< Yelemaia 29 >

1 Na da gobele salasu dunu, balofede dunu, ouligisu dunu amola dunu huluane amo Nebiuga: denese da Yelusaleme amoga lale, afugili Ba: bilone sogega oule asi, ilima meloa dedene i.
Èyí ni ọ̀rọ̀ inú lẹ́tà tí wòlíì Jeremiah rán láti Jerusalẹmu sí ìyókù nínú àwọn àgbàgbà tí ó wà ní ìgbèkùn àti sí àwọn àlùfáà, àwọn wòlíì àti gbogbo àwọn ènìyàn tí Nebukadnessari tí kó ní ìgbèkùn láti Jerusalẹmu lọ sí Babeli.
2 Musa: Yuda hina bagade Yehoiagini, ea: me, hina bagade diasu eagene ouligisu dunu amola bagade dawa: su hawa: hamosu dunu huluane da mugululi asi dagoi ba: i. Amogalu fa: no, na da meloa dedene i.
Lẹ́yìn ìgbà tí Jekoniah, ọba, àti ayaba, àti àwọn ìwẹ̀fà, àti àwọn ìjòyè Juda àti Jerusalẹmu, àwọn gbẹ́nàgbẹ́nà àti àwọn olùyàwòrán tí wọ́n lọ ṣe àtìpó láti Jerusalẹmu.
3 Hina bagade Sedegaia da Elasa (Sia: ifa: ne egefe) amola Gemalaia (Hiligaia egefe) amo hina bagade Nebiuga: denese ilima asunasimusa: dawa: i. Na da na meloa dedene, elama i.
Ó fi lẹ́tà náà rán Eleasa ọmọ Ṣafani àti Gemariah ọmọ Hilkiah, ẹni tí Sedekiah ọba Juda rán sí Nebukadnessari ọba Babeli. Wí pé.
4 Na da agoane dedei, “Hina Gode Bagadedafa, Isala: ili fi ilia Gode, da dunu huluane amo Nebiuga: denese da Yelusaleme amoga lale, Ba: bilone amoga afugili oule masa: ne, Hina Gode da logo doasi, ilima amane sia: sa,
Èyí ni ọ̀rọ̀ tí Olúwa Ọlọ́run Alágbára Israẹli sọ fún gbogbo àwọn ènìyàn tí mo kó lọ ṣe àtìpó láti Jerusalẹmu ní Babeli:
5 ‘Dilia diasu gaguli, hahawane fima. Ifabi bugili, ha: i manu faili manu.
“Ẹ kọ́ ilé kí ẹ sì máa gbé ibẹ̀, ẹ dá oko, kí ẹ sì máa jẹ èso ohun ọ̀gbìn oko yín.
6 Uda lasu hou hamone, mano lama. Amola dilia mano da uda lamu amola mano lalelegema: mu. Dilia fi idi da mae fonobone, heda: mu da defea.
Ẹ ṣe ìgbéyàwó, kí ẹ sì bí ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin, ẹ gbé ìyàwó fún àwọn ọmọkùnrin yín, kí ẹ sì fi àwọn ọmọbìnrin yín fún ọkọ. Kí àwọn náà lè ní ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin. Ẹ máa pọ̀ sí i ní iye, ẹ kò gbọdọ̀ dínkù ní iye níbẹ̀ rárá.
7 Na da dili Ba: bilone moilai bai bagadega udigili hawa: hamoma: ne, logo fodoi. Amaiba: le, amo moilai bai bagade fidima: ne, dilia hawa: hamoma. Amo moilai bai bagade fi ilia da hahawane bagade gaguiwane dialoma: ne, Nama sia: ne gadoma. Bai ilia da bagade gaguiwane ba: sea, dilia amola da bagade gaguiwane ba: mu.
Bákan náà, ẹ máa wá àlàáfíà àti ìre ìlú, èyí tí mo kó yín lọ láti ṣe àtìpó. Ẹ gbàdúrà sí Olúwa fún ìre ilẹ̀ náà; nítorí pé bí ó bá dára fún ilẹ̀ náà, yóò dára fún ẹ̀yin pẹ̀lú.”
8 Na, Hina Gode, Isala: ili fi ilia Gode, da dilima sisasu iaha. Balofede dunu dilia gilisili esala da hobea misunu hou dawa: be olelesa. Be ilia da ogogosa, amola dilima ogogosa: besa: le, ilia sia: mae nabima. Ilia simasia ba: i liligi mae dawa: ma.
Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun Ọlọ́run Israẹli wí: “Ẹ má ṣe gbà kí àwọn wòlíì èké àti àwọn aláfọ̀ṣẹ àárín yín tàn yín jẹ. Ẹ má ṣe fetísílẹ̀ sí àlá, èyí tí ẹ gbà wọ́n níyànjú láti lá.
9 Ilia da Na Dioba: le, dilima ogogosa. Na da amo dunu hamedafa asunasi. Na, Hina Gode Bagadedafa da sia: i dagoi.’
Wọ́n ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ èké fún yín lórúkọ mi, Èmi kò rán wọn níṣẹ́,” ni Olúwa wí.
10 Hina Gode da amane sia: sa, ‘Ba: bilone fi ilia dilima ouligibi ode70 da gidigisia, Na da dilima asigi hou bu olelemu. Na da dilia sogedafa amoga buhagima: ne oule misunu.
Báyìí ni Olúwa wí: “Nígbà tí ẹ bá lo àádọ́rin ọdún pé ní Babeli, èmi yóò tọ̀ yín wá láti ṣe àmúṣẹ ìlérí ńlá mi fún un yín, àní láti kó o yín padà sí Jerusalẹmu.
11 Na fawane da Na dilima imunu ilegei dawa: Amo ilegei da dilima wadela: su hame be hahawane hou fawane imunu. Amo ilegei da dilima hobea misunu hou, hahawane esaloma: beyale bagade hou amo dilia hanai liligi, amo dilima iasimu.
Nítorí mo mọ èrò tí mo rò sí yín,” ni Olúwa wí, “àní èrò àlàáfíà, kì í sì ṣe fún ibi, èrò láti fún un yín ní ìgbà ìkẹyìn àti ìrètí ọjọ́ iwájú.
12 Amasea, dilia da Nama wele sia: mu. Dilia da Nama sia: ne gadomu, amola Na da dilima bu adole imunu.
Nígbà náà ni ẹ̀yin yóò ké pè mí, tí ẹ̀yin yóò sì gbàdúrà sí mi, tí èmi yóò sì gbọ́ àdúrà yín.
13 Dilia da Na hogoi helemu amola dilia da Na ba: mu. Bai dilia da dilia dogoga asigi dawa: su huluanedafa amoga Na hogoi helemu.
Ẹ̀yin yóò wá mi, bí ẹ̀yin bá sì fi gbogbo ọkàn yín wá mi: ẹ̀yin yóò rí mi ni Olúwa Ọlọ́run wí.
14 Dafawane! Dilia da Na ba: mu amola Na da dilia sogedafa amoga bu oule masunu. Na da soge huluane amola sogebi huluane amoga Na da musa: dili afagogoi, amoga Na da dili bu gagadole, dilia sogedafa (amoga Na da dili musa: mugululi masa: ne fadegai) amoga bu oule masunu. Na Hina Gode, da sia: i dagoi.’
Èmi yóò di rí rí fún yín ni Olúwa wí, Èmi yóò sì mú yín padà kúrò ní ìgbèkùn. Èmi yóò ṣà yín jọ láti gbogbo orílẹ̀-èdè àti ibi gbogbo tí Èmi ti lé yín jáde, ni Olúwa wí. Èmi yóò sì kó yín padà sí ibi tí mo ti mú kí a kó yín ní ìgbèkùn lọ.”
15 Dilia da sia: sa, Hina Gode da Ba: bilone soge ganodini balofede dunu dilima iaha.
Ẹ̀yin lè wí pé, “Olúwa ti gbé àwọn wòlíì dìde fún wa ní Babeli.”
16 Hina Gode Ea sia: nabima, ‘Na da hina bagade amo da Da: ibidi ea musa: ouligi soge amo ouligisa, amola dilia sosogo fi dunu amo da dili gilisili hame mugululi asi,
Ṣùgbọ́n èyí ni ọ̀rọ̀ Olúwa ní ti ọba tí ó jókòó lórí ìtẹ́ Dafidi àti ní ti gbogbo ènìyàn tó ṣẹ́kù ní ìlú yìí; àní ní ti àwọn ènìyàn yín tí kò bá yín lọ sí ìgbèkùn,
17 amo dunuma Na da gegesu amola ha: amola olo ilima iasimu. Na da ili figi fage dasaiba: le, manu da hamedei, amo defele hamomu.
bẹ́ẹ̀ ni, báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí pé, “Èmi yóò rán idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn sí àárín wọn; Èmi yóò ṣe wọ́n bí èso ọ̀pọ̀tọ́ búburú tí kò ṣe é jẹ.
18 Na da gegesu amola ha: ga bogosu amola oloi bagade amoga ili sefasimu. Amola osobo bagade fifi asi gala da ili ba: beba: le, beda: iwane fofogadigimu. Na da soge hisu hisu amoga ili afagogomu. Amola amogai esalebe dunu da ili ba: beba: le, beda: iwane fofogadigimu. Ilia da ilima oufesega: mu, amola ilia dioba: le gagabusu aligima: ne ilegemu.
Èmi yóò fi idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn lépa wọn, Èmi yóò sì sọ wọ́n di ìríra lójú gbogbo ìjọba ayé, fún ègún, àti ìyanu, àti ẹ̀sín, àti ẹ̀gàn láàrín gbogbo orílẹ̀-èdè ayé, ní ibi tí Èmi yóò lé wọn sí.
19 Ilia da Na sia: amo Na da balofede dunu ilia lafidili iasilalu amo hame nababeba: le, amo se nabasu da ilima doaga: mu. Ilia da nabimu higa: i galu.
Nítorí wọ́n kọ̀ láti gbọ́ ọ̀rọ̀ mi,” ni Olúwa Ọlọ́run wí. Ọ̀rọ̀ tí mo tún ti ẹnu àwọn ìránṣẹ́ mi wòlíì sọ ní ẹ̀yin tí ń ṣe àtìpó kò gbọ́ ni Olúwa Ọlọ́run wí.
20 Dilia dunu huluane Na da Ba: bilone sogega mugululi masa: ne asunasi! Na, Hina Gode, Na sia: nabima!’
Nítorí náà, gbogbo ẹ̀yin ìgbèkùn, ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa, ẹ̀yin tí mo rán lọ kúrò ní Jerusalẹmu lọ sí Babeli.
21 Hina Gode Bagadedafa, Isala: ili fi ilia Gode, da A: iha: be (Goula: ia egefe) amola Sedegaia (Ma: iasia egefe) ela hou olelei dagoi. Ela da Ea Dioba: le, dilima ogogolala. Hina Gode da A: iha: be amola Sedegaia amo hina bagade Nebiuga: denese ea lobo da: iya amoma imunu. Amasea, Nebiuga: denese da dilia ba: ma: ne, amo dunu medole legemu.
Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run Israẹli sọ nípa Ahabu ọmọ Kolaiah àti nípa Sedekiah ọmọ Maaseiah tí wọ́n ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ èké fún un yín lórúkọ mi: “Èmi yóò fi wọ́n lé Nebukadnessari ọba Babeli lọ́wọ́. Òun yóò sì gba ẹ̀mí wọn ní ìṣẹ́jú yìí gan an.
22 Hobea, Yelusaleme dunu da Ba: bilone sogega mugululi asi, amo ilia da gagabusu aligima: ne ilegemusa: dawa: sea, da agoane sia: mu, ‘Nebiuga: denese da Sedegaia amola A: iha: be ela esaleawane gobesili, ela da bogoi. Hina Gode da dima amo defele hamoma: ne, na da dima gagabusu aligima: ne ilegesa.’
Nítorí tiwọn, ègún yìí yóò ran gbogbo àwọn àtìpó tó wà ní ilẹ̀ Babeli láti Juda: ‘Olúwa yóò ṣe yín bí i Sedekiah àti Ahabu tí ọba Babeli dáná sun.’
23 Amo hou da elama doaga: mu, bai ilia da wadela: ledafa hamobeba: le. Ela da inia uda adole lasu amola Hina Gode Ea Dioba: le ogogosu. Ela da Hina Gode Ea higa: i liligi hamoi. E da ela hamoi amo ba: i dagoi amola fofada: su amo ganodini, E da ba: su dunu esala. Hina Gode da sia: i dagoi.”
Nítorí wọ́n ti ṣe ibi ní ilé Israẹli, wọ́n ti ṣe àgbèrè pẹ̀lú àwọn ìyàwó aládùúgbò wọn, àti ní orúkọ mi ni wọ́n ti ṣe èké, èyí tí Èmi kò rán wọn láti ṣe. Ṣùgbọ́n, Èmi mọ àwọn nǹkan wọ̀nyí, mo sì jẹ́ ẹlẹ́rìí sí i,” ni Olúwa wí.
24 Hina Gode Bagadedafa, Isala: ili fi ilia Gode, da nama na da Siema: ia (Nihelame dunu) ema sia: ma: ne sia: i. Bai Siema: ia da Yelusaleme fi dunu huluane amola gobele salasu dunu Sefanaia (Ma: iasia egefe) amola eno gobele salasu dunu huluane ilima meloa dedene i. Siema: ia da Sefanaiama amane dedene i,
Wí fún Ṣemaiah tí í ṣe Nehalami pé,
“Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Alágbára Israẹli wí: Ìwọ fi lẹ́tà ránṣẹ́ sí gbogbo àwọn ènìyàn ní Jerusalẹmu sí Sefaniah ọmọ Maaseiah tí í ṣe àlùfáà ní orúkọ mi; ó sì sọ fún Sefaniah wí pé,
26 “Hina Gode da di Yihoiada amo ea sogebi lama: ne gobele salasu hamoi. Amola wali di da bisili ouligisu dunu Debolo Diasuga gala. Dia hawa: hamosu da agoane gala. Nowa doulasi dunu hisu da balofede hi sia: sea, amo di sia: inega la: gili, ouli bulu agoane ea galogoa gasisalima.
‘Olúwa ti yàn ọ́ gẹ́gẹ́ bí àlùfáà rọ́pò Jehoiada láti máa jẹ́ alákòóso ilé Olúwa, kí o máa fi èyíkéyìí nínú àwọn aṣiwèrè tó bá ṣe bí i wòlíì si inú àgò irin.
27 Di da abuliba: le amo hou Yelemaia (A: nadode dunu) ema hame hamobela: ? Bai e da ogogole balofede ea dioba: le, ninia fi dunu ilima sia: dalu.
Nítorí náà, èéṣe tí o kò fi bá Jeremiah ará Anatoti wí. Ẹni tí ó ń dúró bí i wòlíì láàrín yín?
28 Ea logo hedofama! Bai e da dunu fi Ba: bilone sogega esala ilima ilia da ode bagohame amogawi udigili hawa: hamomuba: le, ilia da diasu gaguli, moi dogole, ha: i manu bugili, amola amo faili moma: ne sia: i.”
Ó ti rán iṣẹ́ yìí sí wa ni Babeli wí pé, àtìpó náà yóò pẹ́ kí ó tó parí, nítorí náà, ẹ kọ́ ilé kí ẹ sì máa gbé ibẹ̀, ẹ dá oko, kí ẹ sì máa jẹ èso ohun ọ̀gbìn oko yín.’”
29 Sefanaia da nama amo meloa idili i.
Sefaniah àlùfáà ka lẹ́tà náà sí etí ìgbọ́ Jeremiah tí í ṣe wòlíì.
30 Amalalu, Hina Gode da nama amane sia: i,
Nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ Jeremiah wá wí pé,
“Rán iṣẹ́ yìí sí gbogbo àwọn ìgbèkùn wí pé: ‘Èyí ni ohun tí Olúwa wí ní ti Ṣemaiah, ará Nehalami: Nítorí pé Ṣemaiah ti sọtẹ́lẹ̀ fún un yín, ṣùgbọ́n èmi kò ran an, tí òun sì ń mú u yín gbẹ́kẹ̀lé èké.
32 “Dunu huluane Ba: bilone sogega mugululi asi, ilima Siema: ia ea hou olelema: ne, Na sia: adosima, amane, ‘Na, Hina Gode, da Siema: ia amola egaga fi huluane ilima se imunu. Na da e hamedafa asunasi. Be e da ogogole e da balofede dunu sia: i, amola dilima bagade ogogoi. Na da fa: no Na fi dunuma hahawane hamomu. Be e da amo hou mae ba: le, bogomu. Bai e da Na fi ilia Nama odoga: ma: ne olelei. Na, Hina Gode da sia: i dagoi.’”
Nítorí náà báyìí ni Olúwa wí: Wò ó, èmi yóò bẹ Ṣemaiah, ará Nehalami wò, àti irú-ọmọ rẹ̀; òun kì yóò ní ọkùnrin kan láti máa gbé àárín ènìyàn yìí, bẹ́ẹ̀ ni kì yóò rí rere náà tí èmi yóò ṣe fún àwọn ènìyàn mi ni Olúwa wí, nítorí ó ti ti kéde ìṣọ̀tẹ̀ sí mi.’”

< Yelemaia 29 >