< Yelemaia 34 >

1 Ba: bilone hina bagade Nebiuga: denese amola ea dadi gagui wa: i, amola fifi huluane Nebiuga: denese da ouligi ilia dadi gagui, da Yelusaleme amola moilai gadenene diala amoma doagala: loba, Hina Gode da nama sia: i.
Nígbà tí Nebukadnessari ọba Babeli àti àwọn ọmọ-ogun rẹ̀, pẹ̀lú gbogbo ìjọba àti àwọn ènìyàn ní ilẹ̀ ọba tí ó jẹ ọba lé lórí ń bá Jerusalẹmu jà, àti gbogbo àwọn ìlú tí ó yíká, ọ̀rọ̀ yìí tọ Jeremiah wá láti ọ̀dọ̀ Olúwa pé:
2 Hina Gode, Isala: ili fi ilia Gode, da nama Yuda hina bagade Sedegaiama amane adole iasimusa: masa: ne sia: i, “Na, Hina Gode, da amo moilai bai bagade Ba: bilone hina bagade ema imunu. Amasea, e da amo laluga ulagimu.
“Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli ọmọ-ogun wí: Lọ sí ọ̀dọ̀ Sedekiah ọba Juda kí o sì sọ fún un pé, ‘Èyí ni ohun tí Ọlọ́run wí: Èmi fẹ́ fa ìlú yìí lé ọba Babeli lọ́wọ́, yóò sì jó palẹ̀.
3 Di da hobeale masunu hamedei ba: mu. Ilia da di afugili, ema imunu. Di da ema odagia ba: mu amola odagia sia: mu. Amasea, di da Ba: bilone sogega masunu.
Ìwọ kò ní sá àsálà, ṣùgbọ́n à ó mú ọ, bẹ́ẹ̀ ni a ó sì fà ọ́ lé e lọ́wọ́. Ìwọ yóò rí ọba Babeli pẹ̀lú ojú ara rẹ; yóò sì bá ọ sọ̀rọ̀ lójúkojú; ìwọ yóò sì lọ sí Babeli.
4 Sedegaia! Nabima! Na da dia hou olelemu! Di da gegesu ganodini hame bogomu.
“‘Síbẹ̀, gbọ́ ìlérí Olúwa, ìwọ Sedekiah ọba Juda. Èyí ni ohun tí Ọlọ́run wí nípa rẹ; ìwọ kì yóò ti ipa idà kú;
5 Di da olofole esalu, bogomu. Amola dunu da dia aowalalia hina bagade dunu ilia da: i hodo uli dogobeba: le gabusiga: manoma ulagi, amo defele ilia dia da: i hodo dawa: beba: le, gabusiga: manoma ulagimu. Ilia da di dawa: beba: le, didigia: le amane sia: mu, ‘Ninia hina bagade da bogoi dagoi!’ Na, Hina Gode, da sia: i dagoi.”
ìwọ yóò kú ní àlàáfíà. Bí àwọn ènìyàn sì ti ń ṣe iná ìsìnkú ní ọlá fún àwọn baba rẹ, ọba tí ó jẹ ṣáájú rẹ, bẹ́ẹ̀ ni wọn yóò ṣe iná ní ọlá rẹ, wọn ó sì pohùnréré pé, “Yé, olúwa!” Èmi fúnra mi ni ó ṣèlérí yìí ni Olúwa wí.’”
6
Nígbà náà ni Jeremiah wòlíì sọ gbogbo nǹkan yìí fún Sedekiah ọba Juda ní Jerusalẹmu.
7 Ba: bilone hina bagade ea dadi gagui wa: i da Yelusalemega doagala: loba, na da Yelusaleme moilai bai bagade ganodini amo sia: hina bagade Sedegaia ema adole iasi. Gagili sali moilai bai bagade aduna fawane (La: igisi amola Asiga) da Yuda soge ganodini ba: i. Ba: bilone dadi gagui da elema doagala: lebe ba: i.
Nígbà tí ogun ọba Babeli ń bá Jerusalẹmu jà, àti gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè tí ó kù ní Juda, Lakiṣi, Aseka; àwọn nìkan ni ìlú olódi tí ó kù ní Juda.
8 Yuda hina bagade Sedegaia amola Yelusaleme fi dunu da ilia Hibulu udigili hawa: hamosu dunu amola uda ilia udigili hawa: hamosu logo doasima: ne sia: i. Bai dunu huluane da Isala: ili na: iyado dunu udigili hawa: hamosu dunu agoane esaloma: ne hamedafa ba: mu, ilia dawa: i.
Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ Jeremiah wá lẹ́yìn ìgbà tí ọba Sedekiah ti dá májẹ̀mú pẹ̀lú gbogbo àwọn ènìyàn ní Jerusalẹmu láti polongo ìtúsílẹ̀ fún àwọn ẹrú.
9
Kí oníkálùkù lè jẹ́ kí ẹrúkùnrin àti ẹrúbìnrin tí í ṣe Heberu lọ lọ́fẹ̀ẹ́, kí ẹnikẹ́ni kí ó má mú ará Juda arákùnrin rẹ̀ sìn.
10 Dunu huluane amola ouligisu dunu huluane da gousa: su agoane hamoi. Ilia da ilia udigili hawa: hamosu dunu ilia udigili hawa: hamosu logo doasili, bu udigili hawa: hamosu dunu hame lamu. Ilia da dafawane ilia udigili hawa: hamosu logo doasi.
Nítorí náà, gbogbo àwọn aláṣẹ àti àwọn ènìyàn tí wọ́n fi ọwọ́ sí májẹ̀mú náà láti dá ẹrúkùnrin àti ẹrúbìnrin sílẹ̀ kí wọ́n sì má ṣe fi wọ́n sínú ìgbèkùn mọ́. Wọ́n sì gbà, wọ́n sì jẹ́ kí wọn lọ lọ́fẹ̀ẹ́.
11 Be fa: no, ilia da ilia asigi dawa: su afadenei. Ilia amo hawa: hamosu dunu bu gasawane lale, ilia bu udigili hawa: hamoma: ne sesei.
Ṣùgbọ́n lẹ́yìn ìgbà díẹ̀, wọ́n yí ọkàn wọn padà; wọ́n sì mú àwọn ẹrú tí wọ́n ti dá sílẹ̀ padà láti tún máa sìn wọ́n.
Nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ Jeremiah wá wí pé:
13 Amalalu, Hina Gode, Isala: ili fi ilia Gode, da fi dunu ilima amane adole iasima: ne sia: i, “Na da dilia aowalalia Idibidi soge ganodini udigili hawa: hamonanebe amo gaga: le, fisili masa: ne, ga oule asi. Na da ilima Gousa: su hamoi, amane,
“Èyí ni ohun tí Olúwa, Ọlọ́run Israẹli wí pé: Mo dá májẹ̀mú kan pẹ̀lú àwọn baba ńlá yín nígbà tí mo mú wọn kúrò ní Ejibiti; kúrò ní oko ẹrú. Mo wí pé,
14 ‘Ode gafeyale gidigili, ode fesu amoga, ilia da Hibulu udigili hawa: hamosu dunu amola uda huluane da ode gafeyale hawa: hamobeba: le, ilia udigili hawa: hamosu logo doasima: ne, Na da sia: i dagoi. Be dilia aowalalia da Na sia: hamedafa nabi.
‘Ní ọdún keje, ẹnìkọ̀ọ̀kan yín gbọdọ̀ tú àwọn Heberu tí wọ́n ti ta ara wọn fún un yín sílẹ̀ lẹ́yìn tí wọ́n ti sìn yín fún ọdún mẹ́fà. Ẹ gbọdọ̀ jẹ́ kí wọn kí ó lọ’; ṣùgbọ́n àwọn baba yín kò gbọ́; bẹ́ẹ̀ ni wọn kò fetí sí mi.
15 Dilia da gasida agoanega, dilia asigi dawa: su afadenene, Na hahawane ba: ma: ne hamoi dagoi. Dilia huluane da sia: afadafa hamone, dilia Isala: ili na: iyado dunu ilia halegale masa: ne, ilia udigili hawa: hamosu logo doasima: ne sia: i. Amola amo hamoma: ne, dilia da Na Debolo (amo ganodini dilia da Nama nodone sia: ne gadosa) amo ganodini gousa: su hamoi.
Láìpẹ́ yìí ẹ ti ronúpìwàdà, ẹ sì ṣe ohun tí ó tọ́ lójú mi, ẹnìkọ̀ọ̀kan yín sì ṣe ìtúsílẹ̀ fún àwọn ènìyàn. Ẹ sì tún bá mi dá májẹ̀mú ní àwọn ilé tí a ti ń pe orúkọ mi.
16 Be dilia da dilia asigi dawa: su bu afadenene amola Nama baligi fa: su. Dilia huluane da udigili hawa: hamosu dunu amola uda ilia udigili hawa: hamosu logo doasi, amo bu samogene amola gasawane ilia bu udigili hawa: hamoma: ne logei.
Ṣùgbọ́n ẹ̀yin yípadà, ẹ sì sọ orúkọ mi di èérí, olúkúlùkù sì mú kí àwọn ẹni rẹ tí ó ti sọ di òmìnira bí ọkàn wọn ti fẹ́ padà; ẹ̀yin sì tún fi wọ́n ṣe ẹrú.
17 Amaiba: le, wali Na, Hina Gode, da dilia Nama hame nabasu hou hamosu sia: sa. Dilia da dilia na: iyado Isala: ili dunu ilia udigili hawa: hamosu logo hame doasi. Defea! Na da dilia logo doasimu. Dilia da gegesu amola olosu amola ha: bagade amoga bogoma: ne, Na da dilia logo doasimu. Na da dilima hamobeba: le, osobo bagade fifi asi gala huluane da beda: iwane fofogadigimu.
“Nítorí náà báyìí ni Olúwa wí: Ẹ̀yin kò fetí sí mi nípa ọ̀rọ̀ òmìnira láàrín ẹ̀gbọ́n sí àbúrò, láàrín ẹnìkan sí èkejì rẹ̀. Wò ó, èmi yóò kéde òmìnira fún un yín ni Olúwa wí. Sí idà, sí àjàkálẹ̀-ààrùn, àti sí ìyàn, èmi ó sì fi yín fún ìwọ̀sí ní gbogbo ìjọba ilẹ̀ ayé.
Èmi ó ṣe àwọn ọkùnrin náà tí ó da májẹ̀mú mi, tí kò tẹ̀lé májẹ̀mú tí wọ́n ti dá níwájú mi bí ẹgbọrọ màlúù tí wọ́n gé sí méjì, tí ó sì kọjá láàrín ìpín méjì náà.
19 Yuda amola Yelusaleme fi ouligisu dunu amola hina bagade ea ouligisu dunu amola gobele salasu dunu da Nama gousa: su hamoi. Ilia da gawali bulamagau amo oudahida: le, la: ididili la: ididili ligisili, dogoa asili amola gousa: su hamoi. Be ilia da amo gousa: su fi dagoi amola ea sema amola hamoma: ne sia: i hamedafa hamosu. Amaiba: le, Na da amo dunu ilima ilia bulamagau hamoi defele, ilima hamomu.
Àwọn ìjòyè Juda àti àwọn ti Jerusalẹmu, àwọn aláṣẹ àti àwọn àlùfáà àti gbogbo àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà tí ó kọjá láàrín àwọn ìpín méjèèjì ẹgbọrọ màlúù náà.
20 Ilia ha lai dunu da ili medole legemusa: hanaiba: le, Na da ilima imunu. Ilia bogoi da: i hodo da sio amola sigua ohe amoga na dagoi ba: mu.
Èmi ó fi wọ́n lé ọwọ́ àwọn ọ̀tá wọn, àti lé àwọn tí ń wá ẹ̀mí wọn lọ́wọ́. Òkú wọn yóò jẹ́ oúnjẹ fún àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run àti fún àwọn ẹranko igbó.
21 Na da Yuda hina bagade Sedegaia amola ea eagene ouligisu dunu amo ilia ha lai dunu (ili medole legemusa: hanai) ilima imunu. Na da ili Ba: bilone dadi gagui wa: i ilima imunu. Ba: bilone dadi gagui da wali Yelusaleme amoma doagala: su amo yolesi.
“Sedekiah ọba àti àwọn ìjòyè rẹ̀ ní Juda ni èmí yóò fi lé àwọn ọ̀tá wọn lọ́wọ́, àti àwọn tí ń wá ẹ̀mí wọn àti lé ọwọ́ ogun Babeli tí ó ti lọ kúrò lọ́dọ̀ yín.
22 Be Na da ilima sia: nanu, ilia da amo moilai bai bagadega buhagili, doagala: le, hasalili, laluga ulagimu. Na hamobeba: le, Yuda moilai huluane da dunu hame esalebe, wadela: i hafoga: i soge agoane ba: mu. Na, Hina Gode, da sia: i dagoi.”
Wò ó èmi ó pàṣẹ ni Olúwa wí, èmi ó sì mú wọn padà sí ìlú yìí, wọn ó sì bá a jà, wọn ó sì kó o, wọn ó fi iná jó o. Èmi ó sì sọ ìlú Juda dí ahoro.”

< Yelemaia 34 >