< Yelemaia 26 >

1 Yihoiagimi (Yousaia egefe) da Yuda hina bagade hou lai dagolalu,
Ní ìbẹ̀rẹ̀ pẹ̀pẹ̀ ìjọba ọba Jehoiakimu ọmọ Josiah tí ń ṣe ọba Juda, ọ̀rọ̀ yìí wá láti ọ̀dọ̀ Olúwa:
2 amalalu, Hina Gode da nama amane sia: i, “Dia Debolo gagoi amo ganodini lelu, Na sia: dima sia: ma: ne olelei, amo huluane dunu amo da Yuda moilaiga guiguda: nodone sia: ne gadomusa: misi, ilima Na sia: olelema. Sia: huluanedafa, afae mae fisili, olelema!
“Èyí ni ohun tí Olúwa wí, Dúró ní àgbàlá ilé Olúwa, kí o sì sọ fún gbogbo ènìyàn ilẹ̀ Juda tí ó ti wá láti wá jọ́sìn ní ilé Olúwa, sọ fún gbogbo ohun tí mo pàṣẹ fún ọ; má ṣaláìsọ gbogbo ọ̀rọ̀ náà.
3 Amabela: ? Dunu da nabimu amola ilia wadela: i hou yolesima: bela: ? Ilia da agoane hamosea, Na da Na asigi dawa: su afadenene, wadela: su Na ilia wadela: i hou hamobeba: le ilima iasimusa: ilegei, amo ilima hame iasimu.”
Bóyá gbogbo wọn máa gbọ́ ọ̀rọ̀ náà tí ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn yóò kúrò nínú ìwà búburú wọn. Èmi ó yí ọkàn padà, n kò sì ní fi ibi tí mo ti rò sí wọn ṣe wọ́n.
4 Hina Gode da nama, na da Ea sia: ilima alofele imunu sia: i, “Na, Hina Gode, da dilima Na sia: nabima: ne, amola Na olelesu fa: no bobogema: ne sia: i dagoi.
Sọ fún wọn wí pé, ‘Èyí ni ohun tí Olúwa wí: Tí ẹ kò bá fi etí sí ọ̀rọ̀ mi, tí ẹ kò sì gbọ́ òfin mi, ti mo gbé kalẹ̀ níwájú yín,
5 Amola Na hawa: hamosu dunu, amo da balofede dunu Na dilima asula ahoanana, amo ilia sia: nabima: ne sia: i. Be dilia da ilia sia: hamedafa nabi.
àti tí ẹ kò bá gbọ́ ọ̀rọ̀ àwọn ìránṣẹ́ mi, àwọn wòlíì tí mo rán sí i yín léraléra (ṣùgbọ́n ẹ̀yin kò gbọ́),
6 Dilia da mae sinidigili, hame nabasu hou bu hamonanea, Na da Debolo diasu amoga hou Na da Siailou amoga hamoi, defele hamomu. Amasea, osobo bagade fifi asi gala dunu huluane da Yelusaleme ea dioba: le, gagabusu aligima: ne ilegemu.”
nígbà náà ni èmi yóò ṣe ilé yìí bí Ṣilo, èmi yóò sì ṣe ìlú yìí ní ìfibú sí gbogbo orílẹ̀-èdè ayé.’”
7 Gobele salasu dunu amola balofede dunu amola dunu huluane da Na Debolo ganodini sia: i liligi huluane nabi.
Àwọn àlùfáà, àwọn wòlíì àti gbogbo ènìyàn ni ó gbọ́ ọ̀rọ̀ Jeremiah tí ó sọ ní ilé Olúwa.
8 Amola na da Hina Gode Ea adosi huluane sia: i dagolesiloba, ilia da na gagulaligili, bagade wele sia: i, amane, “Di da amo sia: sia: beba: le, ninia di medole legemu da defea.
Ṣùgbọ́n ní kété tí Jeremiah ti parí ọ̀rọ̀ rẹ̀ tí Olúwa pàṣẹ láti sọ; àwọn àlùfáà, àti gbogbo ènìyàn dìímú, wọ́n sì wí pé, “Kíkú ni ìwọ yóò kú!
9 Di da abuliba: le, Hina Gode Ea Dioba: le, amo Debolo da Siailou agoane ba: mu amola amo moilai wadela: lesi dagoi amola amo ganodini dunu afae hame esalebe ba: mu, amo abuliba: le sia: bela: ?” Amalalu, dunu huluane da nama guba: le sisiga: i.
Kí ló dé tí ìwọ ṣe sọ àsọtẹ́lẹ̀ ní orúkọ Olúwa pé, ilé yìí yóò dàbí Ṣilo, orílẹ̀-èdè yìí yóò sì di ahoro tí kì yóò ní olùgbé.” Gbogbo àwọn ènìyàn sì kójọpọ̀ pẹ̀lú Jeremiah nínú ilé Olúwa.
10 Yuda ouligisu dunu da amo hou hamobe nababeba: le, hina bagade diasu yolesili, Debolo diasuga hehenane, Logo Ga: su Gaheabolo gadenenewane lelu.
Nígbà tí àwọn aláṣẹ Juda gbọ́ nípa nǹkan wọ̀nyí, wọ́n lọ láti ààfin ọba sí ilé Olúwa, wọ́n sì mú ààyè wọn, wọ́n jókòó ní ẹnu-ọ̀nà tuntun ilé Olúwa.
11 Amalalu, gobele salasu amola balofede dunu da ouligisu dunu amola dunudafa ilima amane sia: i, “Amo dunu da ninia moilai bai bagade amoma wadela: lesimusa: sia: beba: le, ema fofada: nanu medole legemu da defea. Dilia da ea hou amo dilia gega nabi dagoi.”
Àwọn àlùfáà àti àwọn wòlíì sọ fún àwọn aláṣẹ àti gbogbo ènìyàn pé, “Arákùnrin yìí gbọdọ̀ gba ìdájọ́ ikú nítorí pé ó sọ àsọtẹ́lẹ̀ lórí ìlú yìí: bí ẹ̀yin ti fi etí yín gbọ́!”
12 Amalalu, na da amane sia: i, “Hina Gode Hisu da sia: amo na da Debolo amola moilaiga huluane alofele sia: ma: ne, asunasi.
Nígbà náà ni Jeremiah sọ fún gbogbo àwọn aláṣẹ àti gbogbo àwọn ènìyàn wí pé: “Olúwa rán mi láti sọ àsọtẹ́lẹ̀ ní ilé yìí àti ìlú yìí, gbogbo ohun tí ẹ ti gbọ́.
13 Dilia esalusu hou amola hamobe hou huluane afadenene, Hina Gode Ea sia: nabima. Amai galea, E da Ea asigi dawa: su afadenene, wadela: su amola se iasu amo E da dilima iasima: ne sia: i, amo dilima hame iasimu.
Nísinsin yìí, tún ọ̀nà rẹ ṣe àti ìṣe rẹ, kí ẹ sì gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa Ọlọ́run yín. Olúwa yóò yí ọkàn rẹ̀ padà, kò sì ní mú ohun gbogbo tí ó ti sọ jáde ní búburú ṣẹ lórí yín.
14 Be na! Na da dilia gasaga gagulaligi dagoi. Dilia da dilia asigi dawa: su amoga nama moloi hou hamoma.
Bí ó bá ṣe tèmi ni, èmi wà ní ọwọ́ yín, ẹ ṣe ohun tí ẹ̀yin bá rò pé ó dára, tí ó sì tọ́ lójú yín fún mi.
15 Be amo noga: le dawa: ma. Dilia da na medole legelalu, dilia da wadela: i hame hamoi dunu giadofale medole legei dagoi ba: mu. Bai Hina Gode Hisu da na dilima sisasu ima: ne asunasi dagoi.”
Ẹ mọ̀ dájú pé tí ẹ bá pa mí, ẹ ó mú ẹ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ wá sórí ara yín, sórí ìlú yìí àti àwọn olùgbé inú rẹ̀; nítorí pé nítòótọ́ ni Olúwa ti rán mi láti sọ ọ̀rọ̀ yìí fún un yín.”
16 Amalalu, ouligisu dunu amola dunudafa ilia da gobele salasu amola balofede dunu ilima amane sia: i, “Amo dunu da ninia Hina Gode Ea Dioba: le, ninima sia: i. E medole legemu da defea hame.”
Nígbà náà ni àwọn aláṣẹ àti gbogbo àwọn ènìyàn sọ fún àwọn àlùfáà àti àwọn wòlíì pé, “Ẹ má ṣe pa ọkùnrin yìí nítorí ó ti bá wa sọ̀rọ̀ ní orúkọ Olúwa àwọn ọmọ-ogun.”
17 Amalalu, asigilai dunu mogili da lelu, dunu huluane gilisi ilima amane sia: i,
Lára àwọn àgbàgbà ilẹ̀ náà sì sún síwájú, wọ́n sì sọ fún gbogbo àwọn ènìyàn náà wí pé,
18 “Hesigaia da Yuda hina bagade esaloba, balofede dunu Maiga (Moulesede moilai dunu) da dunu huluane ilima Hina Gode Bagadedafa Ea sia: agoane olelei, ‘Saione moilai da bugili nasu soge osobo gidinai dagoi agoane ba: mu. Yelusaleme da wadela: sea, mugului liligi lelegela heda: su agoane ba: mu, amola Debolo agolo da iwila agoane ba: mu.’
“Mika ti Moreṣeti sọ àsọtẹ́lẹ̀ ní ọjọ́ Hesekiah ọba Juda. Ó sọ fún gbogbo ènìyàn Juda pé, ‘Èyí ni ohun tí Olúwa wí: “‘A ó sì fa Sioni tu bí oko Jerusalẹmu yóò di òkìtì àlàpà àti òkè ilẹ̀ yìí gẹ́gẹ́ bí ibi gíga igbó.’
19 Hina bagade Hesigaia amola Yuda fi dunu da Maiga hame medole legei. Be Hesigaia da Hina Godema nodone hamosu, amola E da ema hahawane ba: ma: ne, nabasu hou hamosu. Amalalu, Hina Gode da Ea asigi dawa: su afadenene, wadela: su E da ilima iasima: ne sia: i, amo hame iasi. Be wali, ninisu da wadela: su bagadedafa ninima doaga: ma: ne, logo fodosa.”
Ǹjẹ́ Hesekiah ọba Juda tàbí ẹnikẹ́ni ní Juda pa á bí? Ǹjẹ́ Hesekiah kò bẹ̀rù Olúwa tí ó sì wá ojúrere rẹ̀? Ǹjẹ́ Olúwa kò ha a sì yí ìpinnu rẹ̀ padà, tí kò sì mú ibi tí ó ti sọtẹ́lẹ̀ yẹ̀ kúrò lórí wọn? Ibi ni a fẹ́ mú wá sórí ara wa yìí.”
20 (Eso enoga, dunu eno amo Iulaia [e da Siema: ia egefe amola ea moilai da Gilia: de Yilimi], e da Hina Gode Ea Dioba: le Yelusaleme amola Yuda fi da wadela: su ba: mu amo ba: la: lusu.
(Bákan náà Uriah ọmọ Ṣemaiah láti Kiriati-Jearimu jẹ́ ọkùnrin mìíràn tí ó sọ àsọtẹ́lẹ̀ kan náà ní orúkọ Olúwa. Ó sọ àsọtẹ́lẹ̀ kan náà sí ìlú náà àti ilẹ̀ yín bí Jeremiah ti ṣe.
21 Yuda hina bagade Yihoiagimi amola ea dadi gagui dunu amola eagene ouligisu dunu da Iulaia ea sia: i nababeba: le, e medole legemusa: ilegei. Be Iulaia da ilia ilegei nababeba: le, Idibidi sogega hobea: i.
Nígbà tí ọba Jehoiakimu àti gbogbo àwọn aláṣẹ gbọ́ gbogbo ọ̀rọ̀ rẹ̀, ọba ń wá láti pa á: ṣùgbọ́n Uriah gbọ́ èyí, ẹ̀rù bà á, ó sì sálọ sí Ejibiti.
22 Be hina bagade Yihoiagimi da dunu ea dio amo Elena: ida: ne (A: gabo egefe) amola dunu eno Iulaia gagulaligimusa: Idibidi sogega asunasi.
Ọba Jehoiakimu rán Elnatani ọmọ Akbori lọ sí Ejibiti pẹ̀lú àwọn ọkùnrin mìíràn.
23 Ilia da Iulaia hina bagade Yihoiagimima bu oule misi. Yehoiagimi sia: beba: le, ilia Iulaia medole legele, ea da: i hodo hame gagui dunu ilia uli dogosu sogebi amoga ha: digi).
Wọ́n sì mú Uriah láti Ejibiti lọ sí ọ̀dọ̀ ọba Jehoiakimu; ẹni tí ó fi idà pa, ó sì sọ òkú rẹ̀ sí inú isà òkú àwọn ènìyàn lásán.)
24 Be Ahaiga: me (Sia: ifa: ne egefe) da na fuligala: beba: le, ilia da dunu eno na medole legemusa: ilima hame iasi.
Ahikamu ọmọ Ṣafani ń bẹ pẹ̀lú Jeremiah, wọn kò sì fi í lé àwọn ènìyàn lọ́wọ́ láti pa á.

< Yelemaia 26 >