< Yelemaia 23 >

1 Hina Gode da ouligisu dunu amo da Ea fi dunu wadela: lesisa amola afagogobe, ilima ougi bagadedafa fofada: mu.
“Ègbé ni fún àwọn olùṣọ́-àgùntàn tí ń tú agbo ẹran mi ká tí ó sì ń pa wọ́n run!” ni Olúwa wí.
2 Amo ouligisu dunu da Gode Ea fi dunu noga: le ouligimu da defea galu. Be Hina Gode, Isala: ili ilia Gode, da ilima amane sia: sa, “Dilia da Na fi dunu noga: le hame ouligi. Dilia da amo dunu afagogole, sefasi dagoi. Amaiba: le, dilia da amo wadela: i hou hamobeba: le, Na da dilima se imunu.
Nítorí náà, èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli sọ ní ti àwọn olùṣọ́-àgùntàn tí ń darí àwọn ènìyàn mi: “Nítorí tí ẹ̀yin tú agbo ẹran mi ká, tí ẹ lé wọn dànù tí ẹ̀yin kò sì bẹ̀ wọ́n wò. Èmi yóò jẹ yín ní yà nítorí nǹkan búburú tí ẹ ti ṣe,” ni Olúwa wí.
3 Na da Na fi dunu eno fifi asi gala ganodini esaloma: ne afagogoi. Be Na da amo fi dunu hame bogoi esalebe, amo bu gilisili, ilia sogedafa amoga bu oule misunu. Ilia mano bagohame da lalelegemu, amola ilia idi da bagade heda: mu.
“Èmi Olúwa tìkára mi yóò kó ìyókù agbo ẹran mi jọ láti inú gbogbo orílẹ̀-èdè tí mo ti lé wọn, Èmi yóò mú wọn padà sínú pápá oko wọn, níbẹ̀ ni wọn ó ti bí sí i, tí wọn ó sì pọ̀ sí i.
4 Na da ouligisu dunu ili noga: le ouligima: ne, amo ilegemu. Na fi dunu da beda: su bu hame ba: mu, amola Na da ilima se iasu eno hamedafa imunu. Na, Hina Gode, da sia: i dagoi.”
Èmi ó wá olùṣọ́-àgùntàn fún wọn, tí yóò darí wọn, wọn kì yóò bẹ̀rù tàbí dààmú, bẹ́ẹ̀ ni ọ̀kan kì yóò sọnù,” ni Olúwa wí.
5 Hina Gode da amane sia: sa, “Eso da misunu amoga Na da Hina Bagade hamoma: ne, Da: ibidi ea moloidafa egaga fi ifa Amoda agoane, Dunu afae amo ilegemu. Amo Hina Bagade da dawa: digili, soge huluane ganodini moloidafawane ouligimu.
“Ọjọ́ ń bọ̀,” ni Olúwa wí, “tí Èmi yóò gbé ẹ̀ka òdodo dìde fún Dafidi, ọba tí yóò lo ìjọba pẹ̀lú ọgbọ́n tí yóò sì ṣe òdodo àti ohun tí ó yẹ lórí ilẹ̀ náà.
6 E da Hina Bagade hamoi dagoiba: le, Yuda dunu da olofoiwane gaga: i dagoi ba: mu. Ilia da Ema dio asulimu, amo ‘Hina Gode, ninia Moloidafa Gaga: su.’”
Ní ọjọ́ rẹ̀ ni a ó gba Juda là, Israẹli yóò sì máa gbé ní aláìléwu. Èyí ni orúkọ tí a ó fi máa pè é: Olúwa Òdodo wa.
7 Hina Gode da amane sia: sa, “Eso da misunu amoga ilia da Na, Fifi Ahoanusu Gode amo da ili Idibidi sogega fisili masa: ne gadili oule misi, amoga Na Dioba: le ilia sia: dafawane hame ilegemu.
Nítorí náà, ọjọ́ ń bọ̀,” ni Olúwa wí, “tí ènìyàn kì yóò tún wí pé, ‘Dájúdájú Olúwa wà láààyè tí ó mú àwọn ọmọ Israẹli jáde kúrò ní ilẹ̀ Ejibiti.’
8 Be amo bu mae dawa: le, ilia da Na da Fifi Ahoanusu Gode amo da gagoe (north) soge amola soge eno amoga Na da musa: ili afagogoi, amoga Na da ilia sogedafa amoga bu oule misi, amo dawa: le ilia da Na Dioba: le sia: dafawane ilegemu. Amasea, ilia da ilia sogedafa amo ganodini esalumu.”
Ṣùgbọ́n wọn yóò máa wí pé, ‘Dájúdájú Olúwa ń bẹ tí ó mú irú-ọmọ ilé Israẹli wá láti ilẹ̀ àríwá àti láti àwọn ilẹ̀ ibi tí mo tí lé wọn lọ,’ wọn ó sì gbé inú ilẹ̀ wọn.”
9 Na dogo da goudai dagoi, amola na da bagadewane yagugusa. Bai Hina Gode da Ea hadigi sia: sia: i dagoi. Na da dunu amo da waini hano bagade maiba: le feloasu, agoaiwane ba: sa.
Nípa ti àwọn wòlíì èké. Ọkàn mi ti bàjẹ́ nínú mi, gbogbo egungun mi ni ó wárìrì. Èmi dàbí ọ̀mùtí ènìyàn, bí ọkùnrin tí ọtí wáìnì ń pa; nítorí Olúwa àti àwọn ọ̀rọ̀ mímọ́ rẹ̀.
10 Dunu huluane amo soge ganodini esala da Hina Gode yolesi dagoi. Ilia da wadela: i hou hamonana, amola gasa fili wadela: le hamosa. Hina Gode da soge amoga gagabui aligima: ne ilegeiba: le, soge da dinana agoane gala, amola bulamagau amola sibi ilia soge da hafoga: i dagoi.
Ilẹ̀ náà kún fún panṣágà ènìyàn; nítorí ègún, ilẹ̀ náà gbẹ, àwọn koríko orí aṣálẹ̀ ilẹ̀ náà rọ. Àwọn wòlíì tẹ̀lé ọ̀nà búburú, wọ́n sì ń lo agbára wọn lọ́nà àìtọ́.
11 Hina Gode da amane sia: sa, “Balofede dunu amola gobele salasu dunu da Gode Ea hou hame dawa: Na ba: loba ilia da Debolo diasu ganodini wadela: le hamonanu.
“Wòlíì àti àlùfáà kò gbé ìgbé ayé ìwà-bí-Ọlọ́run; kódà nínú tẹmpili mi ni mo rí ìwà búburú wọn,” ni Olúwa wí.
12 Ilia logo da enemei amola gasi ganodini agoane ba: mu. Na da hamobeba: le, ilia da sadenane dafamu. Na da ilima wadela: su iasimu. Ilima se imunu eso da doaga: mu. Na, Hina Gode, da sia: i dagoi.
“Nítorí náà, ọ̀nà wọn yóò di yíyọ́, a ó lé wọn jáde sínú òkùnkùn; níbẹ̀ ni wọn yóò ṣubú. Èmi yóò mú ìdààmú wá sórí wọn, ní ọdún tí a jẹ wọ́n ní ìyà,” ni Olúwa wí.
13 Na da Samelia balofede dunu ilia wadela: i hou amo ba: i dagoi. Ilia da Ba: iele ea dioba: le sia: i dagoi. Amola ilia da Na fi ilima bobogema: ne, wadela: i logo olelei dagoi.
“Láàrín àwọn wòlíì Samaria, Èmi rí ohun tí ń lé ni sá. Wọ́n sọ àsọtẹ́lẹ̀ lórúkọ Baali wọ́n sì mú Israẹli ènìyàn mi ṣìnà.
14 Be Yelusaleme bagade balofede dunu da amo baligimusa: wadela: i hou hamoi, amo Na da ba: i. Ilia da inia uda adole lasu amola ogogosu hamoi dagoi. Ilia da dunu eno wadela: le hamoma: ne bagade fidibiba: le, dunu huluane da wadela: le hamosu fisimusa: hame dawa: i. Na ba: loba, ilia huluane da Sodame amola Goumola dunu defele wadela: le hamonana.
Àti láàrín àwọn wòlíì Jerusalẹmu, èmi ti rí ohun búburú. Wọ́n ṣe panṣágà, wọ́n sì ń ṣèké. Wọ́n fún àwọn olùṣe búburú ní agbára, tó bẹ́ẹ̀ tí kò sí ẹnìkan tí ó yípadà kúrò nínú ìwà búburú rẹ̀. Gbogbo wọn dàbí Sodomu níwájú mi, àti àwọn ènìyàn olùgbé rẹ̀ bí Gomorra.”
15 Amaiba: le, Na, Hina Gode Bagadedafa da Yelusaleme balofede dunu ilima amane hamomu. Na da gamogai bugi liligi ili moma: ne ilima imunu. Amola Na da ilima medole legesu hano ilia moma: ne imunu. Bai ilia Godema hame fa: no bobogesu hou, amo Na soge huluane ganodini olelei dagoi.”
Nítorí náà, báyìí ni Olúwa Ọlọ́run Alágbára wí ní ti àwọn wòlíì: “Èmi yóò mú wọn jẹ oúnjẹ kíkorò, wọn yóò mu omi májèlé nítorí láti ọ̀dọ̀ àwọn wòlíì Jerusalẹmu ni àìwà-bí-Ọlọ́run ti tàn ká gbogbo ilẹ̀.”
16 Hina Gode Bagadedafa da Yelusaleme fi dunu ilima amane sia: i, “Balofede dunu ilia sia: mae nabima. Ilia da dilima hahawane hou da doaga: mu, ogogole olelesa. Ilia da ilisu asigi dawa: su ganodini dawa: su liligi amo fawane olelesa, amola Na sia: i liligi hamedafa olelesa.
Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí: “Ẹ má ṣe fi etí sí àsọtẹ́lẹ̀ tí àwọn wòlíì èké ń sọ fún un yín. Wọ́n ń kún inú ọkàn yín pẹ̀lú ìrètí asán. Wọ́n ń sọ ìran láti ọkàn ara wọn, kì í ṣe láti ẹnu Olúwa.
17 Ilia da dunu (amo da Na sia: i liligi nabimu higa: i dunu) ilima ilia da hahawane fawane ba: mu, amo sia: daha. Amola ga: nasi hamoi gasa fi dunu, ilima ilia da wadela: su hame ba: mu olelelala.”
Wọ́n ń sọ fún àwọn tí ó ń gàn mí pé, ‘Olúwa ti wí pé, ẹ̀yin ó ní àlàáfíà.’ Wọ́n sì wí fún gbogbo àwọn tí ó rìn nípa agídí ọkàn rẹ̀ pé, ‘Kò sí ìpalára kan tí yóò ṣẹlẹ̀ sí yín.’
18 Na (Yelemaia) da amane sia: i, “Amo balofede dunu afae da Hina Gode Ea wamolegei asigi dawa: su amo hamedafa dawa: i galu. Afae da Ea sia: amola Ea sia: i adole iasi amo hame nabi amola hame dawa: digi.
Ṣùgbọ́n èwo nínú wọn ni ó dúró nínú ìgbìmọ̀ Olúwa láti rí i tàbí gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ̀? Ta ni ó gbọ́ tí ó sì fetí sí ọ̀rọ̀ náà?
19 Hina Gode Ea ougi da gibula bobodole isu mabe agoane misini, amola gasa bagade isu amo da wadela: i hamosu dunu ilia dialuma da: iya masunu.
Wò ó, afẹ́fẹ́ Olúwa yóò tú jáde pẹ̀lú ìbínú à fẹ́ yíká ìjì yóò fẹ́ sí orí àwọn olùṣe búburú.
20 Amo isu da mae dagole, maneawane, Hina Gode Ea hanai huluane hamoi dagoiba: le fawane yolesimu. Hobeadafa, Hina Gode Ea fi dunu da amo hou dawa: digimu.”
Ìbínú Olúwa kì yóò yẹ̀ títí tí yóò sì fi mú èrò rẹ̀ ṣẹ, ní àìpẹ́ ọjọ́, yóò yé e yín yékéyéké.
21 Hina Gode da amane sia: i, “Na da amo balofede dunu hame asunasi. Be ilia da udigili asi. Na da ilima sia: adosima: ne hame sia: i, be ilia da Na Dioba: le udigili sia: i.
Èmi kò rán àwọn wòlíì wọ̀nyí síbẹ̀ wọ́n lọ pẹ̀lú ọ̀rọ̀ wọn. Èmi kò tilẹ̀ bá wọn sọ̀rọ̀, síbẹ̀ wọ́n sọ àsọtẹ́lẹ̀.
22 Ilia da Na wamolegei asigi dawa: su dawa: i ganiaba, ilia da Na sia: Na fi dunuma alofele imunu dawa: la: loba, amola Na fi dunu ilia wadela: i esalusu amola hawa: hamosu fisima: ne hamona: noba.
Ṣùgbọ́n ì bà ṣe pé wọn dúró nínú ìgbìmọ̀ mi, wọn ìbá ti kéde ọ̀rọ̀ mi fún àwọn ènìyàn mi. Wọn ìbá ti wàásù ọ̀rọ̀ mi fun àwọn ènìyàn wọn ìbá ti yípadà kúrò nínú ọ̀nà àti ìṣe búburú wọn.
23 Na da Gode amo da sogebi huluanedafa amo ganodini esalebe dawa: Na da sogebi afadafa fawane amo ganodini hame esala.
“Ǹjẹ́ Ọlọ́run tòsí nìkan ni Èmi bí?” ni Olúwa wí, “kì í sì í ṣe Ọlọ́run ọ̀nà jíjìn.
24 Dunu huluane da Na mae ba: ma: ne, wamoaligimu hamedei ba: sa. Na da mu amola osobo bagadega sogebi huluanedafa amo ganodini esala.
Ǹjẹ́ ẹnikẹ́ni lè sá pamọ́ sí ibi kọ́lọ́fín kan, kí èmi má ba a rí?” ni Olúwa wí. “Ǹjẹ́ èmi kò ha a kún ọ̀run àti ayé bí?” ni Olúwa wí.
25 Amo balofede ilia sia: Na dawa: Ilia da Na Dioba: le, ogogole sia: sa, amola Na da ilia simasia ba: su amo ganodini ilima sia: sa, amo ogogole olelesa. Bai Na da ilima hamedafa sia: sa.
“Mo ti gbọ́ gbogbo ohun tí àwọn wòlíì èké tí ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ ní orúkọ mi ń sọ. Wọ́n sọ wí pé, ‘Mo lá àlá! Mo lá àlá!’
26 Amo balofede dunu da Na fi dunuma ogogosu sia: ilisu hamosu olelesa, amo da habodane yolesima: bela: ?
Títí di ìgbà wo ni èyí yóò fi máa tẹ̀síwájú ni ọkàn àwọn wòlíì èké wọ̀nyí tí wọ́n ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ ìtànjẹ ọkàn wọn?
27 Ilia da agoane dawa: Ilia da ilia simasia ba: i liligi amo Na fi dunu ilima olelesea, Na fi dunu da ilia edalia hou defele, Na gogolele, Ba: ielema fa: no bobogemu, agoane dawa:
Wọ́n rò wí pé àlá tí wọ́n ń sọ fún ara wọn yóò mú kí àwọn ènìyàn mi gbàgbé orúkọ mi, gẹ́gẹ́ bí àwọn baba wọn ṣe gbàgbé orúkọ mi nípa sí sin òrìṣà Baali.
28 Balofede da simasia ba: sea, amo da simasia ba: su fawane e da sia: mu da defea. Be balofede dunu da Na sia: dafa nabasea, e da mae ogogole, moloiwane amo sia: alofele imunu da defea. Na sia: da widi ha: i manu noga: iwane gala. Be bioi gisi da noga: i hame.
Jẹ́ kí wòlíì tí ó bá lá àlá sọ àlá rẹ̀, ṣùgbọ́n jẹ́ kí ẹni tí ó ní ọ̀rọ̀ mí sọ ọ́ ní òtítọ́. Kí ni koríko gbígbẹ ní í ṣe nínú ọkà?” ni Olúwa wí.
29 Na sia: da lalu agoane. Amola Na sia: da ‘ha: ma’ (hammer), amo da igi fofonobomusa: goudasa, agoai gala.
“Ọ̀rọ̀ mi kò ha a dàbí iná?” ni Olúwa wí, “àti bí òòlù irin tí ń fọ́ àpáta túútúú?
30 Balofede mogili ilia da balofede eno ea udigili sia: dalebe amo lale, eno dunuma olelesea, amo udigili sia: da Na sia: dafa ilia ogogole olelesa. Na da amo ogogosu balofede dunu higasa.
“Nítorí náà, èmi lòdì sí àwọn wòlíì ni,” Olúwa wí, “Tí ń jí ọ̀rọ̀ tí ó yẹ kí ó ti ọ̀dọ̀ mi wá lò lọ́dọ̀ ara wọn.
31 Amola balofede eno da hi sia: olelesea, amo da Na sia: dafa ogogole sia: sa. Na da amo balofede amola higasa.
Bẹ́ẹ̀,” ni Olúwa wí, “Èmi lòdì sí àwọn wòlíì tí wọ́n lo ahọ́n wọn káàkiri, síbẹ̀ tí wọ́n ń sọ wí pé, ‘Olúwa wí.’
32 Nabima! Na, Hina Gode, da amane sia: sa! Na da balofede dunu amo da ilia ogogosu simasia ba: i liligi olelesa, amo higasa. Ilia da amo simasia ba: i olelebeba: le, amola ogogole amola hidale sia: beba: le, Na fi dunu da logo giadofale, dafasa. Na da ili hame asunasi amola olelela masa: ne hame sia: i. Amola ilia da Na fi dunu hamedafa fidisa. Na, Hina Gode, da sia: i dagoi.”
Nítòótọ́, mo lòdì sí àwọn tí ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa àlá èké,” ni Olúwa wí. “Wọ́n ń sọ bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì ń mú àwọn ènìyàn mi ṣìnà nípa onírúurú èké wọn, síbẹ̀ èmi kò rán wọn tàbí yàn wọ́n. Wọn kò sì ran àwọn ènìyàn wọ̀nyí lọ́wọ́ bí ó ti wù kí ó kéré mọ,” ni Olúwa wí.
33 Hina Gode da nama amane sia: i, “Yelemaia! Na fi dunu afae o balofede dunu o gobele salasu dunu, amo da dima amane adole ba: sea, ‘Hina Gode Ea sia: i da adi sia: bela: ?’ di ema bu amane adole ima, ‘Di da Hina Godema da: i dioi liligi bagade. E da di fadegamu!’
“Nígbà tí àwọn ènìyàn wọ̀nyí, tàbí wòlíì tàbí àlùfáà bá bi ọ́ léèrè wí pé, ‘Kí ni ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ Olúwa?’ Sọ fún wọn wí pé, ‘Ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ wo? Èmi yóò pa yín tì ni Olúwa wí.’
34 Be Na fi dunu afae, o balofede o gobele salasu da sia: agoane, ‘Hina Gode Ea sia: da agoane’ amo fawane sia: sea, Na da e amola ea sosogo fi ilima se imunu.
Bí wòlíì tàbí àlùfáà tàbí ẹnikẹ́ni bá sì gbà wí pé, ‘Èyí ni ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ Olúwa.’ Èmi yóò fi ìyà jẹ ọkùnrin náà àti gbogbo agbo ilé rẹ̀.
35 Be amo mae dawa: le, dunu huluane afae afae da ea dogolegei amola na: iyado ilima amane adole ba: mu da defea, ‘Hina Gode da adi adole ibala: ? E da adi sia: bela: ?’ Bai ilia da Na sia: hame dawa:
Èyí ni ohun tí ẹnìkọ̀ọ̀kan yín ń sọ fún ọ̀rẹ́ àti ará ilé rẹ̀: ‘Kí ni ìdáhùn Olúwa?’ Tàbí ‘Kí ni ohun tí Olúwa sọ?’
36 Be dilia bu ‘Amo da Hina Gode Ea sia:’ bu sia: mu da sema bagade. Bai dilisu sia: da Gode Esala, Hina Gode Bagadedafa, amo Ea sia: dilia da giadofale sia: sea, dilia da Na sia: dafa bagadewane wadela: sa.
Ṣùgbọ́n ẹ̀yin kò gbọdọ̀ dárúkọ ọ̀rọ̀ ‘ìjìnlẹ̀ Olúwa’ mọ́, nítorí pé ọ̀rọ̀ oníkálùkù ènìyàn di ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ rẹ̀. Nítorí náà, ẹ̀yin ń yí ọ̀rọ̀ Ọlọ́run alààyè, Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run wa padà.
37 Yelemaia! Di balofede dunu ilima amane adole ba: ma, ‘Hina Gode da dima adi sia: bela: ? Dima adi adole ibala: ?’
Èyí ni ohun tí ẹ̀yin ń sọ fún wòlíì: ‘Kí ni ìdáhùn Olúwa sí ọ́?’ Tàbí ‘Kí ni ohun tí Olúwa bá ọ sọ?’
38 Amasea, amo balofede dunu ilia da Na sia: mae nabawane, ‘Hina Gode da amane sia: sa.’ amane sia: sea, ilima amane olelema,
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹ̀yin ń sọ wí pé, ‘Èyí ni ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ Olúwa,’ èyí ni ohun tí Olúwa sọ, Ẹ̀yin ń lo ọ̀rọ̀ yìí, ‘Èyí ni ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ Olúwa,’ bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé mo sọ fún un yín láti má ṣe lò ó mọ́, ‘Èyí ni ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ Olúwa.’
39 ‘Na, Hina Gode, da dili gaguia gadole, dili amola dilia moilai bai bagade (amo Na da dili amola dilia aowalalia ilima i) amo fadegale fasimu.
Nítorí náà, Èmi yóò gbàgbé yín, bẹ́ẹ̀ ni n ó lé e yín kúrò níwájú mi pẹ̀lú àwọn ìlú tí mo fi fún un yín àti àwọn baba yín.
40 Na da eso huluane dialoma: ne, gogosiasu dilima imunu. Dunu huluane da amo gogosiasu hamedafa gogolemu.’”
Èmi yóò sì mú ìtìjú ayérayé wá sí orí yín, ìtìjú tí kò ní ní ìgbàgbé.”

< Yelemaia 23 >