< Yelemaia 46 >
1 Hina Gode da fifi asi gala ilia hou nama olelei.
Èyí ni ọ̀rọ̀ Olúwa tí ó tọ Jeremiah wòlíì wá nípa àwọn Orílẹ̀-èdè.
2 E da hidadea Idibidi fi ilia hou olelei. E da Idibidi hina bagade Nigou ea dadi gagui wa: i amo ilia hou olelei. Ba: bilone hina bagade Nebiuga: denese da Yuda hina bagade Yihoiagimi ea ouligisu ode biyaduga, e da Gagimisi moilai bai bagade Iufala: idisi Hano gadenene amoga hina bagade Nigou ea dadi gagui wa: i amoga hasalasi. Hina Gode da amane sia: i,
Nípa Ejibiti. Èyí ni ọ̀rọ̀ nípa àwọn ọmọ-ogun Farao Neko ọba Ejibiti ẹni tí a borí rẹ̀ ní Karkemiṣi, ní odò Eufurate láti ọwọ́ Nebukadnessari ọba Babeli ní ọdún kẹrin Jehoiakimu ọmọ Josiah ọba Juda:
3 “Idibidi dadi gagui ouligisu dunu da amane wele sia: sa, ‘Dilia da: igene ga: su momagele, gegemusa: mogodigili masa.
“Ẹ múra àpáta, èyí tí ó tóbi, àti èyí tí ó kéré, kí ẹ sì súnmọ́ ojú ìjà!
4 Dilia hosi liligi momagele, ili da: iya fila heda: ma! Dadalema! Ouli habuga figisima! Dilia goge agei debema! Dilia da: igene ga: su liligi gasisalima!’
Ẹ di ẹṣin ní gàárì, kí ẹ sì gùn ún. Ẹ dúró lẹ́sẹẹsẹ pẹ̀lú àṣíborí yín! Ẹ dán ọ̀kọ̀ yín, kí ẹ sì wọ ẹ̀wù irin.
5 “Be Na da adi ba: sala: ?” Hina Gode da amane sia: sa. “Ilia da beda: iba: le sinidigisa. Ilia ha lai da ili fanana. Ilia da bagadewane beda: iba: le, mae beba: le hobeasa.
Kí ni nǹkan tí mo tún rí? Wọ́n bẹ̀rù, wọ́n sì ń padà sẹ́yìn, wọ́n ti ṣẹ́gun àwọn jagunjagun. Wọ́n sá, wọn kò sì bojú wẹ̀yìn, ìbẹ̀rù sì wà níbi gbogbo,” ni Olúwa wí.
6 Be hedolodafa hehenasu dunu da baligili hobeamu hame dawa: Dadi gagui dunu da hobeale masunu hamedei ba: sa. Gagoe (north) sogega, Iufala: idisi Hano gadenene, ilia da emo udagaguli dafasa.
“Ẹni tí ó yára kì yóò le sálọ, tàbí alágbára kò ní lè sá àsálà. Ní àríwá ní ibi odò Eufurate wọn yóò kọsẹ̀, wọn yóò sì ṣubú.
7 Fi amo da Naile Hano defele heda: le ea bega: nabale aduga: le daha, amo fi da nowala: ?
“Ta ni èyí tí ó gòkè wá bí odò Ejibiti, tí omi rẹ̀ ń ru gẹ́gẹ́ bí odò wọ̀n-ọn-nì?
8 Amo fi da Idibidi. E da Naile Hano defele heda: le, ea bega: nabane aduga: le daha. Idibidi da amane sia: i, ‘Na da heda: le, osobo bagade dedebomu. Na da moilai amola amo ganodini esalebe dunu amo wadela: lesimu.
Ejibiti dìde bí odò náà, bí omi odò tí ń ru. Ó sì wí pé, ‘Èmi yóò dìde, n ó sì bo gbogbo ilẹ̀ ayé.’ Èmi yóò pa ìlú àti àwọn ènìyàn rẹ̀ run.
9 Hosi masa: ne sia: ma! Sa: liode masa: ne sia: ma! Dadi gagui dunu gadili asunasima! Ilia da Suda: ne amola Libia soge, ilia da: i ga: su gaguiwane maha. Amola dadia gegesu bagade dawa: su dunu Lidia sogega misi, amo asunasimu.’”
Ẹ gòkè wá ẹ̀yin ẹṣin, ẹ sì sáré kíkankíkan ẹ̀yin kẹ̀kẹ́. Kí àwọn alágbára túbọ̀ tẹ̀síwájú, àwọn ará Kuṣi àti àwọn ará Puti tí ń di asà mú; àti àwọn ará Lidia tí ń fa ọrun.
10 Wali eso da Ouligisudafa Hina Gode Bagadedafa Ea Eso. Wali eso E da dabemu. Wali eso E da Ea ha lai ilima se imunu. Fedege agoane, Ea gobihei da sadima: ne, Ea ha lai na dagomu. Amola sadima: ne, ilia maga: me manu. Wali eso, gagoe (north) soge Iufala: idisi Hano gadenene, Hina Gode Bagadedafa da gobele salasu hamomu.
Ṣùgbọ́n ọjọ́ náà jẹ́ ti Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun, ọjọ́ ìgbẹ̀san, ìgbẹ̀san lára àwọn ọ̀tá rẹ̀. Idà yóò sì jẹ́ títí yóò fi ní ìtẹ́lọ́rùn, títí yóò fi pa òǹgbẹ rẹ̀ rẹ́ pẹ̀lú ẹ̀jẹ̀. Nítorí pé Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun yóò rú ẹbọ ní ilẹ̀ gúúsù ní odò Eufurate.
11 Idibidi dunu! Manoma hogomusa: , Gilia: de sogega masa! Dilia manoma da udigili hamedei agoane ba: i dagoi. Dilia da uhimu da hamedei.
“Gòkè lọ sí Gileadi, kí o sì mú ìkunra, ìwọ wúńdíá ọmọbìnrin Ejibiti. Ṣùgbọ́n ní asán ni ìwọ ń lo oògùn, kì yóò sí ìwòsàn fún ọ.
12 Fifi asi gala huluane da dilia gogosiasu ba: i, amo nabi dagoi. Dadi gagui afae afae da ea sama amoma emo udagaguli, ela gilisili osoboga dafasa.
Àwọn orílẹ̀-èdè yóò gbọ́ nípa ìtìjú rẹ, igbe rẹ yóò kún gbogbo ayé. Jagunjagun yóò máa ṣubú lu ara wọn lórí rẹ, àwọn méjèèjì yóò sì jọ ṣubú papọ̀.”
13 Ba: bilone hina bagade Nebiuga: denese da Idibidi doagala: musa: manoba, Hina Gode da nama amane sia: i,
Èyí ni ọ̀rọ̀ Olúwa tí ó bá Jeremiah wòlíì nì sọ nípa wíwá Nebukadnessari ọba Babeli láti lọ dojú ìjà kọ Ejibiti:
14 “Idibidi moilai bai bagade (Migidole, Memefisi amola Daha: banisi) amo ganodini ha: giwane amane olelema, ‘Dilila: gaga: ma: ne, momagema! Dilia huluane gegesu ganodini wadela: lesi dagoi ba: mu.
“Kéde èyí ní Ejibiti, sì sọ ọ́ ní Migdoli, sọ ọ́ ní Memfisi àti Tafanesi: ‘Dúró sí ààyè rẹ kí o sì múra sílẹ̀, nítorí pé idà náà ń pa àwọn tí ó yí ọ ká.’
15 Dilia gasa bagadedafa dadi gagui dunu da abuliba: le dafabela: ? Bai Hina Gode da ili fane legei dagoi.
Èéṣe tí àwọn akọni rẹ fi ṣubú? Wọn kò ní le dìde dúró, nítorí Olúwa yóò tì wọ́n ṣubú.
16 Dilia dadi gagui dunu da emo udagaguli dafai dagoi. Ilia enoma enoma amane sia: daha, ‘Hedolo! Ninia ha lai amoga medole legesu mae ba: ma: ne, ninia fi dunu diasuga ahoa: di.’
Wọn yóò máa ṣubú léraléra wọn yóò máa ṣubú lu ara wọn. Wọn yóò sọ wí pé, ‘Ẹ dìde, ẹ jẹ́ kí a padà sí ọ̀dọ̀ àwọn ènìyàn wa àti ilẹ̀ ìbí wa, kúrò níbi idà àwọn aninilára.’
17 Idibidi hina bagade ema amo gaheabolo dio asulima, ‘Sia: Bagade Hidasu Dunu, E da Hasalasisu Giadofai.’
Níbẹ̀ ni wọn ó kígbe pé, ‘Ariwo lásán ni Farao ọba Ejibiti pa, ó ti sọ àǹfààní rẹ̀ nù.’
18 Na, Hina Gode Bagadedafa, da Hina Bagade! Na da Gode Esala! Da: ibo Goumi da goumi huluane baligisa. Amola Gamele Goumi da hano wayabo bagade amoga bagade heda: i dagoi ba: sa. Amo defele, dilima doagala: su dunu ea gasa da dilia gasa bagadewane baligimu.
“Bí èmi ti wà láààyè,” ni ọba, ẹni tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí pé, “Nítòótọ́ gẹ́gẹ́ bí Tabori láàrín àwọn òkè àti gẹ́gẹ́ bi Karmeli lẹ́bàá Òkun bẹ́ẹ̀ ni òun yóò dé.
19 Dilia Idibidi fi dunu! Udigili hawa: hamomusa: masa: ne momagema! Memefisi moilai bai bagade da wadela: i hafoga: i soge amo ganodini dunu esalebe hame ba: mu, agoai ba: mu galebe.
Ìwọ, ọmọbìnrin ti ń gbé Ejibiti pèsè ohun èlò ìrìnàjò fún ara rẹ nítorí Memfisi yóò di ahoro a ó sì fi jóná, láìní olùgbé.
20 Idibidi da bulamagau aseme noga: idafa agoane ba: sa. Be gagoe (north) amoga gasonasu awinimi ema doagala: musa: manebe ba: sa.
“Ẹgbọrọ abo màlúù tó lẹ́wà ní Ejibiti ṣùgbọ́n eṣinṣin ìparun dé, ó dé láti àríwá.
21 Idibidi muni hawa: hamosu dadi gagui dunu amola da bulamagau mano fonobahadi defele, gasa hame ba: sa. Ilia da bu gegemusa: hame lelu. Ilia da sinidigili, hobea: i. Ilia wadela: mu eso da doaga: i dagoi.
Àwọn jagunjagun rẹ̀ dàbí àbọ́pa akọ màlúù. Àwọn pẹ̀lú yóò yípadà, wọn ó sì jùmọ̀ sá, wọn kò ní le dúró, nítorí tí ọjọ́ ibi ń bọ̀ lórí wọn àsìkò láti jẹ wọ́n ní ìyà.
Ejibiti yóò pòṣé bí ejò tí ń sá bí ọmọ-ogun ṣe ń tọ̀ ọ́ wá pẹ̀lú agbára. Wọn ó tọ̀ ọ́ wá pẹ̀lú àáké, gẹ́gẹ́ bí i ti agégi.
23 Ha lai dadi gagui wa: i da manebe ba: loba, Idibidi da sania agoane soiya afia: i. Ilia ha lai da dunu amo da goaheiga ifa aba amola iwila bagade wadela: su, amo defele ilima doagala: sa. Ha lai dadi gagui da idimu hame gala. Ilia idi da danuba: wa: i ilia idi baligisa.
Wọn o gé igbó rẹ̀ lulẹ̀,” ni Olúwa wí, “nítorí ti a kò le rídìí rẹ̀. Nítorí pé wọ́n pọ̀ ju ẹlẹ́ǹgà lọ, wọ́n sì jẹ́ àìníye.
24 Idibidi dunu da gogosiasu ba: sa. Gagoe (north) fi dunu da ilima hasalasi dagoi. Na, Hina Gode, da sia: i dagoi.”
A ó dójútì ọmọbìnrin Ejibiti, a ó fà á lé ọwọ́ àwọn ènìyàn àríwá.”
Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run Israẹli wí pé: “Èmi yóò rọ̀jò ìyà mi sórí Amoni òrìṣà Tebesi, sórí Farao, sórí Ejibiti àti àwọn òrìṣà rẹ̀ àti sórí àwọn ọba rẹ̀ àti sórí àwọn tó gbẹ́kẹ̀lé Farao.
26 Hina Gode Bagadedafa, Isala: ili fi ilia Gode, da amane sia: sa, “Na da Dibisi moilai bai bagade ea ogogosu ‘gode’ A: imone amola Idibidi fi huluane (ilia ‘gode’ amola hina bagade) ilima se bagade imunu. Na da Idibidi hina bagade amola dunu huluane ema fa: no bobogesa, amo lale, dunu amo da ili medole legemusa: hanai ilima imunu. Na da ili amo Ba: bilone hina bagade Nebiuga: denese amola ea dadi gagui wa: i ilima imunu. Be hobea, dunu da musa: Idibidi soge ganodini esalu, amo defele, dunu da bu amo ganodini esalumu. Na, Hina Gode, da sia: i dagoi.”
Èmi ó sì fi wọ́n lé àwọn tó wá ẹ̀mí wọn lọ́wọ́, lé Nebukadnessari ọba Babeli, ṣùgbọ́n lẹ́yìn ìgbà díẹ̀, Ejibiti yóò sì di gbígbé bí i ti àtijọ́,” ni Olúwa wí.
27 Hina Gode da amane sia: i, “Na fi dunu! Mae beda: ma! Dilia da soge sedaga amo ganodini udigili hawa: hamonana. Be amoga Na da dili gaga: le, fadegamu. Dilia da dilia sogedafa amoga buhagili, olofole esalumu. Amasea, dilia da gaga: iwane, mae beda: iwane, amo ganodini esalumu.
“Má bẹ̀rù, ìwọ Jakọbu ìránṣẹ́ mi, má fòyà, ìwọ Israẹli. Dájúdájú èmi ó gbà ọ́ láti ọ̀nà jíjìn, àwọn ọmọ ọmọ rẹ ní ilẹ̀ ìgbèkùn. Jakọbu yóò tún ní àlàáfíà àti ààbò, kò sì ṣí ẹni tí yóò dẹ́rùbà á.
28 Na da dilima misini, dili gaga: mu. Na da fifi asi gala amoga Na da dili afagogoi dagoi, amo huluane wadela: lesimu. Be Na da dili hame wadela: lesimu. Na da dilima se imunu. Be amo se iasea, moloidafa se fawane imunu. Na, Hina Gode, Na da sia: i dagoi.”
Má bẹ̀rù, Jakọbu ìránṣẹ́ mi, nítorí pé mo wà pẹ̀lú rẹ,” bẹ́ẹ̀ ni Olúwa wí. “Bí mo tilẹ̀ pa gbogbo orílẹ̀-èdè run, láàrín àwọn tí mo fọ́n yín ká sí. Èmi kò ní run yín tán. Èmi yóò jẹ ọ́ ní ìyà lórí òdodo, èmi kí yóò jọ̀wọ́ rẹ lọ́wọ́ lọ láìjẹ ọ́ ní yà.”