< Yelemaia 2 >

1 Hina Gode da nama amane sia: i,
Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ̀ mí wá wí pé:
2 “Amo sia: Yelusaleme esalebe dunu huluane ilima olelema, ‘Dia manohadi eso amoga Nama mae fisili noga: le fa: no bobogelalu. Na da fedege agoane di uda lai agoane laloba, di da Nama bagade asigisu. Dia da wadela: i hafoga: i soge, soge amo da ha: i manu hame bugi soge, amo ganodini Nama noga: le fa: no bobogesu. Amo hou Na bu dawa: lala.
“Lọ kí o sì kéde sí etí Jerusalẹmu pé: “Báyìí ni Olúwa wí, “‘Èmi rántí ìṣeun ìgbà èwe rẹ, ìfẹ́ ìgbéyàwó rẹ àti nígbà tí ìwọ tẹ̀lé mi nínú ijù, nínú ìyàngbẹ ilẹ̀.
3 Isala: ili fi! Dili da Na: fawane galu. Dilia da Na dogolegei sema fi galu. Nowa dunu da dilima se iasu, amo Na da wadela: su amola se iasu ilima iasi. Na, Hina Gode, da sia: i dagoi.” Isala: ili Fi ilia Aowalalia ilia Wadela: i Hou
Israẹli jẹ́ mímọ́ sí Olúwa, àkọ́kọ́ èso ìkórè rẹ̀, gbogbo ẹnikẹ́ni tí ó jẹ run ni a ó dá lẹ́bi, ibi yóò sì wá sí orí wọn,’” bẹ́ẹ̀ ni Olúwa wí.
4 Dilia! Ya: igobe egaga fi dunu! Isala: ili fi dilia! Hina Gode Ea sia: nabima!
Gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa, ẹ̀yin ìdílé Jakọbu àti gbogbo ẹ̀yin ará ilé Israẹli.
5 Hina Gode da amane sia: sa, “Dilia aowalalia da Nama adi wadela: i hou diwane udidibala: ? Ilia da abuliba: le Nama baligi fa: bela? Ilia da hamedei loboga hamoi ‘gode’ agoaila ilima nodone sia: ne gadobeba: le, bu ilia hou amola da hamedei ba: i dagoi.
Báyìí ni Olúwa wí: “Irú àìṣedéédéé wo ni baba yín rí lọ́wọ́ mi, tí wọ́n fi jìnnà sí mi? Wọ́n tẹ̀lé àwọn òrìṣà asán, àwọn fúnra wọn sì di asán.
6 Na da ili gaga: le, Idibidi sogega fisili masa: ne, ga asunasi! Ilia da hahawane masa: ne, Na da ili bisili, wadela: i hafoga: i soge (amo ganodini da gibu hame, gasi dunasi bagade amola dunu hamedafa esala) amo baligima: ne oule asi. Be ilia da Nama hame asigi galu.
Wọn kò béèrè, ‘Níbo ni Olúwa wà, tí ó mú wa jáde láti ilẹ̀ Ejibiti wá, tí ó mú wa la aginjù já, tí ó mú wa la àárín pẹ̀tẹ́lẹ̀ àti ihò, ìyàngbẹ ilẹ̀ àti òkùnkùn biribiri, ilẹ̀ ibi tí ẹnikẹ́ni kò là kọjá, tí ẹnikẹ́ni kò sì tẹ̀dó sí?’
7 Na da ili nasegagi soge noga: idafa, ilia da amo ea ha: i manu amola liligi noga: idafa hahawane lama: ne, amoma oule misi. Be amo mae dawa: le, ilia da Na soge wadela: lesi. Ilia da soge Na ilima i, amo wadela: lesi.
Èmi mú yín wá sí ilẹ̀ ọlọ́ràá láti máa jẹ èso ibẹ̀ àti ọrọ̀ rẹ̀, ṣùgbọ́n ẹ̀yin wọ inú rẹ̀, ẹ sì bà á jẹ́, ẹ sì sọ ogún mi di ohun ìríra.
8 Ilia gobele salasu dunu da “Hina Gode da habila: ?” hame adole ba: i. Na gobele salasu dunu, ilia da Na hamedafa dawa: i. Na fi ouligisu dunu da Nama odoga: i dagoi. Balofede dunu da Ba: iele ea dioba: le ilegele sia: i, amola hamedei loboga hamoi ‘gode’ agoaila ilima nodone sia: ne gadoi.
Àwọn àlùfáà kò béèrè wí pé, ‘Níbo ni Olúwa wà?’ Àwọn tí ń ṣiṣẹ́ pẹ̀lú òfin kò si mọ̀ mí, àwọn olùṣọ́ sì ṣẹ̀ sí mi. Àwọn wòlíì sì ń sọtẹ́lẹ̀ nípa òrìṣà Baali, wọ́n sì ń tẹ̀lé àwọn òrìṣà asán.
9 Amaiba: le, Na, Hina Gode, da Na fi ilima bu fofada: mu. Na da iligaga fi ilima fofada: mu.
“Nítorí náà, mo fi ẹ̀sùn kàn yín lẹ́ẹ̀kan sí i,” ni Olúwa wí. “Èmi ó sì fi ẹ̀sùn kan àwọn ọmọ ọwọ́ rẹ.
10 Guma: dini Saibalase oga amoga masa! Amola dunu eno gusudili Gida sogega asunasima. Amasea, noga: le ba: ma! Amo hou defele da musa: hamedafa ba: i.
Rékọjá lọ sí erékùṣù àwọn ara Kittimu, kí ẹ sì wò ó, ránṣẹ́ lọ sí ìlú Kedari, kí ẹ sì kíyèsi gidigidi; kí ẹ wò bí irú nǹkan báyìí bá ń bẹ níbẹ̀?
11 Fifi asi gala eno da ilia ogogosu ‘gode’ hame afadenesu. Be Na fi da Na fisili, eno ogogosu ‘gode’ liligi lai. Na da ilia Godedafa amola Na da ili fidibiba: le, eno fifi asi gala da ilima nodoi. Be ilia da Na fisili, ogogosu ‘gode’ amo da ili fidimusa: hame dawa: , ilima fa: no bobogei.
Orílẹ̀-èdè kan ha á pa ọlọ́run rẹ̀ dà? (Síbẹ̀, wọ́n kì í ṣe iṣẹ́ ọlọ́run.) Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn mi ti pààrọ̀ Ọlọ́run ògo wọn fún àwọn ère tí kò níyì.
12 Amaiba: le, Na da mu amoma amane sia: sa ‘Fofogadigima! Dia beda: iba: le amola fofogadigiba: le, yaguguma.
Àwọn ènìyàn mi ti dẹ́ṣẹ̀ méjì kí ẹ sì wárìrì pẹ̀lú ìbẹ̀rù ńlá,” ni Olúwa wí.
13 Bai Na fi dunu da wadela: i hou aduna hamoi dagoi. Na da gaheabolo hano bubuga: su defele gala. Be ilia da Na hihini, Nama baligi fa: i. Amola ilia da igi magufu amoga hano si dogoi. Be amo hano si da goudaiba: le, hano da amo ganodini dialumu da hamedei ba: sa.”
“Àwọn ènìyàn mi ti dẹ́ṣẹ̀ méjì, wọ́n ti kọ̀ mí sílẹ̀, Èmi orísun omi ìyè, wọ́n sì ti ṣe àmù, àmù fífọ́ tí kò lè gba omi dúró.
14 Isala: ili fi da udigili hawa: hamosu fi hame. Ilia da udigili hawa: hamosu hamoma: ne, hame lalelegei. Amaiba: le, abuliba: le ilia ha lai dunu da ili awele gugunufisala: ?
Israẹli ha á jẹ́ ọmọ ọ̀dọ̀ ẹrú nípa ìbí? Kí ló ha a dé tí ó fi di ìkógun?
15 Ilia da Isala: ili fi ilima laione wa: me defele husa. Isala: ili ea ha lai da Isala: ili soge wadela: lesili, hafoga: i dunu hame esalebe soge amo defele hamoi dagoi. Isala: ili moilai huluane da wadela: lesi dagoi dialebe, amola amo ganodini, dunu da hame esalebe.
Àwọn kìnnìún ké ramúramù; wọ́n sì ń bú mọ́ wọn. Wọ́n ti fi ilẹ̀ rẹ̀ ṣòfò; ìlú rẹ̀ ti di jíjóná, ó sì ti di ìkọ̀sílẹ̀.
16 Dafawane! Memefisi dunu amola Dabinisi dunu da Isala: ili ea dialuma goudai dagoi.
Bákan náà, àwọn ọkùnrin Memfisi àti Tafanesi wọ́n ti fa adé orí rẹ yọ.
17 Isala: ili! Disu da amo se nabasu hamoi dagoi. Na da dia Hina Godedafa amola Na da di logoga hahawane oule ahoanebe ba: i. Be di da Na yolesi dagoi.
Ẹ̀yin kò ha a ti fa èyí sórí ara yín nípa kíkọ Olúwa Ọlọ́run sílẹ̀ nígbà tí ó tọ́ ọ lójú ọ̀nà?
18 Di da Idibidi sogega asili, Naile Hano amoga nasea, adi bidi ba: ma: bela: ? O Asilia sogega asili, Iufala: idisi Hano amoga nasea, adi bidi ba: ma: bela: ?
Kí ló dé tí o ṣe wá lọ Ejibiti láti lọ mu omi ní Ṣihori? Kí ló dé tí o sì fi lọ sí Asiria láti lọ mú omi ni odò Eufurate náà?
19 Di da Nama baligi fa: beba: le, wadela: i bagade hamoi dagoi. Amo hou da fedege agoane dima fofada: ne, se imunu. Dia da dawa: mu. Na da dia Hina Gode, amola di da Na fisibiba: le, wadela: i bagade hamoi. Na, Ouligisudafa Hina Gode Bagadedafa da sia: i dagoi.”
Iṣẹ́ búburú yín yóò fìyà jẹ yín ìpadàsẹ́yìn rẹ yóò sì bá ọ wí mọ̀ kí o sì rí i wí pé ibi àti ohun búburú yóò sì jẹ́ tìrẹ nígbà tí o ti kọ Olúwa Ọlọ́run sílẹ̀, ẹ kò sì ní ìbẹ̀rù fún mi,” ni Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
20 Ouligisudafa Hina Gode da amane sia: sa, “Isala: ili! Di da musa: hemonega Na Hinadafa Hou higasu. Di da Na sia: nabimu higasu, amola Nama nodone sia: ne gadomu higasu. Be dia da goumi huluane amo da: iya amola golofoyei ifa huluane amo hagudu, dia da ogogosu wadela: i uda lasu hou ‘gode’ ilima nodone sia: ne gadosu.
“Nígbà àtijọ́, o ti fọ́ àjàgà rẹ sọnù, ìwọ sì já ìdè rẹ; ìwọ wí pé, ‘Èmi kì yóò sìn ọ́!’ Lóòtítọ́, lórí gbogbo òkè gíga ni àti lábẹ́ igi tí ó tànkálẹ̀ ni ìwọ dùbúlẹ̀ sí gẹ́gẹ́ bí panṣágà.
21 Na da fedege agoane di waini efe hawa: ida: iwane agoane bugi. Be di da wadela: le heda: le, wali hamedei dasai waini efe agoane ba: sa.
Èmi ti gbìn ọ́ gẹ́gẹ́ bí àjàrà ọ̀tọ̀, gẹ́gẹ́ bí ìṣúra ọlọ́lá. Báwo wá ni ìwọ ṣe yípadà sí mi di àjàrà búburú àti aláìmọ́?
22 Di da nigima: agoane ba: sa. Amola di da gasa bagade safo amoga dia nigima: doga: i ganiaba, Na da dia nigima: amaiwane dialebe ba: la: loba.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé o wẹ ara rẹ pẹ̀lú sódà tí o sì lo ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọṣẹ síbẹ̀síbẹ̀ èérí ni ẹ̀ṣẹ̀ rẹ níwájú,” ni Olúwa Olódùmarè wí.
23 Dia da dia hou hame wadela: lesi amola Ba: ielema hame nodone sia: ne gadosu sia: sa. Be amo da ogogosa. Ba: ma! Di da fago ganodini, wadela: i hou bagade hamosu. Di da sigua ga: mele aseme amo da hafoga: i sogega gawali hogomusa: hehenasu agoane gala. (Gode da fedege agoane, Isala: ili fi dunu huluane da dunu afae agoane sia: sa.)
“Báwo ni ìwọ ṣe wí pé, ‘Èmi kò ṣe aláìmọ́, Èmi kò sá à tẹ̀lé àwọn Baali’? Wo bí o ṣe hùwà ní àfonífojì; wo ohun tí o ṣe. Ìwọ jẹ́ abo ìbákasẹ tí ń sá síyìn-ín sọ́hùn-ún.
24 E da gawali hanaiba: le, nowa da e ouligima: bela: ? Gawali da ema doaga: musa: dawa: sea, e da logo doasi dagoi hahawane ba: sa. Amo esoha, amo aseme da gawali ema doaga: mu bagade hanai gala.
Kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ igbó tí ń gbé aginjù tí ń fa ẹ̀fúùfù ìfẹ́ sí i mu rẹ, ta ni ó le è mú dúró ní àkókò rẹ̀? Kí gbogbo àwọn akọ ẹran tí o wá a kiri kì ó má ṣe dá ara wọn lágara, nítorí wọn yóò rí ní àkókò oṣù rẹ̀.
25 Isala: ili! Amo hou yolema! Di da ‘gode’ eno ilima hehenane fa: no bobogebeba: le, dia emo da wadela: sa amola dia da: gisu da hafoga: i. Be di da amane sia: sa, “Hame! Na da sinidigimu hamedei ba: sa. Na da ga fi ‘gode’ hanai gala amola na da ilima fa: no bobogemusa: dawa: lala.”
Dá ẹsẹ̀ dúró láìwọ bàtà, àti ọ̀fun rẹ nínú òǹgbẹ. Ṣùgbọ́n ìwọ wí pé, ‘Asán ni! Èmi fẹ́ràn àwọn ọlọ́run àjèjì, àwọn ni èmi yóò tọ̀ lẹ́yìn.’
26 Hina Gode da amane sia: sa, “Ilia da wamolasu dunu gagulaligisia, e da gogosiasu ba: sa. Amo defele, dilia Isala: ili dunu huluane, dilia hina bagade, eagene ouligisu dunu, gobele salasu dunu amola ba: la: lusu dunu, huluane da gogosiasu ba: mu.
“Gẹ́gẹ́ bí a ṣe ń dójútì olè nígbà tí a bá mú u, bẹ́ẹ̀ náà ni ojú yóò ti ilé Israẹli— àwọn ọba àti àwọn ìjòyè wọn, àwọn àlùfáà àti wòlíì wọn pẹ̀lú.
27 Dilia da ifa amo da dilia ada amola igi da dilia ame, amo sia: sa. Amaiba: le, dilia da se bagade amola gogosiasu ba: mu. Bai dilia da Nama mae sinidigili, Nama baligi fa: i dagoi. Be dilia da se nabasea, dilia da Nama misini, Na dili gaga: ma: ne edegesa.
Wọ́n sọ fún igi pé, ‘Ìwọ ni baba mi,’ àti sí òkúta wí pé, ‘Ìwọ ni ó bí mi,’ wọ́n ti kọ ẹ̀yìn wọn sí mi, wọn kò kọ ojú sí mi síbẹ̀ nígbà tí wọ́n bá wà nínú ìṣòro, wọn yóò wí pé, ‘Wá kí o sì gbà wá!’
28 Amo ‘gode’ liligi dilisu hamoi, amo da habila: ? Dilia se nabasea, ilia da dili fidimu da defea. Ilia da amo hou hamoma: ne defelela: ? Yuda! Dia ‘gode’ ilia idi da dia moilai bai bagade huluane ilia idi defele gala.
Níbo wá ni àwọn ọlọ́run tí ẹ ṣe fúnra yín ha a wà? Jẹ́ kí wọ́n wá kí wọ́n sì gbà yín nígbà tí ẹ bá wà nínú ìṣòro! Nítorí pé ẹ̀yin ní àwọn ọlọ́run púpọ̀, gẹ́gẹ́ bí ẹ ti ṣe ni àwọn ìlú, ìwọ Juda.
29 Dilia Nama egasu da adila: ? Dilia da abuliba: le Nama odoga: bela: ?
“Kí ló dé tí o ṣe wá ń fi ẹ̀sùn kàn mí? Gbogbo yín ni ó ti ṣọ̀tẹ̀ sí mi,” ni Olúwa wí.
30 Na da dilima se iasu be dilia hou hame hahamoi. Na da dilia hou hahamoma: ne sia: i, be dilia da hame nabi. Dilia da ougi bagade laione wa: me defele, dilia balofede dunu medole legei.
“Nínú asán mo fìyà jẹ àwọn ènìyàn yín, wọn kò sì gba ìbáwí. Idà yín ti pa àwọn wòlíì yín run, gẹ́gẹ́ bí kìnnìún tí ń bú ramúramù.
31 Isala: ili dunu! Na sia: nabima! Na da dilima adi wadela: i hou hamobela: ? Na da dilima wadela: i hafoga: i soge o gasi amola wadela: lesisu soge agoane ba: bela: ? Hame mabu! Amaiba: le, dilia da abuliba: le dilia hanaiga hamomu sia: sala: ? Abuliba: le Nama hamedafa sinidigimu sia: sala: ?
“Ẹ̀yin ìran yìí, ẹ kíyèsi ọ̀rọ̀ Olúwa: “Mo ha ti di aginjù sí Israẹli tàbí mo jẹ ilẹ̀ olókùnkùn biribiri? Èéṣe tí àwọn ènìyàn mi ṣe wí pé, ‘A ní àǹfààní láti máa rìn kiri; àwa kì yóò tọ̀ ọ́ wá mọ́?’
32 Uda a: fini da ea nina: hamosu igi gogolesala: ? Uda da ea gawa fisia ga: su abula ida: iwane gogolesala: ? Hame mabu! Be Na fi dunu da eso amo idimu hamedei amoga Na gogolei dagoi.
Wúńdíá ha le gbàgbé ohun ọ̀ṣọ́ rẹ̀, tàbí ìyàwó ohun ọ̀ṣọ́ ìgbéyàwó rẹ̀? Síbẹ̀, àwọn ènìyàn mi ti gbàgbé mi ní ọjọ́ àìníye.
33 Dilia da dili lamu dunu ilima fa: no bobogemu bagade dawa: Wadela: idafa uda da dilia hou ba: sea, eno wadela: i hou baligili hamomusa: dawa:
Ìwọ ti jẹ́ ọlọ́gbọ́n tó nípa ọ̀rọ̀ ìfẹ́! Àwọn obìnrin búburú yóò kẹ́kọ̀ọ́ nípa ọ̀nà rẹ.
34 Dilia abula da wamolasu dunu ilia maga: mega nigima: i hame, be hame gagui dunu amola asaboi wadela: i hamosu hame dawa: dunu, amo ea maga: mega nigima: i dagoi.
Lórí aṣọ rẹ ni wọ́n bá ẹ̀jẹ̀ àwọn tálákà aláìṣẹ̀, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ìwọ kò ká wọn mọ́ níbi tí wọ́n ti ń rùn wọlé. Síbẹ̀ nínú gbogbo èyí
35 Be amo mae dawa: le, dilia da amane sia: sa, ‘Ninia da wadela: i hame dawa: Hina Gode da ninima bu ougima: ne da bai hame gala.’ Be dilia da wadela: i hou hame hamosu amo ogogole sia: beba: le, Na, Hina Gode, Na da dilima se imunu.
ìwọ sọ wí pé, ‘Èmi jẹ́ aláìṣẹ̀; kò sì bínú sí mi.’ Èmi yóò mú ìdájọ́ mi wá sórí rẹ nítorí pé ìwọ wí pé, ‘Èmi kò dẹ́ṣẹ̀.’
36 Dilia da ga fi ‘gode’ liligi ilima sinidigiba: le, dilia hou fonobone wadela: lesi dagoi. Asilia fi da dili hame fidibiba: le, dilia da da: i dioi galu. Amola Idibidi da dili hame fidimuba: le, dilia da bu da: i diomu.
Èéṣe tí ìwọ fi ń lọ káàkiri láti yí ọ̀nà rẹ padà? Ejibiti yóò dójútì ọ́ gẹ́gẹ́ bí i ti Asiria.
37 Dilia da gogosiabeba: le, dialuma fili sa: ili, Idibidi mae ba: ma: ne, sinidigimu. Dilia da ga fi ilia hou dafawaneyale dawa: sa. Be Na, Hina Gode da amo dunu higale yolesi. Dilia da ilima fidisu hamedafa ba: mu.
Ìwọ yóò sì fi ibẹ̀ sílẹ̀ pẹ̀lú kíkáwọ́ rẹ lé orí rẹ, nítorí pé Olúwa ti kọ̀ àwọn tí ìwọ gbẹ́kẹ̀lé sílẹ̀, kì yóò sí ìrànlọ́wọ́ kankan fún ọ láti ọ̀dọ̀ wọn.

< Yelemaia 2 >