< Aisaia 65 >

1 Hina Gode da amane sia: i, “Na da Na fi dunu ilia sia: ne gadosu amoma adole imunusa: momagele esalu, be ilia da Nama hame sia: ne gadoi. Ilia da Na hogoi helele, ba: mu, Na da dawa: i galu. Be ilia da hame hogoi helei. Na da eso huluane Isala: ili fi fidimusa: ouesalu, be ilia da Nama hame sia: ne gadoi. Be Na da ilima adole imunusa: , “Na da wea! Na da dili fidimu!” amo sia: ma: ne momagele esalu.
“Èmi fi ara mi hàn fún àwọn tí kò béèrè fún mi; àwọn tí kò wá mi ni wọ́n rí mi. Sí àwọn orílẹ̀-èdè tí kò pe orúkọ mi, ni èmi wí pé, ‘Èmi nìyìí, Èmi nìyìí.’
2 Na fi dunu da higale, wadela: i hou hamosa, amola ilia hanaiga fawane ahoa. Be Na da eso huluane ili hahawane aowamusa: ouesalu.
Gbogbo ọjọ́ ni mo ti nawọ́ mi síta sí àwọn ènìyàn ọlọ́rùn líle, tí wọn ń rìn lọ́nà tí kò dára, tí wọ́n sì gbára lé èrò ara wọn
3 Ilia da mae gogosiane, Na ougima: ne hamonana. Ilia da sema ifabi ganodini, ogogosu ‘gode’ liligi ilima gobele salasu hou hamosa. Amola ogogosu ‘gode’ ilia oloda da: iya, gabusiga: manoma gobesisa.
àwọn ènìyàn tí wọ́n bí mi nínú nígbà gbogbo lójú ara mi gan an, wọ́n ń rú ẹbọ nínú ọgbà wọ́n sì ń sun tùràrí lórí i pẹpẹ bíríkì;
4 Gasia, ilia da magufu gelabo amola bogoi uli dogoi amoga bogoi a: silibu ilima sia: sa: imusa: ahoa. Ilia da gebo huna bobodole gobei amo ogogosu ‘gode’ma gobele salimusa: hamoi, amo naha.
wọ́n ń jókòó láàrín ibojì wọ́n sì ń lo òru wọn nínú ìṣọ́ ìkọ̀kọ̀; tí wọ́n ń jẹ ẹran ẹlẹ́dẹ̀, tí ìkòkò ọbẹ̀ wọn kún fún ẹran àìmọ́;
5 Amalalu, ilia da eno dunuma amane sia: sa, “Gadenene mae misa! Nini mae digili ba: ma! Bai ninia da sema hadigi hamoi dagoi.” Na da agoaiwane dunu bagade higa: i. Na ilima ougi da lalu bagade amo da ha: ba: domu hame gala, agoaiwane gobesisa.
tí ó wí pé, ‘Ẹ sún mẹ́yìn; ẹ má wá sọ́dọ̀ mi, nítorí mo ti jẹ́ mímọ́ jù fún un yín!’ Àwọn ènìyàn bẹ́ẹ̀ jẹ́ èéfín nínú ihò imú mi iná tí ń fi gbogbo ọjọ́ jó.
6 Na da amo dunu ilima se iasu ilegele dedei dagoi. Na da ilia wadela: i hou hame gogolemu be dabe ilima imunu.
“Kíyèsi i, a ti kọ ọ́ síwájú mi, Èmi kì yóò dákẹ́, ṣùgbọ́n èmi yóò san án padà lẹ́kùnrẹ́rẹ́; Èmi yóò san án padà sí àyà wọn
7 Ilia da wadela: i hou hamoiba: le, amola ilia aowalali dunu da wadela: i hamoiba: le, Na da ilima dabe imunu. Ilia da ogogosu ‘gode’ ilia agolo da: iya gagui sia: ne gadosu sogebi amoga gabusiga: manoma gobesi amola Na Dio wadela: lesi. Amaiba: le, ilia wadela: i hou hamoi amo defele, Na da ilima dabe imunu.”
àwọn ẹ̀ṣẹ̀ yín àti tàwọn baba yín,” ni Olúwa wí. “Nítorí pé wọ́n sun ẹbọ ní orí òkè ńlá wọ́n sì ṣe ẹ̀gbin sí mi ní òkè kékeré, Èmi yóò wọ́n ọ́n sí itan wọn ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ ẹ̀san ohun gbogbo tí wọ́n ṣe tẹ́lẹ̀.”
8 Hina Gode da amane sia: sa, “Dunu da waini fage noga: i amo udigili hame wadela: lesisa. Be amo lale, ilia da waini hano hamosa. Na amola da Na fi huluanedafa hame gugunufinisimu. Be mogili da Nama fa: no bobogebeba: le, Na da ili gaga: mu.
Báyìí ni Olúwa wí: “Gẹ́gẹ́ bí ìgbà tí oje sì tún wà nínú àpólà àjàrà tí àwọn ènìyàn sì wí pé, ‘Má ṣe bà á jẹ́, nítorí ìbùkún ń bẹ nínú rẹ̀,’ bẹ́ẹ̀ ni èmi yóò ṣe nítorí ìránṣẹ́ mi; Èmi kì yóò pa gbogbo wọn run.
9 Na da Isala: ili dunu amo da Yuda fi amo ganodini esala ilima hahawane hamomu. Iligaga fi da Na goumi soge gagumu. Na ilegei fi dunu amo da Na hawa: hamonana, amo da amo sogega esalumu.
Èmi yóò mú ìrandíran wá láti ìdílé Jakọbu, àti láti Juda àwọn tí yóò jogún òkè ńlá mi wọ̀n-ọn-nì; àwọn àyànfẹ́ ènìyàn mi yóò jogún wọn, ibẹ̀ ni àwọn ìránṣẹ́ mi yóò sì gbé.
10 Ilia da Nama nodomu. Amola ilia da ilia sibi amola bulamagau gisi moma: ne Sielone Umi gududili gala amola Bidi Hamosu Fago gusudili gala amoga oule masunu.
Ṣaroni yóò di pápá oko fún ọ̀wọ́ ẹran, àti àfonífojì Akori yóò di ibi ìsinmi fún agbo ẹran, fún àwọn ènìyàn mi tí ó wá mi.
11 Be dilia mogili da Na hou fisiagale, Na sema agolo Saione higasa amola ogogosu ‘gode’ Ga: de amola Meni (amo da hahawane doaga: su hou amola udigili manebe hou ilia da sia: sa) amoma fa: no bobogesa. Be hou hisu da dilima doaga: mu.
“Ṣùgbọ́n fún ẹ̀yin tí ó kọ Olúwa sílẹ̀ tí ó sì gbàgbé òkè ńlá mímọ́ mi, tí ó tẹ́ tábìlì fún Gadi tí ẹ sì kún abọ́ pẹ̀lú ọtí wáìnì fún àtubọ̀tán,
12 Dilia da se nabawane bogomu. Bai Na da wele sia: beba: le, dilia da hame bu adole i, amola Na da sia: beba: le, dilia da nabimu higa: i. Be dilia da Na sia: mae nabima: ne amola wadela: i hou hamoma: ne, ilegei dagoi.
Èmi yóò yà ọ́ sọ́tọ̀ fún idà, àti pé ẹ̀yin yóò bẹ̀rẹ̀ mọ́lẹ̀ fún àwọn tí a pa; nítorí mo pè, ṣùgbọ́n ẹ̀yin kò dáhùn. Mo sọ̀rọ̀ ṣùgbọ́n ẹ̀yin kò tẹ́tí sílẹ̀. Ẹ̀yin ṣe búburú ní ojú mi ẹ sì yan ohun tí ó bà mí lọ́kàn jẹ́.”
13 Amaiba: le, Na dilima amane sia: sa, ‘Nowa da Nama nodone sia: ne gadosea, amola Na sia: nabasea, da ha: i manu amola hano moma: ne defele ba: mu. Be dilia da ha: mu amola hano hanamu. Ilia da hahawane esalumu be dilia da gogo sia: su ba: mu.
Nítorí náà, báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí: “Àwọn ìránṣẹ́ mi yóò jẹun; ṣùgbọ́n ebi yóò máa pa ẹ̀yin, àwọn ìránṣẹ́ mi yóò mu, ṣùgbọ́n òǹgbẹ yóò máa gbẹ ẹ̀yin; àwọn ìránṣẹ́ mi yóò ṣe àjọyọ̀, ṣùgbọ́n a ó dójútì yin.
14 Ilia da hahawaneba: le, gesami hea: mu. Be dilia da se bagade nababeba: le, dinanawane wele sia: mu.
Àwọn ìránṣẹ́ mi yóò kọrin láti inú ayọ̀ ọkàn wọn wá, ṣùgbọ́n ẹ̀yin yóò kígbe sókè láti inú ìrora ọkàn yín àti ìpohùnréré ní ìròbìnújẹ́ ọkàn.
15 Na ilegei fi dunu da dilia dioba: le, gagabusu aligima: ne sia: mu. Na, Hina Bagade Ouligisudafa, da dili medole lelegemu. Be nowa da Nama fa: no bobogesea, Na da ilima dio gaheabolo asulimu.
Ẹ̀yin yóò fi orúkọ yín sílẹ̀ fún àwọn àyànfẹ́ mi gẹ́gẹ́ bí ègún; Olúwa Olódùmarè yóò sì pa yín, ṣùgbọ́n fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ ni òun yóò fún ní orúkọ mìíràn.
16 Nowa Isala: ili soge ganodini esala dunu da Nama hahawane dogolegele iasu adole ba: sea, Na, Dafawane Hamosu Gode, da ema hahawane dogolegele iasu imunu. Nowa da dafawane sia: musa: dawa: sea, e da Dafawane Hamosu Gode, amo Ea Dioba: le, dafawaneyale sia: mu. Musa: bidi hamosu da bu hame ba: mu, gogolei dagoi ba: mu.”
Ẹnikẹ́ni tí ó bá gbàdúrà ìbùkún ní ilẹ̀ náà yóò ṣe é nípasẹ̀ Ọlọ́run òtítọ́; Ẹni tí ó bá búra ní ilẹ̀ náà yóò búra nípasẹ̀ Ọlọ́run òtítọ́. Nítorí ìyọnu àtijọ́ yóò di ìgbàgbé yóò sì fi ara sin kúrò lójú mi.
17 Hina Gode da amane sia: sa, “Na da osobo bagade gaheabolo amola mu gaheabolo hahamomu. Musa: hamoi hou da gogolei dagoi ba: mu.
“Kíyèsi i, Èmi yóò dá àwọn ọ̀run tuntun àti ayé tuntun. A kì yóò rántí ohun àtẹ̀yìnwá mọ́, tàbí kí wọn wá sí ọkàn.
18 Na gaheabolo liligi hamomuba: le, dilia eso huluane hahawane bagade ba: mu da defea. Gaheabolo Yelusaleme Na da hamomu amo ganodini da hahawane hou fawane ba: mu amola ea fi dunu da hahawane bagade ganumu.
Ṣùgbọ́n ẹ yọ̀ kí inú yín dùn títí láé nínú ohun tí èmi yóò dá, nítorí èmi yóò dá Jerusalẹmu láti jẹ́ ohun ìdùnnú àti àwọn ènìyàn rẹ̀, ohun ayọ̀.
19 Na Nisu da Yelusaleme amola ea fi dunu ba: sea, hahawane ba: mu. Amo ganodini da disu amola fidima: ne wele sia: su bu hame ba: mu.
Èmi yóò ṣe àjọyọ̀ lórí Jerusalẹmu n ó sì ní inú dídùn nínú àwọn ènìyàn mi; ariwo ẹkún àti igbe ni a kì yóò gbọ́ nínú rẹ̀ mọ́.
20 Mano ilia dudubusu esoga da bu hame bogomu amola dunu huluane ilia ode ilegei defele esalumu. Nowa da ode 100 esalebe ba: sea, amo dunu da da: i hame, ayeligi fawane ilia da sia: mu. Be nowa da ode 100 amoga hame doaga: sea, e da Na se iasu lai dagoi, ilia da dawa: mu.
“Títí láé a kì yóò gbọ́ nínú rẹ̀ ọmọ ọwọ́ tí yóò gbé fún ọjọ́ díẹ̀, tàbí àgbàlagbà tí kì yóò lo ọjọ́ ayé rẹ̀ tán; ẹni tí ó bá kú ní ìwọ̀n ọgọ́rùn-ún ni a ó pè ní ọ̀dọ́mọdé; ẹni tí kò ba le pé ọgọ́rùn-ún kan ni a ó pè ní ẹni ìfibú.
Wọn yó ò kọ́ ilé, wọn yóò sì gbé nínú wọn wọn yóò gbin ọgbà àjàrà, wọn yóò sì jẹ èso wọn.
22 Dunu da ilia diasu gaguli, amo ganodini eno dunu hame be ilisu da esalumu. Ilia da waini efe sagale, eno dunu ilima hame imunu be ilisu fawane da amo waini hano manu. Na dunu da ifa agoane, ode bagohame esalumu. Ilia da hawa: hamobeba: le, liligi lasea, ilisu da amo liligi hahawane gagumu.
Wọn kì yóò kọ́ ilé fún ẹlòmíràn láti gbé, tàbí kí wọn gbìn fún ẹlòmíràn láti jẹ. Nítorí gẹ́gẹ́ bí ọjọ́ orí igi kan, bẹ́ẹ̀ ní ọjọ́ àwọn ènìyàn mi yóò rí; àwọn àyànfẹ́ mi yóò jẹ iṣẹ́ ọwọ́ wọn fún ìgbà pípẹ́.
23 Ilia hawa: hamosu da hahawane hehenane, didili hamoi dagoi ba: mu. Amola ilia mano da gugunufinisisu hame ba: mu. Na da mae fisili, eso huluane iligaga fi amo hahawane fidilalumu.
Wọn kì yóò ṣe iṣẹ́ lásán, wọn kí yóò bímọ fún wàhálà; nítorí wọn yóò jẹ́ àwọn ènìyàn ti Olúwa bùkún fún, àwọn àti àwọn ìrandíran wọn pẹ̀lú wọn.
24 Ilia da Nama sia: ne gadolala, sia: ne gadosu da hame dagosea, Na da hedolowane ilia sia: ne: gadosu adole ba: i liligi ilima imunu.
Kí wọn tó pè, èmi yóò dáhùn; nígbà tí wọ́n sì ń sọ̀rọ̀ lọ́wọ́, èmi yóò gbọ́.
25 Wufi wa: me amola sibi mano da gilisili ha: i manu. Laione wa: me da bulamagau defele gisi manu amola gasonasu sania da gasonasea, dunu da bu hame bogomu. Na sema agolo Saione, amo ganodini da wadela: i liligi o wadela: lesisu liligi hamedafa ba: mu.”
Ìkookò àti ọ̀dọ́-àgùntàn yóò jẹun pọ̀, kìnnìún yóò sì jẹ koríko gẹ́gẹ́ bí akọ màlúù, ṣùgbọ́n erùpẹ̀ ni yóò jẹ́ oúnjẹ ejò. Wọn kì yóò pa ni lára tàbí pa ni run ní gbogbo òkè mímọ́ mi,” ni Olúwa wí.

< Aisaia 65 >