi esalebe hamedei soge ba: mu. Na, Hina Gode, da sia: i dagoi.
Gẹ́gẹ́ bí wọ́n ṣe gba Sodomu àti Gomorra pẹ̀lú àwọn ìlú tí ó wà ní àyíká rẹ,” ní Olúwa wí. “Bẹ́ẹ̀ ni, kò sí ẹnikẹ́ni tí yóò gbé níbẹ̀; kò sì ní sí ènìyàn tí yóò tẹ̀dó síbẹ̀ mọ́.
19 Laione wa: me da Yodane Hano bega: iwila amo yolesili, bulamagau ha: i manu mola: ya: i gisi soge amoga manebe, amo defele, Na da Idome dunu ilia sogega misini, ili hobeama: ne sefasimu. Amasea, Na da ouligisu dunu amo fi ouligima: ne ilegemu. Nowa da Na agoanela: ? Nowa da Nama doagala: ma: bela: ? Nowa ouligisu dunu da Nama ha lai hamoma: bela: ?
“Bí i kìnnìún ni òun ó gòkè wá láti igbó Jordani sí orí ilẹ̀ ọlọ́ràá, Èmi ó lé Edomu kúrò ní ilẹ̀ rẹ̀ ní kíákíá. Ta ni àyànfẹ́ náà tí èmi ó yàn sórí rẹ̀? Ta ló dàbí mi, ta ni ó sì pé mi ṣe ẹlẹ́rìí? Ta ni olùṣọ́-àgùntàn náà tí yóò le dúró níwájú mi?”
20 Amaiba: le, Na ilegebe nabima! Na da Idome soge fi dunu amola Dima: ne moilai bai bagade dunu ilima se imunu. Ilia mano amola da ga hiougiligai dagoi ba: mu. Amola dunu huluane da amo hou beda: iwane fofogadigili ba: mu.
Nítorí náà, ẹ gbọ́ ohun tí Olúwa ní fún Edomu, ohun tí ó ní ní pàtàkì fún àwọn tí ń gbé ní Temani. Àwọn ọ̀dọ́ àgbò ni à ó lé jáde; pápá oko wọn ni yóò run nítorí wọn.
21 Idome soge da dafasea, ha lasu bagade nababeba: le, osobo bagade da igugumu. Amola, Agaba Hano Adobo da sedadewane diala. Be beda: ma: ne ha lasu da bagadeba: le, ilia amola da amo sia: nabimu.
Ilẹ̀ yóò mì tìtì nípa ariwo ìṣubú wọn, a ó gbọ́ igbe wọn ní Òkun pupa.
22 Buhiba da ea ougia ilua: le, gududili wa: le ahoa, amo defele, ha lai dunu da Bosela doagala: mu. Amo esoha, uda da mano lamu gadenesea beda: i, amo defele Idome dadi gagui dunu da beda: mu.”
Wò ó! Ẹyẹ idì yóò gòkè fò wálẹ̀, yóò tẹ ìyẹ́ rẹ̀ lórí Bosra. Ní ọjọ́ náà ọkàn àwọn ajagun Edomu yóò dàbí ọkàn obìnrin tí ń rọbí.
23 Hina Gode da Dama: sagase fi ilia hou dawa: le amane sia: i, “Ha: ima: de amola Aba: de moilai bai bagade dunu da da: i dioi sia: nababeba: le, da: i dione dawa: lala. Hano wayabo bagade ea gafului da sa: iboso amoga heda: sa, amo defele da: i dioi da ilima heda: beba: le, ilia da helefimu hame dawa:
Nípa Damasku. “Inú Hamati àti Arpadi bàjẹ́ nítorí wọ́n gbọ́ ìròyìn búburú, ìjayà dé bá wọn, wọ́n sì dààmú bí omi Òkun.
24 Dama: sagase fi dunu da gasa hame amola beda: iba: le, hobeale asi dagoi. Uda da mano lamu gadenesea, se naba amola hahawane hame ba: sa, amo defele ilia da hamosa.
Damasku di aláìlera, ó pẹ̀yìndà láti sálọ, ìwárìrì sì dé bá a; ìbẹ̀rù àti ìrora dìímú, ìrora bí ti obìnrin tí ó wà ní ipò ìrọbí.
25 Musa: Dama: sagase moilai bai bagade da bagade ba: i amola hahawane dialu. Be wali, amo ganodini, dunu esalebe da hame ba: sa.
Kí ló dé tí ìlú olókìkí di ohun ìkọ̀sílẹ̀; ìlú tí mo dunnú sí.
26 Amo esoga Na da ema se iasea, ea ayeligi dunu da ea logo ganodini medole legei dagoi ba: mu, amola ea dadi gagui wadela: lesi dagoi ba: mu.
Lóòtítọ́, àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin rẹ yóò ṣubú lójú pópó, gbogbo àwọn ọmọ-ogun rẹ yóò pa ẹnu mọ́ ní ọjọ́ náà,” ní Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
27 Na da Dama: sagase ea gagoi dobea laluga ulagimu amola hina bagade Beneha: ida: de ea diasu laluga ulagimu. Na, Hina Gode Bagadedafa, da sia: i dagoi.”
“Èmi yóò fi iná sí odi Damasku, yóò sì jó gbọ̀ngàn Beni-Hadadi run.”
28 Hina Gode da Gida fi amola soge amo da Ha: iso fi ilia ouligi (amo soge Ba: bilone hina bagade Nebiuga: denese da hasalalu lai) ilima amane hamoma: ne sia: i, “Gida fi ilima doagala: ma! Amo gusudili fi wadela: lesima!
Nípa ìlú Kedari àti ìjọba Hasori èyí ti Nebukadnessari ọba Babeli dojú ìjà kọ, èyí ni ohun tí Olúwa sọ, “Dìde kí o sì dojú ìjà kọ ìlú Kedari, kí o sì pa àwọn ènìyàn ìlà-oòrùn run.
29 Ilia abula diasu amola sibi fi wa: i amola ilia diasu abula amola ilia liligi huluane abula diasu ganodini diala, amo lama! Ilia ga: mele amola lama! Amola fi dunu ilima, ‘Beda: su da dilima sisiga: sa’ olelema!
Àgọ́ wọn àti agbo àgùntàn wọn ni wọn ó kó lọ; àgọ́ wọn yóò di ìṣínípò padà pẹ̀lú gbogbo ẹrù àti ìbákasẹ wọn. Àwọn ènìyàn yóò ké sórí wọ́n pé, ‘Ẹ̀rù yí káàkiri!’
30 Ha: iso dunu! Na da dilima sisasu iaha! Wamoaligimusa: , sedagawane hobeama! Ba: bilone hina bagade, Nebiuga: denese, da dilima doagala: ma: ne ilegei dagoi. E da amane sia: sa,
“Sálọ kíákíá! Fi ara pamọ́ sí ibi jíjìn, ẹ̀yin olùgbé Hasori,” ni Olúwa wí. “Nebukadnessari ọba Babeli ti dojú ìjà kọ ọ́.
31 ‘Defea! Amo dunu fi da hahawane gaga: i dagoi, ilisu dawa: sa. Be ninia da ilima doagala: mu. Ilia moilai da logo ga: su hame gala amola hame gagili sali agoane ba: sa.’
“Dìde kí o sì dojú ìjà kọ orílẹ̀-èdè tí ó wà nínú ìrọ̀rùn, èyí tí ó gbé ní àìléwu,” ní Olúwa wí. “Orílẹ̀-èdè tí kò ní odi tàbí irin, àwọn ènìyàn rẹ̀ ń dágbé.
32 Ilia ga: mele amola laigebo huluane lale dagoma! Na da la: idi huluane amoga amo fi ilia dialuma hinabo dunumuni dadamuni, afagogomu. Amola la: ididili la: ididili, amoga ilima wadela: lesisu iasimu.
Àwọn ìbákasẹ á di ẹrù àti àwọn ẹran ọ̀sìn, wọ́n á di ìkógun. Èmi yóò tú àwọn tí ó wà ní òkèèrè sí inú afẹ́fẹ́. Èmi yóò sì mú ibi wá sí àyíká gbogbo,” báyìí ní Olúwa wí.
33 Na da Ha: iso amo hafoga: i soge agoane eso huluane dialoma: ne hamomu. Sigua wa: me fawane da amo ganodini esalebe ba: mu. Amo ganodini, eso huluanedafa, dunu fi da hame esalebe ba: mu. Na, Hina Gode, da sia: i dagoi.”
“Hasori yóò di ibi ìdọdẹ àwọn akátá, ibi ìkọ̀sílẹ̀ ayérayé, kò sí ẹni tí yóò gbé ní ibẹ̀.”
34 Sedegaia da Yuda soge hina bagade ouligisu hou lai. Amogalu, Hina Gode Bagadedafa da hou amo E da Ila: me fi ilima ilegei, amo nama olelei.
Èyí ní ọ̀rọ̀ Olúwa èyí tí ó tọ Jeremiah wòlíì wá nípa Elamu ní ìbẹ̀rẹ̀ ìjọba Sedekiah ọba Juda.
35 E amane sia: i, “Dadi gagui dunu ilia hamobeba: le, Ila: me da gasa lai. Be Na da dadi gagui dunu huluane medole legemu.
Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun sọ: “Wò ó, èmi yóò fọ́ ìtẹ̀gùn Elamu, ẹni tí wọ́n sinmi lé nípa agbára.
36 Na sia: beba: le, fo bagade da la: idi huluane amoga Ila: me wadela: ma: ne misunu. Na da ea fi dunu fifi asi gala huluanedafa amo ganodini esaloma: ne, afagogomu.
Èmi yóò mú kí afẹ́fẹ́ orígun mẹ́rẹ̀ẹ̀rin àgbáyé lòdì sí Elamu. Èmi yóò tú wọn ká sí ìpín afẹ́fẹ́ mẹ́rin àti pé, kò sí orílẹ̀-èdè tí ilẹ̀ àjèjì Elamu kò ní lọ.
37 Na hamobeba: le, Ila: me fi dunu da ilia ha lai amo da ili medole legemusa: hanai, ilima bagade beda: mu. Na da ougi bagadeba: le, Na da dadi gagui wa: i ili huluane wadela: lesima: ne, ilima asunasili, dunu afae esalebe hame ba: mu.
Èmi yóò kẹ́gàn Elamu níwájú àwọn ọ̀tá wọn, àti níwájú àwọn tí wọ́n ń wá ẹ̀mí wọn, Èmi yóò mú ibi wá sí orí wọn, àní, ìbínú gbígbóná mi,” bẹ́ẹ̀ ni Olúwa wí. “Èmi yóò lé wọn pẹ̀lú idà, di ìgbà tí èmi yóò rẹ́yìn wọn.
38 Na da ilia hina bagade amola ouligisu dunu huluane wadela: lesimu. Amasea, amogawi, Na da Na fisu gaguli, ili ouligimu.
Èmi yóò sì gbé ìtẹ́ mi kalẹ̀ ní Elamu, èmí yóò sì pa ọba wọn àti ìjòyè wọn run,” báyìí ni Olúwa wí.
39 Be fa: nodafa, Na da Ila: me dunu ilia bu hahawane gaguiwane buhagima: ne, logo doasimu. Na, Hina Gode, da sia: i dagoi.”
“Síbẹ̀, èmi yóò dá ìkólọ Elamu padà láìpẹ́ ọjọ́,” báyìí ni Olúwa wí.

< Yelemaia 49 >