< Yelemaia 17 >

1 Hina Gode da amane sia: sa, “Yuda fi dunu! Dilia wadela: i hou da fedege agoane, ouli nusi amoga dedei dagoi. Amo wadela: i hou da ga: nasi igi nusi amoga dilia dogoga amola dilia oloda hegomai amoga dedei dagoi.
“Ẹ̀ṣẹ̀ Juda ni a fi kálámù irin kọ, èyí tí a fi ṣóńṣó òkúta adamante gbẹ́ ẹ, sórí wàláà oókan àyà wọn, àti sórí ìwo pẹpẹ yín.
2 Dilia da uda ‘gode’ A: sela amoma nodone sia: ne gadomusa: , ‘oloda’ amola ‘dawa: digima: ne olelesu’ amo mola: iya: i ifa dafulili amola agolo huluane amola goumi huluane umi ganodini gala, amo da: iya gagui dagoi. Amola amoga dilia nodone sia: ne gadolala.
Kódà àwọn ọmọ wọn rántí pẹpẹ àti ère Aṣerah lẹ́bàá igi tí ó tẹ́ rẹrẹ àti àwọn òkè gíga.
3 Dilia da sogebi huluane amo ganodini wadela: le bagade hamobeba: le, Na da dilia ha lai amo dilia ida: iwane liligi amola muni huluane gesowale lale, gaguli masa: ne, ilima logo doasimu.
Àwọn òkè nínú ilẹ̀ àti àwọn ọrọ̀ rẹ̀ àti ọlá rẹ̀ ni èmi yóò fi sílẹ̀ bí ìjẹ pẹ̀lú àwọn ibi gíga, nítorí ẹ̀ṣẹ̀ tí ó pọ̀ káàkiri orílẹ̀-èdè yín.
4 Na hamobeba: le, dilia da soge amo Na da dilima i, amo fisimu, amola soge dilia hamedafa dawa: , amo ganodini dilia ha lai ilia udigili se iasu hawa: hamosu hamonanumu. Bai Na ougi da lalu agoane, ha: ba: domu hamedene, eso huluane nenanumu.”
Láti ipasẹ̀ àìṣedéédéé yín ni ẹ̀yin yóò ti sọ ogún tí mo fún un yín nù. Èmi yóò fi yín fún ọ̀tá yín bí ẹrú ní ilẹ̀ tí ẹ̀yin kò mọ̀, nítorí ẹ̀yin ti mú inú bí mi, èyí tí yóò sì wà títí ayé.”
5 Hina Gode da amane sia: sa, “Nowa dunu da Na hou fisili, osobo bagade dunu ilia hou amola ilia gasa fawane dafawaneyale dawa: sea, amo dunuma Na da se imunusa: fofada: mu.
Báyìí ni Olúwa wí: “Ègbé ni fún àwọn tí ó fi ìgbẹ́kẹ̀lé wọn sínú ènìyàn, tí ó fi agbára rẹ̀ sínú ẹran-ara, àti tí ọkàn rẹ̀ kò sí lọ́dọ̀ Olúwa.
6 E da ifalobo hafoga: i soge ganodini lela agoane ba: sa. Amo osobo da deme amoga wadela: lesiba: le, liligi noga: le alemu da hamedei. Amo defele Na hou fisisu dunu da noga: le esalusu hame ba: mu.
Yóò dàbí igbó tí ó wà ní ilẹ̀ aláìlọ́ràá, kò ní rí ìre, nígbà tí ó bá dé, yóò máa gbé ní ibi ìyàngbẹ ilẹ̀ aginjù, ní ilẹ̀ iyọ̀ tí ẹnikẹ́ni kò gbé.
7 Be nowa da Na dafawaneyale dawa: beba: le, Na hou lalegagusia, Na da Na hahawane dogolegesu hou ema imunu.
“Ṣùgbọ́n ìbùkún ni fún ọkùnrin náà tí ó gbẹ́kẹ̀lé Olúwa, tí ó sì fi Olúwa ṣe ìgbẹ́kẹ̀lé rẹ̀.
8 Amo dunu da ifa, hano noga: iwane gadenene bugiba: le, ea difi da hanoga sa: i dagoi, agoaiwane ba: sa. Esosea, e da hame beda: sa. Bai ea lubi da mola: iya: i diala. Amola gibu hame dasea, e da mae dawa: iwane, fage legelala.
Yóò dàbí igi tí a gbìn sí ipadò tí ó ta gbòǹgbò rẹ̀ ká etí odò kò sí ìbẹ̀rù fún un nígbà ooru, gbogbo ìgbà ni èwe rẹ̀ máa ń tutù kò sí ìjayà fún un ní ọdún ọ̀dá bẹ́ẹ̀ ni kò ní dẹ́kun láti máa so èso.”
9 Nowa da osobo bagade dunu ea dogo dawa: digima: bela: ? Dawa: mu da hamedei. Bai osobo bagade dunu ea dogoga ogogosu hou da eno ogogosu liligi huluane baligisa. Ea dogo da oloiba: le, uhinisimu da hamedei ba: sa.
Ọkàn ènìyàn kún fún ẹ̀tàn ju ohun gbogbo lọ, ó kọjá ohun tí a lè wòsàn. Ta ni èyí lè yé?
10 Na, Hina Gode, da osobo bagade dunu ilia asigi dawa: su ba: lala amola ilia dogo amo adoba: lala. Na da dunu afae afae ilima ilia esalusu hou amola ilia hamobe hou defele, ilima hamonana.”
“Èmi Olúwa ń wo ọkàn àti èrò inú ọmọ ènìyàn, láti san èrè iṣẹ́ rẹ̀ fún un gẹ́gẹ́ bí ọ̀nà rẹ̀, àti gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀.”
11 Dunu da muni ogogole lasea, amo da sio da oso e da hame legei amoga fili, mano lalelegesa agoane gala. E da ea gasa bagade eso amoga, ea gagui huluane fisi dagoi ba: mu. Amola ea esalusu dagosea, e da gagaoui dunu agoai ba: mu.
Bí àparò tó pa ẹyin tí kò yé ni ọmọ ènìyàn tí ó kó ọrọ̀ jọ ni ọ̀nà àìṣòdodo. Yóò di ẹni ìkọ̀sílẹ̀ ní agbede-méjì ayé rẹ̀, àti ní òpin rẹ̀ yóò wá di aṣiwèrè.
12 Ninia Debolo da hadigi fisu amo da musa: goumi bagadega gagui asili, waha lela, agoai ba: sa.
Ìtẹ́ ògo; ibi gíga láti ìpilẹ̀ṣẹ̀ ní ibi ilé mímọ́ wa.
13 Hina Gode! Di fawane da ninia hobea dafawane esaloma: beyale dawa: lusu hou ouligisu dunu esala. Nowa da Di fisisia da gogosiamu. Ilia da dio osobo dou amoga dedei defele hamedafa ba: mu. Bai ilia da hano si ida: iwane (amo da Di, Hina Gode) amo yolesi dagoi.
Olúwa ìwọ ni ìrètí Israẹli; gbogbo àwọn tí ó kọ̀ ọ́ sílẹ̀ ni ojú ó tì. Àwọn tí ó padà sẹ́yìn kúrò lọ́dọ̀ rẹ ni a ó kọ orúkọ wọn sínú ekuru, nítorí wọ́n ti kọ Olúwa, orísun omi ìyè sílẹ̀.
14 Hina Gode! Dia na uhinisima! Amasea, na da hahawane esalebe ba: mu. Dia na gaga: ma! Amasea, na da gaga: i dagoi ba: mu. Na da Dima fawane nodone sia: ne gadolala.
Wò mí sàn Olúwa, èmi yóò di ẹni ìwòsàn, gbà mí là, èmi yóò di ẹni ìgbàlà, nítorí ìwọ ni ìyìn mi.
15 Dunu da nama amane sia: daha, ‘Hina Gode da nini beda: ma: ne magagiba: le, E da amo hou wahadafa ninima hamomu da defea.’
Wọ́n sọ fún mi wí pé: “Níbo ni ọ̀rọ̀ Olúwa wà? Jẹ́ kí ó di ìmúṣẹ báyìí.” Ni Olúwa wí.
16 Be Hina Gode! Di dawa: ! Na da Di ilima se iasu ima: ne hame sia: i. Ilia da bidi hamosu amola se nabasu ba: ma: ne, na da hame hanai galu. Hina Gode! Di dawa: !
Èmi kò sá kúrò láti máa jẹ́ olùṣọ àgùntàn rẹ, ìwọ mọ̀ wí pé èmi kò kẹ̀rẹ̀ ní ọjọ́ ìpọ́njú. Ohun tí ó jáde ní ètè mi jẹ́ èyí tí ó hàn sí ọ.
17 Dia na beda: ma: ne mae hamoma! Bidi hamosu da doaga: sea, Di da na gaga: su sogebi gala.
Má ṣe di ìbẹ̀rù fún mi, ìwọ ni ààbò mi ní ọjọ́ ìpọ́njú.
18 Dia da dunu amo da nama se iaha, amo ilia gogosiama: ne hamomu da defea. Be Hina Gode! Dia na gaga: ma! Ili bagade beda: ma: ne hamoma! Be na beda: ma: ne, mae hamoma! Dima ha lai dunu wadela: lesima: ne, goudane fasima!
Jẹ́ kí ojú ti àwọn ẹni tí ń lépa mi, ṣùgbọ́n pa mí mọ́ kúrò nínú ìtìjú, jẹ́ kí wọn kí ó dààmú. Mú ọjọ́ ibi wá sórí wọn, fi ìparun ìlọ́po méjì pa wọ́n run.
19 Hina Gode da nama amane sia: i, “Yelemaia! Di Dunu Ilia Logo Holei (amoga Yuda hina bagade dunu ilia moilai bai bagade amo ganodini golili maha) amoga asili, Na sia: olelema. Amasea, Yelusaleme logo holei eno huluane, amoga olelela masa.
Èyí ni ohun tí Olúwa wí fún mi: “Lọ dúró ní ẹnu-ọ̀nà àwọn ènìyàn níbi tí àwọn ọba Juda ń gbà wọlé tí wọ́n ń gbà jáde àti ní gbogbo ẹnu-bodè Jerusalẹmu.
20 Dia Yuda hina bagade amola Yuda fi dunu huluane amola dunu huluane da Yelusaleme ganodini esalebe, amo logo holeiga golili maha, ilima ilia Na sia: nabima: ne sia: ma.
Sọ fún wọ́n pé, ‘Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa ẹ̀yin ọba Juda àti gbogbo ẹ̀yin ènìyàn Juda àti gbogbo ẹ̀yin tí ń gbé ní Jerusalẹmu tí ń wọlé láti ẹnu ibodè yìí.
Báyìí ni Olúwa wí, “Ẹ kíyèsi láti máa ru ẹrù lọ́jọ́ ìsinmi tàbí kí ẹ gbé wọlé láti ẹnu ibodè Jerusalẹmu.
22 Ilia da ilia esalusu amoma asigi galea, ilia da Sa: bade eso amoga liligi maedafa gaguli masa: ne sia: ma. Ilia da liligi gaguli, Yelusaleme ea logo holeiga golili sa: imu da sema bagade. Ilia da Sa: bade esoga mae hawa: hamoma: ma. Na da ilia aowalalia ilima sia: i defele, ilia da Sa: bade eso sema eso agoane ba: ma: ne sia: ma.
Má ṣe gbé ẹrù jáde kúrò nínú ilé yín, bẹ́ẹ̀ ni kí ẹ má ṣe ṣe iṣẹ́kíṣẹ́ ní ọjọ́ ìsinmi ṣùgbọ́n kí ẹ pa ọjọ́ ìsinmi mọ́ fún àwọn baba ńlá yín.”
23 Ilia aowalalia da Na sia: hame nabi amola hame dawa: digi. Be amo mae dawa: le, ilia dogo ga: nasima: ne hamoi. Ilia da Na sia: hame nabasu amola Na olelesu amoma hame fa: no bobogei.
Síbẹ̀ wọn kò gbọ́ tàbí tẹ́tí sílẹ̀, wọ́n jẹ́ ọlọ́rùn líle; wọn kì í fẹ́ gbọ́ tàbí gba ìbáwí.
24 Amo dunu ilia Na sia: amola Na sema huluane nabima: ne sia: ma. Ilia da Sa: bade esoga liligi gaguli, moilai logo holeiga golili masunu da sema bagade sia: ma. Sa: bade eso da sema eso. Amaiba: le, amoga ilia hawa: hamosu maedafa hamoma: ne sia: ma.
Ṣùgbọ́n tí ẹ̀yin bá kíyèsi láti gbọ́ tèmi ní Olúwa wí, tí ẹ kò sì gbe ẹrù gba ẹnu-bodè ìlú ní ọjọ́ ìsinmi, ṣùgbọ́n tí ẹ ya ọjọ́ ìsinmi, sí mímọ́, nípa pé ẹ kò ṣe iṣẹ́kíṣẹ́ ní ọjọ́ náà.
25 Amasea, ilia hina bagade dunu amola ilia egefelali da Yelusaleme logo holeiga moilai golili sa: ili, Da: ibidi ea gasa defele gasawane hawa: hamomu. Ilia amola Yuda fi dunu amola Yelusaleme fi dunu da sa: liode amola hosi da: iya fila heda: le masunu. Amola Yelusaleme da dunu amoga nabaiwane ba: lalumu.
Nígbà náà ni ọba tí ó jókòó lórí ìtẹ́ Dafidi yóò gba ẹnu ibodè wọlé pẹ̀lú àwọn ìjòyè rẹ̀. Àwọn àti ìjòyè wọn yóò gun ẹṣin àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wá, àwọn ọkùnrin Juda àti àwọn olùgbé Jerusalẹmu yóò tẹ̀lé wọn; ìlú yìí yóò sì di ibi gbígbé títí láéláé.
26 Dunu da Yuda moilai huluane amola moilai amo da Yelusaleme sisiga: sa, amoga misunu. Ilia Bediamini soge amola agolo goumi baiga diala, amola goumi amola Yuda gagoe (south) sogebi amoga misunu. Ilia da Na Debolo diasu amoga gobele salasu ohe amola gobele salasu liligi eno, amola gagoma amola gabusiga: manoma amola Nama nodomusa: iasu liligi gaguli misunu.
Àwọn ènìyàn yóò wá láti ìlú Juda àti ní agbègbè Jerusalẹmu, láti ilẹ̀ Benjamini, láti pẹ̀tẹ́lẹ̀, àti láti òkè, àti láti gúúsù wá, wọn yóò wá pẹ̀lú ọrẹ ẹbọ sísun, àti ọrẹ ẹran, àti tùràrí, àti àwọn tó mú ìyìn wá sí ilé Olúwa.
27 Be ilia da Na sia: nabima: ne, amola Sa: bade eso da sema eso, amo dawa: ma: ne sia: ma. Ilia da Sa: bade esoga liligi gaguli, Yelusaleme logo holeiga maedafa golili misa: ne sia: ma. Be ilia amo sema fisia, Na da Yelusaleme logo holei laluga ulagisimu. Yelusaleme hina bagade ilia diasu da laluga nene dagole, enoga ha: ba: domu da hamedei ba: mu.”
Ṣùgbọ́n bí ẹ̀yin kò bá pa òfin mi mọ́ láti ya ọjọ́ ìsinmi sí mímọ́, kí ẹ má sì ṣe ru ẹrùkẹ́rù bí ẹ̀yin yóò ṣe máa gba ẹnu ibodè Jerusalẹmu wọlé ní ọjọ́ ìsinmi, nígbà náà ni èmi yóò da iná tí kò ní ṣe é parun ní ẹnu-bodè Jerusalẹmu tí yóò sì jó odi agbára rẹ̀.’”

< Yelemaia 17 >