< Yelemaia 31 >
1 Hina Gode da amane sia: sa, “Eso da misunu amoga Na da Isala: ili fi huluane ilima ilia Godedafa ba: mu, amola ilia huluane da Na fi dunu ba: mu.
“Nígbà náà, Èmi yóò jẹ́ Ọlọ́run fún gbogbo ìdílé ìran Israẹli, àwọn náà yóò sì jẹ́ ènìyàn mi,” ni Olúwa wí.
2 Hafoga: i soge ganodini, Na da dunu amo da hame bogoi esalu, ilima Na asigi hou olelei. Isala: ili dunu da helebeba: le, helefimu hanai gala: loba,
Èyí ni ohun tí Olúwa wí: “Àwọn ènìyàn tí ó sá àsálà lọ́wọ́ idà yóò rí ojúrere Olúwa ní aṣálẹ̀, Èmi yóò sì fi ìsinmi fún Israẹli.”
3 Na da sedaga esalu, amoga ili ba: ma: ne misi. Isala: ili dunu! Na da eso huluane mae yolesili, dilima asigi galu. Amola Na da wali mae yolesili, Na eso huluane dialoma: ne asigi hou dilima olelelalumu.
Olúwa ti fi ara rẹ̀ hàn wá ní ìgbà kan rí, ó wí pé: “Èmi ti nífẹ̀ẹ́ yín pẹ̀lú ìfẹ́ àìlópin; mo ti fi ìfẹ́ ńlá fà yín,
4 Na da bu eno dili gagumu. Dilia da gesami liligi bu gaguia gadole, hahawane gosa: ma.
Èmi yóò tún gbé e yín sókè, àní a ó tún gbé e yín ró ìwọ wúńdíá ilẹ̀ Israẹli. Àní ẹ ó tún tún ohun èlò orin yín gbé, ẹ ó sì jáde síta pẹ̀lú ijó àti ayọ̀.
5 Dilia da bu Samelia agolo amo da: iya waini efe sagamu, amola bugi dunu da amo sagai ea fage manu.
Ẹ ó tún gbin ọgbà àjàrà ní orí òkè Samaria; àwọn àgbẹ̀ yóò sì máa gbádùn èso oko wọn.
6 Dafawane, eso da doaga: mu amoga sosodo aligisu dunu da Ifala: ime agologa amane wele sia: mu, ‘Ninia da Saione amoga masunu. Hadiga! Ninia Hina Godema heda: la: di.’”
Ọjọ́ kan máa wà tí àwọn olùṣọ́ yóò kígbe jáde lórí òkè Efraimu wí pé, ‘Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí a gòkè lọ sí Sioni, ní ọ̀dọ̀ Olúwa Ọlọ́run wa.’”
7 Hina Gode da amane sia: sa, “Isala: ili ea houba: le, hahawane gesami hea: ma. Isala: ili da fifi asi gala huluane baligisa. Dilia nodone gesami amane hea: ma! ‘Hina Gode da Ea fi dunu gaga: i dagoi. Huluane hame bogoi esala, E da gaga: i dagoi!’
Èyí ni ọ̀rọ̀ tí Olúwa sọ wí pé: “Ẹ fi ayọ̀ kọrin sí Jakọbu; ẹ hó sí olórí àwọn orílẹ̀-èdè gbogbo. Jẹ́ kí wọ́n gbọ́ ìyìn rẹ kí o sì wí pé, ‘Olúwa, gba àwọn ènìyàn rẹ là; àwọn tí ó ṣẹ́kù ní Israẹli.’
8 Na da ili gagoe (north) amola osobo bagade bega: bega: amoga lale, oule misunu. Si dofoi, emo gasuga: igi, abula agui uda amola uda da mano lalelegemu gadenesa, amo huluane da ili sigi misunu. Ilia da fi bagadedafa agoane buhagimu.
Wò ó, Èmi yóò mú wọn wá láti ilẹ̀ àríwá; èmi yóò kó gbogbo wọn jọ láti òpin ayé. Lára wọn ni yóò jẹ́ afọ́jú àti arọ, aboyún àti obìnrin tí ń rọbí, ọ̀pọ̀ ènìyàn yóò wá.
9 Na fi dunu da dinanawane amola sia: ne gadolalawane bu misunu amola Na da ili bisimu. Na da hano noga: i amoga ili oule masunu. Na da ili mae dafama: ne, logo noga: idafa amoga ili asula masunu. Na da Isala: ili fi ilima Ada agoane esala, amola Na magobo mano da Ifala: ime.”
Wọn yóò wá pẹ̀lú ẹkún, wọn yóò gbàdúrà bí Èmi yóò ṣe mú wọn padà. Èmi yóò jẹ́ atọ́nà fún wọn ní ẹ̀bá odò omi; ní ọ̀nà tí ó tẹ́jú tí wọn kì yóò le ṣubú, nítorí èmi ni baba Israẹli, Efraimu sì ni àkọ́bí ọkùnrin mi.
10 Hina Gode da amane sia: sa, “Fifi asi gala huluane! Na sia: nabima! Amola Na sia: amo soge baligili sedaga amoga olelema. Na da Na fi afagogoi, be Na da ili bu gagadole, sibi ouligisu da ea sibi sosodo ouligisu defele, ili sosodo ouligimu.
“Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa ẹ̀yin orílẹ̀-èdè ẹ kéde rẹ̀ ní erékùṣù jíjìn; ‘Ẹni tí ó bá tú Israẹli ká yóò kójọ, yóò sì ṣọ́ agbo rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí olùṣọ́-àgùntàn.’
11 Na da fedege agoane, Isala: ili ea se iasu logo doasi dagoi. Amola gasa bagade fi da Na fi wadela: musa: dawa: i, be Na da Na fi dunu gaga: i.
Nítorí Olúwa ti tú Jakọbu sílẹ̀, o sì rà á padà ní ọwọ́ àwọn tí ó lágbára jù ú lọ.
12 Ilia da misini, hahawaneba: le, Saione Goumia gesami hea: mu. Na da hahawane iasu ilima imunu, amo gagoma, waini hano, olife susuligi, sibi amola bulamagau. Ilia da Na iabe hahawane ba: mu. Ilia da ifabi amoga gibu defele daha, amaiwane ba: mu. Ilia hanai defele, ilia da lai dagoi ba: mu.
Wọn yóò wá, wọn ó sì hó ìhó ayọ̀ lórí òkè Sioni; wọn yóò yọ ayọ̀ níbi oore Olúwa. Àlìkámà ni, ọtí wáìnì tuntun àti òróró ọ̀dọ́-àgùntàn àti ọ̀dọ́ ọ̀wọ́ ẹran. Wọn ó dàbí ọgbà àjàrà tí a bomirin, ìkorò kò ní bá wọn mọ́.
13 Amasea, uda mano da hahawane gosa: mu. Amola dunu, ayeligi amola da: i hamoi da hahawane bagade dawa: mu. Na da ilia dogo denesimu amola ilia da: i dioi afadenene, bu hahawane hou hamomu.
Àwọn wúńdíá yóò jó, wọn ó sì kún fún ayọ̀, bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni ọkùnrin àti obìnrin. Èmi yóò sọ ọ̀fọ̀ wọn di ayọ̀, dípò ìkorò èmi yóò tù wọ́n nínú. Èmi ó sì fún wọn ní ayọ̀.
14 Na da ilia gobele salasu dunu amo sadima: ne, ilima ha: i manu baligili noga: i imunu. Amola Na fi dunu ilia hanai liligi amo ilima imunu. Na, Hina Gode da sia: i dagoi.”
Èmi ó tẹ́ àwọn àlùfáà lọ́rùn pẹ̀lú ọ̀pọ̀; àwọn ènìyàn mi yóò sì kún fún oore mi,” ni Olúwa wí.
15 Hina Gode da amane sia: sa, “La: ima moilaiga ilia didigia: be sia: naba. La: ima fi da ilia mano huluane fisili asi dagoiba: le, dinana. Ilima dogo denesimu da hamedei.
Èyí ni ohun tí Olúwa wí: “A gbọ́ ohùn kan ní Rama tí ń ṣọ̀fọ̀ pẹ̀lú ẹkún kíkorò. Rakeli ń sọkún àwọn ọmọ rẹ̀; kò gbà kí wọ́n tu òun nínú, nítorí àwọn ọmọ rẹ̀ kò sí mọ́.”
16 Disu yolesima! Dilia si hano doga: ma! Dilia da dilia mano fidima: ne, gasa bagade hamoi. Amoga, dilia da bidi lamu. Ilia da dilia ha lai sogega mugululi asi. Be ilia da buhagimu.
Báyìí ni Olúwa wí: “Dá ohùn rẹ dúró nínú ẹkún àti ojú rẹ nínú omijé; nítorí a ó fi èrè sí iṣẹ́ rẹ,” ni Olúwa wí. “Wọn ó sì padà wá láti ilẹ̀ ọ̀tá.
17 Dilia da hobea hahawane ba: mu. Dilia mano da dilima bu misunu. Na, Hina Gode da sia: i dagoi.
Nítorí ìrètí wà fún ọjọ́ iwájú rẹ,” ni Olúwa wí. “Àwọn ọmọ rẹ yóò padà wá sí ilẹ̀ wọn.
18 Na da Isala: ili dunu ilia sia: naba. Ilia da da: i dioiba: le amane sia: sa, ‘Hina Gode! Ninia da hame fofoi sigua ohe agoai gala. Be Di da Dia sia: nabima: ne ninima olelei dagoi. Nini buhagima: ne oule misa! Dia da ninia Hina Godedafa! Ninia Dima sinidigima: ne momagei dagoi.
“Nítòótọ́, èmi ti gbọ́ ìpohùnréré Efraimu wí pé, ‘Ìwọ ti bá mi wí gẹ́gẹ́ bí ọmọ màlúù tí a kò kọ́ èmi sì ti gbọ́ ìbáwí. Rà mí padà, èmi yóò sì yípadà, nítorí ìwọ ni Olúwa Ọlọ́run mi.
19 Ninia da Di yolesi be fonobahadi ouesalu, Dima bu sinidigima: ne hanai galu. Di da ninima se iabeba: le, ninia da da: i dioiba: le, dialuma fili sa: i. Ninia da gogosia: i dagoi, Bai ninia goihadini esogainini wadela: le hamoi dagoi.’”
Lẹ́yìn tí èmi ti yípadà, mo ronúpìwàdà, lẹ́yìn tí èmi ti wá mọ̀, èmi lu àyà mi. Ojú tì mí, mo sì dààmú; nítorí èmi gba èrè ẹ̀gàn ìgbà èwe mi.’
20 Hina Gode da amane sia: sa, “Isala: ili! Di da Na dogolegei mano! Di da Na mano amola Na da dima baligili asigisa! Na da dia dio sia: sea, dima asigiwane dawa: lala. Di da Na dogolegei mano. Na da di se mae nabima: ne, asigimu.
Efraimu kì í ha í ṣe ọmọkùnrin mi dáradára tí inú mi dùn sí bí? Bí èmi ti ń sọ̀rọ̀ sí i tó, síbẹ̀, èmi rántí rẹ̀. Nítorí náà, ọkàn mi ṣe ohun kan fún un, èmi káàánú gidigidi fún un,” ni Olúwa wí.
21 Dawa: digisu alalo hahamone, buhagimu logo olelema! Dia asi logo amoga buhagima! Isala: ili fi dunu! Bu misa! Moilai amo dilia yolesi, amoga buhagima!
“Gbé àmì ojú ọ̀nà dìde, ṣe atọ́nà àmì, kíyèsi òpópó ọ̀nà geere ojú ọ̀nà tí ó ń gbà. Yípadà ìwọ wúńdíá Israẹli, padà sí àwọn ìlú rẹ.
22 Dilia hame nabasu dunu! Dilia da habowali seda logo aduna amoga masunusa: dadawa: ma: bela: ? Na da hou gaheabolo amola hisu hahamoi dagoi. Uda da dunu gaga: mu - amo da osobo bagade hou hisu agoane. Amo defele, Na da hou hisu hahamoi dagoi.”
Ìwọ yóò ti ṣìnà pẹ́ tó, ìwọ aláìṣòótọ́ ọmọbìnrin; Olúwa yóò dá ohun tuntun lórí ilẹ̀, ọmọbìnrin kan yóò yí ọkùnrin kan ká.”
23 Hina Gode Bagadedafa, Isala: ili fi ilia Gode, da amane sia: sa, “Na da Na fi dunu ilia sogedafa amoga bu oule masea, ilia Yuda soge amola ea moilai huluane amo ganodini bu amane sia: mu, ‘Hina Gode da Yelusaleme sema agolo amoma hahawane hamomu da defea. E da amo hadigi sogebi amo ganodini esala.’
Báyìí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun Israẹli wí: “Nígbà tí èmi bá kó wọn dé láti ìgbèkùn; àwọn ènìyàn tí ó wà ní ilẹ̀ Juda àti ní àwọn ìlú rẹ̀ yóò tún lo àwọn ọ̀rọ̀ yìí lẹ́ẹ̀kan sí i; wí pé, ‘Kí Olúwa kí ó bùkún fún ọ, ìwọ ibùgbé òdodo, ìwọ òkè ìwà mímọ́.’
24 Dunu fi da Yuda soge amola ea moilai huluane ganodini esalebe ba: mu. Amola amo ganodini, ifabi ouligisu dunu amola sibi ouligisu dunu amola ilia sibi wa: i da esalebe ba: mu.
Àwọn ènìyàn yóò gbé papọ̀ ní Juda àti ní gbogbo àwọn ìlú rẹ̀; bákan náà ni àgbẹ̀ àti àwọn tí ń tẹ̀lé agbo ẹran wọn ká.
25 Na da helei nabi dunu amo nasegagimu amola dunu ha: iba: le gasa hame, amo sadima: ne, ha: i manu imunu.
Èmi yóò sọ aláàárẹ̀ di ọ̀tun, èmi yóò sì tẹ́ gbogbo ọkàn tí ń káàánú lọ́rùn.”
26 Amasea, dunu da amane sia: mu, ‘Na da golale, nedigili, da: i hagi ba: i.’
Lórí èyí ni mo jí, mo sì wò yíká, oorun mi sì dùn mọ́ mi.
27 Na, Hina Gode, da amane sia: sa, ‘Eso da misunu, amoga Na da Isala: ili soge amola Yuda soge amo dunu amola ohe amoga nabamu.
“Wò ó, ọjọ́ ń bọ̀,” ni Olúwa wí, “nígbà tí èmi yóò gbin ilé Israẹli àti ilé Juda pẹ̀lú irúgbìn ọmọ ènìyàn àti ẹranko.
28 Amola musa: Na da dawa: iwane fadegale fasi amola wadela: lesi, amola mugului, amo defele Na da dawa: iwane bugimu amola hiougimu.
Gẹ́gẹ́ bí mo ṣe ń ṣọ́ wọn, láti fàtu, àti láti wó lulẹ̀, àti láti gba ìṣàkóso, láti bàjẹ́ àti láti mú ibi wá, bẹ́ẹ̀ ni èmi yóò ṣọ́ wọn láti kọ́ àti láti gbìn,” ni Olúwa wí.
29 Amo eso doaga: sea, dunu da bu hame sia: mu, ‘Ada amola ame da gamogai waini fage mai - be ilia mano fawane da gamogai nabi.’
“Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì àwọn ènìyàn kò ní sọ mọ́ pé: “‘Àwọn baba ti jẹ èso àjàrà àìpọ́n àti pé eyín kan àwọn ọmọdé.’
30 Be nowa da gamogai waini fage nasea, hisu da gamogai nabimu. Amola dunu da hi wadela: i hou hamoiba: le fawane bogomu.”
Ṣùgbọ́n olúkúlùkù ni yóò kú fún ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀, ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ èso kíkan ni eyín yóò kan.
31 Hina Gode da amane sia: sa, “Eso da misunu, amoga Na da gaheabolo Gousa: su Amo sia: ea bai da Hibulu sia: ganodini molole hame ba: sa. amo Isala: ili dunu amola Yuda dunu ilima hamomu.
“Ìgbà kan ń bọ̀,” ni Olúwa wí, “tí Èmi yóò bá ilé Israẹli àti ilé Juda dá májẹ̀mú tuntun.
32 Musa: Na da ilia aowalalia ilia lobolele, Idibidi soge yolesimusa: gadili oule asili, ilima Gousa: su hamoi. Be gaheabolo Gousa: su da musa: hamoi defele hame ba: mu. Na da ilima egoa agoane hamoi, be ilia da amo Gousa: su sema nabawane hame hamosu.
Kò ní dàbí májẹ̀mú tí mo bá àwọn baba ńlá wọn dá, nígbà tí mo fà wọ́n lọ́wọ́, tí mo mú wọn jáde ní Ejibiti nítorí wọ́n da májẹ̀mú mi. Lóòótọ́ ọkọ ni èmi jẹ́ fún wọn,” ni Olúwa wí.
33 Gaheabolo Gousa: su amo Na da Na Isala: ili fi ilima hamomu da agoane ba: mu. Na da Na sema ilia da: i hodo ganodini salimu, amola Na sema ilia dogo da: iya dedemu. Na da ilia Gode esalumu, amola ilia da Na fi dunu esalumu.
“Èyí ni májẹ̀mú tí èmi yóò bá ilé Israẹli dá lẹ́yìn ìgbà náà,” ni Olúwa wí pé: “Èmi yóò fi òfin mi sí ọkàn wọn, èmi ó sì kọ ọ́ sí àyà wọn. Èmi ó jẹ́ Olúwa wọn; àwọn ó sì jẹ́ ènìyàn mi.
34 Ilia da afae afae ilia fi dunu eno ilima Godema dawa: su hou bu hame olelemu. Bai ilia huluane, dunu bagade amola fonobahadi, huluanedafa da Na dawa: mu. Na da ilia wadela: i hou gogolema: ne olofomu, amola Na da ilia wadela: i hou bu hamedafa dawa: mu. Na, Hina Gode, da sia: i dagoi.”
Kò ní sí pé ọkùnrin kan ń kọ́ àwọn ará ilé rẹ̀ tàbí ọkùnrin ń kọ́ arákùnrin rẹ̀ pé, ‘Ẹ mọ Olúwa,’ nítorí gbogbo wọn ni yóò mọ̀ mí láti ẹni kékeré wọn títí dé ẹni ńlá,” ni Olúwa wí. “Nítorí èmi ó dárí àìṣedéédéé wọn jì, èmi kò sì ní rántí ẹ̀ṣẹ̀ wọn mọ́.”
35 Hina Gode da haga ninia hadigi ba: ma: ne, eso iaha. Amola gasi ganodini E da oubi amola gasumuni iaha. E da hano wayabo bagade guma: ne, bibiogosa. Ea dio da Hina Gode Bagadedafa.
Èyí ni ohun tí Olúwa wí: ẹni tí ó mú oòrùn tan ìmọ́lẹ̀ ní ọ̀sán, tí ó mú òṣùpá àti ìràwọ̀ ràn ní òru; tí ó rú omi Òkun sókè tó bẹ́ẹ̀ tí ìjì rẹ̀ fi ń hó Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni orúkọ rẹ̀.
36 Amo osobo bagade hou da dialebe ba: sea, Isala: ili fidafa agoane dialebe ba: mu. Bai Hina Gode da agoane ilegei dagoiba: le.
“Àyàfi tí ìlànà yìí bá kúrò níwájú mi,” ni Olúwa wí. “Ǹjẹ́ àwọn ọmọ Israẹli yóò dẹ́kun láti jẹ́ orílẹ̀-èdè níwájú mi láéláé.”
37 Osobo bagade dunu da mu amola osobo bagade bai, amo ilia ba: de amola sedade defei dawa: mu da hamedei. Amo defele, Hina Gode da Ea fi Isala: ili amo ilia hou hamobeba: le higale yolesimu da hamedei. Hina Gode da sia: i dagoi.
Èyí ni ohun tí Olúwa wí: “Àyàfi tí a bá lé àwọn ọ̀run lókè tí ìpìlẹ̀ ayé sì di àwárí ní ìsàlẹ̀, ni èmi yóò kọ àwọn Israẹli nítorí ohun gbogbo tí wọ́n ti ṣe,” ni Olúwa wí.
38 Hina Gode da amane sia: sa, “Eso da doaga: mu, amoga Yelusaleme da bu gaguli, Na moilai bai bagadedafa agoane bu ba: mu. Ilia bu hiougisia, moilai bai bagade da Hana: niele diasu gado gagagula heda: i amoga guma: asili, Sisigagala: i Logo Ga: su amoga doaga: mu.
“Ọjọ́ náà ń bọ̀,” ni Olúwa wí, “tí wọn yóò tún ìlú yìí kọ́ fún mi láti ilé ìṣọ́ Hananeli dé igun ẹnu ibodè.
39 Amola bega: alalo da bu guma: asili, Ga: ilebe Agolo amo baligili, Goua: be sogebiga doaga: mu.
Okùn ìwọ̀n yóò sì nà jáde láti ibi gígùn lọ sí òkè Garebu yóò sì lọ sí Goa.
40 Fago sogebi huluanedafa, bogoi dunu uli dogosu sogebi amola isu salasu sogebi amola soge huluane Gidalone Hano gadodili amo gusudili asili Hosi Logo Holei amoga doaga: sa, amo huluane da Na sema soge dialebe ba: mu. Yelusaleme da eso huluane dialumu. Moilai bai bagade da ha lai amoga mugului amola wadela: lesi dagoi bu hamedafa ba: mu.”
Gbogbo àfonífojì níbi tí wọ́n ń da òkú àti eérú sí, àti gbogbo àfonífojì Kidironi ní ìhà ìlà-oòrùn títí dé igun ẹnu ibodè ẹṣin yóò jẹ́ mímọ́ sí Olúwa. A kì yóò fa ìlú náà tu tàbí kí a wó o palẹ̀.”