< Aisaia 8 >

1 Hina Gode da nama amane sia: i, “Dia meloa bioi bagade lale, amoga dunu noga: le idima: ne agoane dedemu, ‘Ma: ihi Sia: ila: ile Ha: isaba: se ‘(dawaloma: ne da hedolo wamolale, gaguli masa)’
Olúwa sọ fún mi pé, mú ìwé ńlá kan, kí o sì fi kálàmù ìkọ̀wé lásán kọ Maha-Ṣalali-Haṣi-Basi.
2 Amo dedei dafawaneyale ba: ma: ne, ba: su dunu moloidafa aduna ilegemu. Amo da gobele salasu ouligisu ea dio amo Iulaia amola Segalaia (Yibeligaia egefe) ilegema.
Èmi yóò sì mú Uriah àlùfáà àti Sekariah ọmọ Jeberekiah gẹ́gẹ́ bí ẹlẹ́rìí òtítọ́ wá sí ọ̀dọ̀ mi.
3 Fa: no, na uda da abula agui ba: i. Ania dunu mano lalelegeloba, Hina Gode da nama amane sia: i, “Dia manoma ‘Ma: ihi Sia: ila: ile Ha: isiaba: se” dio asulima.
Lẹ́yìn náà, mo lọ sí ọ̀dọ̀ wòlíì obìnrin náà, ó sì lóyún, ó sì bí ọmọkùnrin kan. Olúwa sì wí fún mi pé, “Pe orúkọ rẹ̀ ní Maha-Ṣalali-Haṣi-Basi.
4 E da fonobahadi fawane asigilale, ‘Ada’ amola ‘Ame’ amo sia: musa: dawa: mu. Be hidadea, amo sia: mu hamedei galea, Asilia hina bagade da Dama: sagase amola Samelia, amo ea muni amola liligi ida: iwane wamolale, gaguli masunu.”
Kí ọmọkùnrin náà tó mọ bí a ti ń sọ pé, ‘Baba mi’ tàbí ‘Ìyá mi,’ gbogbo ọrọ̀ Damasku àti ìkógun ti Samaria ni ọba àwọn Asiria yóò ti kó lọ.”
5 Hina Gode da bu nama sia: i.
Olúwa sì tún sọ fún mi pé,
6 E da amane sia: i, “Yuda dunu da Hano Siloua: me ea olofoi hano amo higa: i dagoi. Amola ilia da hina bagade Lisini amola hina bagade Biga amoma beda: iba: le, yagugusa.
“Nítorí pé àwọn ènìyàn yìí ti kọ omi Ṣiloa tí ń sàn jẹ́ẹ́jẹ́ sílẹ̀ tí wọ́n sì ń yọ̀ nínú Resini àti ọmọ Remaliah,
7 Amaiba: le, Na, Hina Gode, da Asilia hina bagade amola ea dadi gagui dunu huluane, amo Yuda dunu fi ilima doagala: musa: oule misunu. Iufala: idisi Hano da neda: le, ea bega: nabale aduga: le daha amo defele ilia da misunu.
ǹjẹ́ nítorí náà kíyèsi i, Olúwa ń fa omi odò tí ó le, tí ó sì pọ̀ wá sórí wọn, àní, ọba Asiria àti gbogbo ògo rẹ̀, yóò sì wá sórí gbogbo ọ̀nà odò rẹ̀, yóò sì gun orí gbogbo bèbè rẹ̀,
8 Ilia da Yuda sogega hano bagade neda: i agoane misini, bagade heda: le, liligi huluane dedebomu.” Gode da nini esala! Ea ougia ligia gadole da ninia soge gaga: sa.
yóò sì gbá àárín Juda kọjá, yóò sì ṣàn bò ó mọ́lẹ̀, yóò sì mú un dọ́rùn. Nínà ìyẹ́ apá rẹ̀ yóò sì bo gbogbo ìbú ilẹ̀ rẹ̀, ìwọ Emmanueli.”
9 Dilia fifi asi gala dunu fi huluane beda: iwane gilisima! Soge sedaga fi huluane, nabima! Gegemusa: momagema, be beda: ma! Dafawane! Momagema, be beda: iwane dawa: ma!
Ké ariwo ogun, ẹ̀yin orílẹ̀-èdè, kí a sì fọ́ ọ yín túútúú, fetísílẹ̀, ẹ̀yin ilẹ̀ jíjìn réré. Ẹ palẹ̀mọ́ fún ogun, kí a sì fọ́ ọ túútúú!
10 Gegemusa: ilegema! Be dilia ilegesu da dafamu. Baligiliwane fada: i sia: ma! Be dilia momagesu da hamedei. Bai Gode da ninima esala.
Ẹ gbìmọ̀ pọ̀, yóò sì di asán, ẹ gbèrò ọ̀rọ̀ náà, ṣùgbọ́n kì yóò dúró, nítorí Ọlọ́run wà pẹ̀lú wa.
11 Hina Gode da Ea gasa bagade amoga, na da Yuda dunu eno ilima mae fa: no bobogema: ne sisane sia: i.
Olúwa bá mi sọ̀rọ̀ pẹ̀lú ọwọ́ agbára rẹ̀ o ìkìlọ̀ fún mi pé, èmi kò gbọdọ̀ tẹ̀lé ọ̀nà àwọn ènìyàn wọ̀nyí. Ó wí pé,
12 E da amane sia: i, “Di da amo dunu ilia ilegesu amoma mae gilisima, amola liligi amoma ilia da beda: i, amoba: le di mae beda: ma.
“Má ṣe pe èyí ní ọ̀tẹ̀ gbogbo ohun tí àwọn ènìyàn yìí pè ní ọ̀tẹ̀, má ṣe bẹ̀rù ohun tí wọ́n bá bẹ̀rù, má sì ṣe fòyà rẹ̀.
13 Na, Hina Gode Bagadedafa da Hadigi (Houli)! Amo mae gogolema! Di da eno dunuma mae beda: ne, Nama fawane beda: ma.
Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni Ẹni tí ìwọ yóò kà sí mímọ́, Òun ni kí o bẹ̀rù Òun ni kí àyà rẹ̀ fò ọ́,
14 Na da baligili Hadigidafa. Amaiba: le, Na da fedege agoane, igi amoga dunu da emo udasisu gala. Na da sani amoga Yuda amola Isala: ili dunu amola Yelusaleme dunu daha.
Òun yóò sì jẹ́ ibi mímọ́ ṣùgbọ́n fún ilé Israẹli méjèèjì ni yóò jẹ́, òkúta tí í mú ni kọsẹ̀ àti àpáta tí ó mú wọn ṣubú àti fún àwọn ènìyàn Jerusalẹmu ni yóò jẹ́ tàkúté àti ìdẹ̀kùn.
15 Dunu bagohame da dafane, goudai dagoi ba: mu. Ilia da amo saniga sa: imu.”
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ wọn ni yóò kọsẹ̀, wọn yóò ṣubú wọn yóò sì fọ́ yángá, okùn yóò mú wọn, ọwọ́ yóò sì tẹ̀ wọ́n.”
16 Dilia! Na adoba: su dunu! Dilia sia: , amo Gode da nama i, amo noga: le ouligima!
Di májẹ̀mú náà kí o sì fi èdìdì di òfin náà láàrín àwọn ọmọ-ẹ̀yìn mi.
17 Hina Gode da Ea fi dunu E mae ba: ma: ne, wamoaligi dagoi. Be na da Ea hou dafawaneyale dawa: be, amola E da fa: no misunu hou amo noga: le ouligisu na dawa:
Èmi yóò dúró de Olúwa, ẹni tí ó ń fi ojú rẹ̀ pamọ́ fún ilé Jakọbu. Mo fi ìgbẹ́kẹ̀lé mi sínú rẹ.
18 Na amola mano amo Hina Gode da nama i, da lela. Hina Gode Bagadedafa Ea Fisu da Saione Goumiga gala, amola E da nini sia: ne iasu esala agoane Isala: ili fi dunu ilima asunasi dagoi.
Èmi nìyí, àti àwọn ọmọ tí Olúwa fi fún mi. Àwa jẹ́ àmì àti àpẹẹrẹ ní Israẹli láti ọ̀dọ̀ Olúwa àwọn ọmọ-ogun, ẹni tí ó ń gbé ní òkè Sioni.
19 Be eno dunu da dilia udigili ba: la: lusu dunu amola gesami dasu (amo da gesami hea: sa amola hehedosa) amoma adole ba: ma: ne sia: mu. Be abuliba: le esala dunu fidima: ne, bogoi dunu amoma adole ba: ma: bela: ?”
Nígbà tí àwọn ènìyàn bá sọ fún un yín pé kí ẹ lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn abókùúsọ̀rọ̀ àti àwọn oṣó, ti máa ń kún tí wọ́n sì ń sọ̀rọ̀ kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́, ǹjẹ́ kò ha yẹ kí àwọn ènìyàn béèrè lọ́wọ́ Ọlọ́run wọn bí? Èéṣe tí ẹ fi ń bá òkú sọ̀rọ̀ ní orúkọ alààyè?
20 Be dilia bu adole ima, “Gode Ea sema amola Ea dedei huluane amo fawane dawa: ma. Gesami dasu dunu ilia sia: maedafa nabima! Eno dunu da Gode Ea sia: defele hame sia: sea, amo dunu da hadigi hame, ogogosu fawane dawa: ma.”
Sí òfin àti májẹ̀mú! Bí wọn kò bá sọ̀rọ̀ gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ yìí, wọn kò rí ìmọ́lẹ̀ ọjọ́.
21 Isala: ili dunu da ha: i nabawane amola da: i dione, udigili soge ganodini lalumu. Ilia da ha: iba: le amola ougiba: le, ba: le gadole ilia Hina bagade amola Godema gagabusu aligima: ne sia: mu.
Nínú ìnilára àti ebi, ni wọn yóò máa kọjá lọ láàrín ilẹ̀ náà, nígbà tí ebi bá pa wọ́n, nígbà yìí ni wọn yóò máa kanra, wọn yóò wòkè, wọn yóò sì fi ọba àti Ọlọ́run wọn ré.
22 Amasea, ilia da osoboga ba: le guduli, be bidi hamoi amola gasi amola beda: ma: ne gasi amoga Gode da ili sefasilala, amo fawane ba: mu.
Nígbà náà ni wọn yóò sì wolẹ̀, wọn yóò sì rí ìpọ́njú, òkùnkùn àti ìpòrúru tí ó ba ni lẹ́rù, a ó sì sọ wọ́n sínú òkùnkùn biribiri.

< Aisaia 8 >