< Yelemaia 14 >

1 Hina Gode da esoi bagade ea hou olelema: ne, nama amane sia: i,
Èyí ni ọ̀rọ̀ Olúwa sí Jeremiah nípa ti àjàkálẹ̀-ààrùn:
2 “Yuda soge da da: i dioiwane didigia: su. Ea moilai bai bagade huluane da bogogia: lala. Ea fi dunu huluane da da: i dione, osoboga dia dafia: sa. Amola Yelusaleme da enoga fidima: ne wele sia: nana.
“Juda káàánú, àwọn ìlú rẹ̀ kérora wọ́n pohùnréré ẹkún fún ilẹ̀ wọn, igbe wọn sì gòkè lọ láti Jerusalẹmu.
3 Bagade gagui dunu da ilia hawa: hamosu dunu hano dima: ne asunasisa. Ilia da hano si amoga asili, hano hame dialebe ba: sa. Ilia hano nasu ganagu hano hamedei hagiwane bu gaguli maha. Ilia da: i dioiwane amola gagoudanu, gogosiane ilia odagi dedebole, buhagisa.
Àwọn ọlọ́lá ènìyàn rán àwọn ìránṣẹ́ wọn lọ bu omi, wọ́n lọ sí ìdí àmù ṣùgbọ́n wọn kò rí omi. Wọ́n padà pẹ̀lú ìkòkò òfìfo; ìrẹ̀wẹ̀sì àti àìnírètí bá wọn, wọ́n sì bo orí wọn.
4 Gibu da hame sa: iba: le, amola osobo huluane da hafoga: iba: le, ifabi ouligisu dunu da baligili da: i dione heawisa. Ilia amola odagi dedebosa.
Ilẹ̀ náà sán nítorí pé kò sí òjò ní ilẹ̀ náà; ìrètí àwọn àgbẹ̀ di òfo, wọ́n sì bo orí wọn.
5 Sogega, “dia” ohe ame da ea gaheabolo lalelegei mano amo fisiagasa. Bai gisi hame galebeba: le.
Kódà, abo àgbọ̀nrín tí ó wà lórí pápá fi ọmọ rẹ̀ tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ bí sílẹ̀, torí pé kò sí koríko.
6 Sigua ‘dougi’ da agolo da: iya lela. Ilia sigua wa: me defele ha: ha: sa. Ilia da ha: i manu hameba: le, ilia si da wadela: sa.
Àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ igbó dúró lórí òkè òfìfo wọ́n sì ń mí ẹ̀fúùfù bí ìkookò ojú wọn kò ríran nítorí pé kò sí koríko jíjẹ.”
7 Na fi dunu da Nama amane wele sia: sa, ‘Dafawane! Ninia wadela: i hou da ninima diwane udidisa. Be Hina Gode! Dia musa: ilegele sia: i defele, nini fidima! Ninia da eso bagohame Di baligi fa: sea, wadela: le hamoi ba: sa.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹ̀ṣẹ̀ wa jẹ́rìí lòdì sí wa, wá nǹkan kan ṣe sí i Olúwa, nítorí orúkọ rẹ. Nítorí ìpadàsẹ́yìn wa ti pọ̀jù, a ti ṣẹ̀ sí ọ.
8 Be Di fawane da Isala: ili fi gaga: musa: dawa: Di fawane da nini mae wadela: lesima: ne, gaga: musa: dawa: Di da abuliba: le ga fi dunu amo da gasi afadafa fawane ninia soge ganodini esalebe, agoane ba: sala: ?
Ìrètí Israẹli; ìgbàlà rẹ lásìkò ìpọ́njú, èéṣe tí ìwọ dàbí àlejò ní ilẹ̀ náà bí arìnrìn-àjò tí ó dúró fún bí òru ọjọ́ kan péré?
9 Di da abuliba: le, dunu da fofogadigibi agoane ba: sala: ? Abuliba: le, gasa hame dadi gagui nini fidimusa: hame dawa: agoane ba: sala: ? Hina Gode! Di da dafawane ninimagale esala! Ninia da Dia fi dunu! Nini mae yolesima!’”
Èéṣe tí ìwọ dàbí ẹni tí a dààmú, bí jagunjagun tí kò le ran ni lọ́wọ́? Ìwọ wà láàrín wa, Olúwa, orúkọ rẹ ni a sì ń pè mọ́ wa; má ṣe fi wá sílẹ̀.
10 Hina Gode da Ea fi dunu ilia hou olelema: ne, amane sia: sa, “Ilia da Na fisimusa: hobeamu hanai gala. Ilia da ilia hou amoma hina esaloma: ne hame dawa: Amaiba: le, Na da ilima hahawane hame. Na da ilia wadela: i hou bu dawa: mu amola amoba: le, se ilima imunu.”
Báyìí ni Olúwa sọ nípa àwọn ènìyàn wọ̀nyí: “Wọ́n fẹ́ràn láti máa rìn kiri; wọn kò kó ọkàn wọn ní ìjánu. Nítorí náà Olúwa kò gbà wọ́n; yóò wá rántí ìwà búburú wọn báyìí, yóò sì fi ìyà ẹ̀ṣẹ̀ wọn jẹ wọ́n.”
11 Hina Gode da nama amane sia: i, “Amo dunu fidima: ne, Nama mae adole ba: ma!
Nígbà náà ni Olúwa sọ fún mi pé, “Má ṣe gbàdúrà fún àlàáfíà àwọn ènìyàn wọ̀nyí.
12 Ilia da ha: i mae nawane sia: ne gadosea, Na da ili fidima: ne wele sia: su hame nabimu. Amola ilia da Nama ohe gobele salasu amola gagoma iasu iasea, Na da ili hahawane hame ba: mu. Be amo mae dawa: le, Na da gegesu amola ha: naba amola olo ilima iasili, ili medole lelegemu.”
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé wọ́n gbààwẹ̀, èmi kò ní tẹ́tí sí igbe wọn. Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé wọ́n rú ẹbọ sísun àti ẹbọ ìyẹ̀fun, èmi ò nígbà wọ́n. Dípò bẹ́ẹ̀, èmi ó fi idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn pa wọ́n run.”
13 Amalalu, na da amane sia: i, “Ouligisudafa Hina Gode! Di dawa: ! Balofede dunu da Dia fi dunu da ha: i bagade amola gegesu hame ba: mu, amo ilima agoane sia: sa. Bai Di da sia: i dagoi, olofosu fawane da Dia soge amo ganodini ba: mu, ilia sia: sa.”
Ṣùgbọ́n mo sọ pé, “Háà! Olúwa Olódùmarè. Àwọn wòlíì ń sọ fún wọn pé, ‘Ẹ kò ni rí idà tàbí ìyàn. Dájúdájú èmi ó fún yín ní àlàáfíà tí yóò tọ́jọ́ níbí yìí?’”
14 Be Hina Gode da nama bu adole i, “Amo balofede dunu da Na Dioba: le ogogosa. Na da ili hame asunasi amola ilia da Na sia: alofele olelema: ne, Na da hamedafa sia: i. Ilia esala ba: su olelebe amo da Nama hame misi. Ilia ba: la: lusu liligi da hamedei liligi amo ilisu ilia asigi dawa: su ganodini hamoi.
Nígbà náà Olúwa sọ fún mi pé, “Àwọn wòlíì ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ èké ní orúkọ mi. Èmi kò rán wọn, tàbí yàn wọ́n tàbí bá wọn sọ̀rọ̀. Ìran èké ni wọ́n ń rí sí i yín. Àsọtẹ́lẹ̀ èké ni wọ́n ń sọ fún un yín nípa ìran ìrírí, àfọ̀ṣẹ, ìbọ̀rìṣà àti ìtànjẹ ọkàn wọn.
15 Na, Hina Gode, da dima olelemu. Amo balofede dunu (amo Na da hame asunasi, be ilia da Na Dioba: le gegesu amola ha: i bagade da hame misunu ogogole sia: sa) Na da ili gegesu amola ha: i bagade amoga medole legemu.
Nítorí náà, èyí ni Olúwa sọ nípa àwọn wòlíì tí wọ́n ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ lórúkọ mi. Èmi kò rán wọn, síbẹ̀ wọ́n sì ń sọ pé, ‘Idà kan tàbí ìyàn, kì yóò dé ilẹ̀ yìí.’ Àwọn wòlíì kan náà yóò parẹ́ nípa idà àti ìyàn.
16 Dunu amoma ilia amo liligi ogogole sia: i, ilia amola da gegesu amola ha: i bagade amoga medole legei ba: mu. Ilia bogoi da: i hodo da Yelusaleme logoga ha: digi dagoi ba: mu, amola amo uli dogoma: ne, dunu afae da hame ba: mu. Amo hou da ili huluanema doaga: mu. Amoga ilia uda amola dunu mano amola uda mano, huluane medole legei dagoi ba: mu. Ilia wadela: i hou hamoiba: le, dabe lamu.”
Bẹ́ẹ̀ sì ni àwọn ènìyàn tí wọ́n ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ fún ni a ó lé sí òpópónà Jerusalẹmu torí idà àti ìyàn. Wọn kò ní i rí ẹni tí yóò sìn wọ́n tàbí ìyàwó wọn, àwọn ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin wọn. Èmi yóò mú ìdààmú tí ó yẹ bá ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin wọn.
17 Hina Gode da na da Ea fi dunu ilima na da: i dioi ilima olelema: ne sia: i. Ea sia: beba: le, na da ilima amane sia: i, “Haga amola gasia amola na si hano da gudu sa: imu da defea. Na dibi da hamedafa dagomu. Bai na fi dunu da oso dogone fa: ginisi amola se bagade naba.
“Kí ìwọ kí ó sì sọ ọ̀rọ̀ yìí fún wọn pé: “‘Jẹ́ kí ojú mi kí ó sun omijé ní ọ̀sán àti ní òru láìdá; nítorí tí a ti ṣá wúńdíá, ọmọ ènìyàn mi ní ọgbẹ́ ńlá pẹ̀lú lílù bolẹ̀.
18 Na da moifufu amoga ahoasea, na da dunu gegesu ganodini medole legei ilia bogoi da: i hodo ba: sa. Na da moilai gagagai amo ganodini ahoasea, na da dunu ha: ga bogogia: lalebe ba: sa. Balofede amola gobele salasu dunu amola da mugululi, soge amo ilia hame dawa: soge amoga afugili asi.”
Bí mo bá lọ sí orílẹ̀-èdè náà, Èmi yóò rí àwọn tí wọ́n fi idà pa. Bí mo bá lọ sí ìlú ńlá, èmi rí àwọn tí ìyàn ti sọ di aláàrùn. Wòlíì àti Àlùfáà ti lọ sí ilẹ̀ tí wọn kò mọ̀.’”
19 Hina Gode! Di da dafawanedafa Yuda fi fisiagabela: ? Di da Saione dunu higasala: ? Di da abuliba: le nini mae uhima: ne ninima se bagadedafa ibala: ? Ninia da olofosu hogoi helei, be hahawane hou da hame doaga: i. Ninia da uhinisisu hogoi helei, be beda: su bagade fawane ba: i.
Ṣé o ti kọ Juda sílẹ̀ pátápátá ni? Ṣé o ti ṣá Sioni tì? Èéṣe tí o fi pọ́n wa lójú tí a kò fi le wò wá sàn? A ń retí àlàáfíà ṣùgbọ́n ohun rere kan kò tí ì wá, ní àsìkò ìwòsàn ìpayà là ń rí.
20 Hina Gode! Ninia da dima wadela: le bagade hamoi. Ninia wadela: i hou amola ninia aowalalia ilia wadela: i hou, amo ninia Dima fofada: nana.
Olúwa, a jẹ́wọ́ ìwà ibi wa àti àìṣedéédéé àwọn baba wa; lóòótọ́ ni a ti ṣẹ̀ sí ọ.
21 Dia hahawane ninima imunu sia: i ilegesu amo bu dawa: ma! Dia nini mae higama! Yelusaleme da Dia hadigi fisu ea sogebi. Amaiba: le, Yelusaleme da gogosiasa: besa: le, gaga: ma. Dia gousa: su ninima hamoi amo mae fima.
Nítorí orúkọ rẹ má ṣe kórìíra wa; má ṣe sọ ìtẹ́ ògo rẹ di àìlọ́wọ̀. Rántí májẹ̀mú tí o bá wa dá kí o má ṣe dà á.
22 Fifi asi gala ilia loboga hamoi ogogosu ‘gode’ da gibu iasimu hame dawa: Mu hisu da gibu hamomu hame dawa: Ninia Hina Gode! Di fawane da amo hamomusa: dawa: Amaiba: le, ninia dafawaneyale esaloma: beyale dawa: lusu da Di fawane.
Ǹjẹ́ èyíkéyìí àwọn òrìṣà yẹ̀yẹ́ tí àwọn orílẹ̀-èdè le ṣe kí òjò rọ̀? Ǹjẹ́ àwọsánmọ̀ fúnra rẹ̀ rọ òjò bí? Rárá, ìwọ ni, Olúwa Ọlọ́run wa. Torí náà, ìrètí wa wà lọ́dọ̀ rẹ, nítorí pé ìwọ lo ń ṣe gbogbo nǹkan wọ̀nyí.

< Yelemaia 14 >