< Yelemaia 4 >

1 Hina Gode da amane sia: sa, “Isala: ili fi dunu! Dilia da sinidigimusa: dawa: sea, Nama sinidigima. Dilia da moloiwane Nama fa: no bobogesea amola loboga hamoi ogogosu ‘gode’ fadegasea,
“Tí ìwọ yóò bá yí padà, ìwọ Israẹli, padà tọ̀ mí wá,” ni Olúwa wí. “Tí ìwọ yóò bá sì mú ìríra rẹ kúrò níwájú mi, ìwọ kí ó sì rìn kiri.
2 dilia da Na Dioba: le dafawane ilegemu da defea ba: mu. Amasea, fifi asi gala huluane da Nama Na da ili hahawane dogolegele sia: ma: ne adole ba: mu. Amola ilia da Nama nodone sia: ne gadomu.”
Tí ó bá jẹ́ lóòtítọ́ àti òdodo ni ìwọ búra. Nítòótọ́ bí Olúwa ti wà láààyè, nígbà náà ni orílẹ̀-èdè yóò di alábùkún fún nípasẹ̀ rẹ, àti nínú rẹ̀ ni wọn yóò ṣògo.”
3 Hina Gode da Yuda soge amola Yelusaleme moilai bai bagade dunu ilima amane sia: sa, “Dilia soge hame gidinai amo gidinama. Dilia hawa: amo aya: gaga: nomei gisi ganodini mae bugima.
Èyí ni ohun tí Olúwa wí fún àwọn ènìyàn Juda àti Jerusalẹmu: “Hú gbogbo ilẹ̀ tí ẹ kò lò rí, kí o má sì ṣe gbìn sáàrín ẹ̀gún.
4 Dilia Gousa: su amo dilia da Na, Hina Gode, Nama hamoi, amo bu dawa: le, mae fima. Dilia Yuda amola Yelusaleme fi dunu! Nama sia: sima! Amane hame hamosea, Na ougi da lalu agoane nemu. Bai dilia wadela: le hamoi dagoi. Na ougi da dunu enoga ha: ba: domu hamedene nenanumu.”
Kọ ara rẹ ní ilà sí Olúwa, kọ ọkàn rẹ ní ilà, ẹ̀yin ènìyàn Juda àti gbogbo ènìyàn Jerusalẹmu, bí bẹ́ẹ̀ kọ́, ìbínú mi yóò ru jáde yóò sì jó bí iná, nítorí ibi tí o ti ṣe kì yóò sí ẹni tí yóò pa á.
5 Soge huluane amo ganodini, dalabede fulaboma! Ha: giwane wele sia: ma! Yuda soge amola Yelusaleme fi dunu ilima ilia da gasa bagade gagole moilai bai bagadega hehenama: ne sia: ma!
“Kéde ní Juda, kí o sì polongo ní Jerusalẹmu, kí o sì wí pé: ‘Fun fèrè káàkiri gbogbo ilẹ̀!’ Kí o sì kígbe: ‘Kó ara jọ pọ̀! Jẹ́ kí a sálọ sí ìlú olódi.’
6 Saione amoma doaga: ma: ne, logo olelema! Dilia esalusu gaga: ma: ne hobeama! Mae aligima! Hina Gode da se nabasu amola soge wadela: su hou gagoe (north) amoga gaguli maha.
Fi àmì láti sálọ sí Sioni hàn, sálọ fún ààbò láìsí ìdádúró. Nítorí èmi ó mú àjálù láti àríwá wá, àní ìparun tí ó burú jọjọ.”
7 Laione wa: me da ea wamoaligisu amoga manebe, amo defele fifi asi gala wadela: su dunu da manebe goea. E da Yuda wadela: lesimusa: manebe. Yuda soge moilai huluane da mugului dagoi ba: mu. Amo ganodini, dunu afae esalebe da hame ba: mu.
Kìnnìún ti sá jáde láti inú ibùgbé rẹ̀, apanirun orílẹ̀-èdè sì ti jáde. Ó ti fi ààyè rẹ̀ sílẹ̀ láti ba ilẹ̀ rẹ̀ jẹ́. Ìlú rẹ yóò di ahoro láìsí olùgbé.
8 Amaiba: le, wadela: i eboboi abula salawane, dima amola didigia: ma. Bai Hina Gode da Yuda fi ilima ougi bagade amola Ea ougi da hame gumi.
Nítorí náà, gbé aṣọ ọ̀fọ̀ wọ̀ káàánú kí o sì pohùnréré ẹkún, nítorí ìbínú ńlá Olúwa kò tí ì kúrò lórí wa.
9 Hina Gode da amane sia: i, “Amo esoha, hina bagade amola eagene ouligisu dunu da bagade beda: mu. Gobele salasu dunu amola balofede dunu da beda: ne, fofogadigimu.”
“Ní ọjọ́ náà,” ni Olúwa wí pé, “Àwọn ọba àti ìjòyè yóò pàdánù ẹ̀mí wọn, àwọn àlùfáà yóò wárìrì, àwọn wòlíì yóò sì fòyà.”
10 Amalalu, na da amane sia: i, “Ouligisudafa Hina Gode! Di da Yelusaleme fi dunu ilima dafawane ogogoi dagoi. Di da olofosu manebe sia: i dagoi, be ilia asogoa hedofama: ne, gegesu gobihei bagade galebe ba: sa.”
Nígbà náà ni mo sì wí pé, “Háà! Olúwa Olódùmarè, báwo ni ìwọ ti ṣe tan àwọn ènìyàn wọ̀nyí àti Jerusalẹmu jẹ nípa sísọ wí pé, ‘Ìwọ yóò wà ní àlàáfíà,’ nígbà tí o jẹ́ wí pé idà wà ní ọ̀fun wa.”
11 Eso da manebe, amoga Yelusaleme da sia: nabimu. Amo sia: da hafoga: i sogega gia: i bagade fo agoane ilima doaga: ma: ne manebe. Asaboi fo da gisi fawane gaguli ahoa. Be amo fo da agoaiwane hame.
Nígbà náà ni a ó sọ fún Jerusalẹmu àti àwọn ènìyàn pé, “Ẹ̀fúùfù líle láti aṣálẹ̀ fẹ́ lu àwọn ènìyàn mi, kì í ṣe láti sọ di mímọ́.
12 Amo fo da Hina Gode da sia: beba: le misunu, amola fo eno ea gasa bagade baligimu. Bai amo fo da Hina Gode Hisu da Ea dunu fi ilima se ima: ne fofada: musa: manebe ba: mu.
Ẹ̀fúùfù líle tí ó wá láti ọ̀dọ̀ mi. Báyìí mo kéde ìdájọ́ mi lórí wọn.”
13 Ba: ma: i! Ha lai dunu da mu mobi agoane manebe. Ea gegesu ‘sa: liode’ da fo ononoi defele ba: sa. Amola ea hosi ea hehenasu da buhiba ea hagili ahoasu baligisa. Ninia da fisi dagoi! Nini da wadela: lesi dagoi!
Wò ó! O ń bọ̀ bí ìkùùkuu kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀ sì wá bí ìjì líle ẹṣin rẹ̀ sì yára ju idì lọ. Ègbé ni fún wa àwa parun.
14 Yelusaleme! Dia gaga: su ba: ma: ne, dia dogo nigima: amo dodofema! Di da habogala wadela: i asigi dawa: su yolesima: bela: ?
Ìwọ Jerusalẹmu, mú búburú kúrò lọ́kàn rẹ kí o sì yè. Yóò ti pẹ́ tó tí ìwọ yóò mú èrò búburú wà ní ọkàn rẹ?
15 Sia: adola ahoasu dunu da Da: ne moilai amola Ifala: ime agolo amoga misini, wadela: su sia: olelesa.
Ohùn kan sì ń kéde ní Dani o ń kókìkí ìparun láti orí òkè Efraimu wá.
16 Ilia da fifi asi gala ilima sisa: ma: ne misi. Amola Yelusaleme fi ilima ha lai da soge sedaganini manebe amo ilima sisasu olelemusa: misi. Amo ha lai dunu da Yuda soge moilai amoma ha lamu.
“Sọ èyí fún àwọn orílẹ̀-èdè, kéde rẹ̀ fún Jerusalẹmu pé: ‘Ọmọ-ogun ọ̀tá ń bọ̀ láti ilẹ̀ jíjìn wá wọ́n sì ń kígbe ogun láti dojúkọ ìlú Juda.
17 Ilia da dunu da soge sosodo aligisu defele, Yelusaleme sisiga: mu. Bai Yelusaleme fi da Hina Gode Ema odoga: su. Hina Gode da sia: i dagoi.
Wọ́n yí i ká bí ìgbà tí àwọn ọkùnrin bá ń ṣọ́ pápá, nítorí pé ó ti dìtẹ̀ sí mi,’” ni Olúwa wí.
18 Yuda! Disu dia hamobeba: le amola dia esalusu hou amoba: le, amo se iasu da dima doaga: i. Dia wadela: i hou hamobeba: le, amo se nabasu da dima misi. Dia wadela: i hou da gobihei agoane dia dogo soi dagoi.
“Ìwà rẹ àti ìṣe rẹ ló fa èyí bá ọ ìjìyà rẹ sì nìyìí. Báwo ló ti ṣe korò tó! Báwo ló ti ṣe gún ọkàn rẹ sí!”
19 Na da se nabi dagoi. Amo se nabasu nabimu da nama hamedei! Na dogo! Na dogo da ilibu agoane hedolole dusa! Na da ouiya: mu gogolesa. Na da dalabede fulabosu naba, amola gegesu halasu naba.
Háà! Ìrora mi, ìrora mi! Mo yí nínú ìrora. Háà, ìrora ọkàn mi! Ọkàn mi lù kìkì nínú mi, n kò le è dákẹ́. Nítorí mo ti gbọ́ ohùn ìpè, mo sì ti gbọ́ igbe ogun.
20 Wadela: su afae ba: lalu, wadela: su eno da hedolowane doaga: sa. Soge huluane da wadela: lesi dagoi. Hedolowane, ninia abula diasu da wadela: lesi dagoi ba: sa. Ilia abula da gadelale, fofonoboi dagoi ba: sa.
Ìparun ń gorí ìparun; gbogbo ilẹ̀ náà sì ṣubú sínú ìparun lọ́gán ni a wó àwọn àgọ́ mi, tí ó jẹ́ ohun ààbò mi níṣẹ́jú kan.
21 Gegesu da bagadewane heda: sa. Na da habowali seda amo gegesu ba: ma: bela: ? Dalabede ea fulabosu, na da naba. Amo na da habowali seda nabima: bela: ?
Yóò ti pẹ́ tó, tí èmi yóò rí ogun tí èmi yóò sì gbọ́ ìró fèrè?
22 Hina Gode da amane sia: sa, “Na fi dunu da gagaoui dagoi. Ilia da Na hame dawa: Ilia da gagaoui mano defele, asigi dawa: su hame gala. Ilia da wadela: i hou hamomusa: bagade dawa: su dunu agoai ba: sa. Be hou ida: iwane didili hamomusa: hamedafa dawa:”
“Aṣiwèrè ni àwọn ènìyàn mi; wọn kò mọ̀ mí. Wọ́n jẹ́ aláìgbọ́n ọmọ; wọ́n sì jẹ́ aláìlóye. Wọ́n mọ ibi ni ṣíṣe; wọn kò mọ bí a ti í ṣe rere.”
23 Na da osobo bagade ba: i. E da wadela: lesi dagoi ba: i. Na da mu ba: i. Be amoga da hadigi hame galu.
Mo bojú wo ayé, ó sì wà ní júujùu, ó sì ṣófo àti ní ọ̀run, ìmọ́lẹ̀ wọn kò sì ṣí.
24 Na da goumi ba: i. Ilia da fogoi amola agolo da la: ididili, la: ididili fogolalebe ba: i.
Mo wo àwọn òkè ńlá, wọ́n wárìrì; gbogbo òkè kéékèèké mì jẹ̀jẹ̀.
25 Na ba: loba, dunu fi huluane da hamedafa gala. Sio fi huluane amola da hagili asi dagoi ba: i.
Mo wò yíká n kò rí ẹnìkan; gbogbo ẹyẹ ojú ọ̀run ló ti fò lọ.
26 Nasegagi soge huluane da hafoga: i soge agoane hamoi dagoi ba: i. Soge ea moilai bai bagade huluane da mugululi, wadela: lesi dagoi ba: i. Bai Hina Gode Ea ougi bagade da amo sogega dialebe ba: i.
Mo bojú wò, ilẹ̀ eléso, ó sì di aṣálẹ̀ gbogbo àwọn ìlú inú rẹ̀ sì ṣubú sínú ìparun níwájú Olúwa àti níwájú ríru ìbínú rẹ̀.
27 (Hina Gode da amane sia: i dagoi, “Osobo bagade huluane da wadela: lesi dagoi ba: mu. Be Na da dafawanedafa hame wadela: lesimu.”)
Èyí ni ohun tí Olúwa wí: “Gbogbo ìlú náà yóò sì di ahoro, síbẹ̀ èmi kì yóò pa á run pátápátá.
28 Osobo bagade da da: i diomu. Mu da gasimu. Hina Gode da sia: i dagoi, amola E da Ea asigi dawa: su amo hame afadenemu. E da amo hou hamomusa: dawa: i dagoi, amola E da Ea asigi dawa: su hame bu sinidigimu.
Nítorí náà, ayé yóò pohùnréré ẹkún àwọn ọ̀run lókè yóò ṣú òòkùn nítorí mo ti sọ, mo sì ti pète rẹ̀ mo ti pinnu, n kì yóò sì yí i padà.”
29 Dunu huluane da hosi amoga fila heda: i dunu amola dadi gagui dunu ilia halasu nabasea, hobeamu. Mogili da iwilaga hobeamu amola mogili da igi sogega hobeamu. Moilai huluane da dunu hamedafa esalebe ba: mu. Amola amo moilai ganodini, dunu da bu hamedafa fi dialumu.
Nípa ariwo àwọn ẹlẹ́ṣin àti àwọn tafàtafà gbogbo ìlú yóò sálọ. Ọ̀pọ̀ sálọ sínú igbó; ọ̀pọ̀ yóò sì gun orí àpáta lọ. Gbogbo ìlú náà sì di ahoro; kò sì ṣí ẹnìkan nínú rẹ̀.
30 Yelusaleme! Di da wadela: lesi dagoi ba: mu! Di da abuliba: le yoi abula gasisalabala? Dia da abuliba: le nina: hamoma: ne, igi noga: iwane legesa amola dia si amoga soa: legesala: ? Di da udigili nina: hamosa. Bai dima gamu dunu ilia da wali di higasa amola di medole legemusa: dawa: lala.
Kí ni ò ń ṣe, ìwọ tí o ti di ìjẹ tán? Ìwọ ìbá wọ ara rẹ ní aṣọ òdodo kí o sì fi wúrà ṣe ara rẹ lọ́ṣọ̀ọ́. Àwọn olólùfẹ́ rẹ kẹ́gàn rẹ; wọ́n sì ń lépa ẹ̀mí rẹ.
31 Na da se nabasu wele sia: su, amo uda da ea magobo mano lamu gadenesa wele sia: be agoane wesa, amo nabi dagoi. Amo da fedege agoane, Yelusaleme ea mifo lamu hamedeiba: le, habe ha: ha: iya wele sia: nebe agoai nabi. E da ea lobo ilua: le amane sia: su, “Na da wadela: lesi dagoi. Ilia da na medole legemusa: manebe!”
Mo gbọ́ ìró kan bí i igbe obìnrin tó ń rọbí, tí ó ń rọbí, ìrora bí i abiyamọ ọmọbìnrin Sioni tí ń pohùnréré ẹkún ara rẹ̀. Tí ó na ọwọ́ rẹ̀ tí ó sì wí pé, “Kíyèsi i mo gbé, nítorí a ti fi ẹ̀mí mi lé àwọn apani lọ́wọ́.”

< Yelemaia 4 >