< Aisaia 6 >

1 Ode amoga hina bagade Asaia da bogoi, na da Hina Gode Ea Fisu amoga fila heda: lebe ba: i. E da gado gaguia gadoi amola Ea abula feafeai da Debolo Diasu nabai dagoi.
Ní ọdún tí ọba Ussiah kú, mo rí Olúwa tí ó jókòó lórí ìtẹ́ tí ó ga tí a gbé sókè, ìṣẹ́tí aṣọ ìgúnwà rẹ̀ sì kún inú tẹmpili.
2 Esalebe liligi lalu agoane ba: su, ilia dio da “Selafimi” da Hina Gode Ea esalebe sisiga: le ba: i. Ilia afae afae da ougia gafeyale gala. Ougia aduna amoga ilia da ilia odagi dedeboi. Ougia aduna eno amoga ilia emo dedeboi amola ougia aduna eno amoga ilia da hagili asi.
Àwọn Serafu wà ní òkè rẹ̀, ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn ní ìyẹ́ mẹ́fà, wọ́n fi ìyẹ́ méjì bo ojú wọn, wọ́n fi méjì bo ẹsẹ̀ wọn, wọ́n sí ń fi méjì fò.
3 Ilia da enoma enoma amane wele sia: su, “Hadigi! Hadigi! Hadigi! Hina Gode Bagadedafa da Hadigi. Osobo bagade da Ea Hadigi Hou Ida: iwane Gala amoga nabai gala.”
Wọ́n sì ń kọ sí ara wọn wí pé, “Mímọ́, mímọ́, mímọ́ ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun gbogbo ayé kún fún ògo rẹ̀.”
4 Ilia sia: nababeba: le, logo holei ifa la: ididili amola la: ididili da ugugui amola gagili fea da ugugui. Amola Debolo diasu da mobi amoga nabai ba: i.
Nípa ìró ohùn un wọn, òpó ìlẹ̀kùn àti gbogbo ògiri ilé náà sì mì tìtì, gbogbo inú tẹmpili sì kún fún èéfín.
5 Na da amane sia: i, “Na da bogoma: ne se nabi! Na da wadela: lesi dagoi! Bai na lafi da ledo bagade. Na da wadela: i sia: bagade sia: sa amola na fi amo ganodini na da esala, ilia amola da wadela: i sia: bagade sia: daha. Amola na da na siga, Hina Gode Bagadedafa ba: i dagoi.
Mo kígbe pé, “Ègbé ni fún mi! Mo ti gbé!” Nítorí mo jẹ́ ènìyàn aláìmọ́ ètè, mo sì ń gbé láàrín àwọn ènìyàn aláìmọ́ ètè, ojú mi sì ti rí ọba, Olúwa àwọn ọmọ-ogun jùlọ.
6 Amalalu, “Selafimi” afae da dida amoga nenanebe laluso oloda amoga lale, gaguli, nama hagili misi.
Nígbà náà ni ọ̀kan nínú àwọn Serafu wọ̀nyí fò wá sí ọ̀dọ̀ mi pẹ̀lú ẹ̀yín iná ní ọwọ́ rẹ̀, èyí tí ó ti fi ẹ̀mú mú ní orí pẹpẹ.
7 E da amo laluso amoga na lafi gadofo digili ba: i. Amola e da nama amane sia: i, “Amo laluso da dia lafi gadofo digili ba: i dagoi. Wali dia wadela: i hou hamoiba: le gogosiasu da fadegai dagoi, amola Gode da dia wadela: i hou gogolema: ne olofoi dagoi.”
Èyí ni ó fi kàn mí ní ẹnu tí ó sì wí pé, “Wò ó, èyí ti kan ètè rẹ; a ti mú ẹ̀bi rẹ kúrò, a sì ti wẹ ẹ̀ṣẹ̀ rẹ nù.”
8 Amalalu, na da Hina Gode Ea sia: nabi, amane, “Na da nowa asunasima: bela: ? Nowa da Ninia sia: na ahoasu dunu hamoma: bela: ?” Na da bu adole i, “Na da masunu! Dia na asunasima!”
Nígbà náà ni mo sì gbọ́ ohùn Olúwa wí pé, “Ta ni èmi yóò rán? Ta ni yóò sì lọ fún wa?” Nígbà náà ni èmi sì wí pé, “Èmi nìyí, rán mi!”
9 Amaiba: le, E da nama masa: ne amola dunu fi ilima amo sia: olelema: ne sia: i, “Dilia da gega nabimu, be dawa: hame lamu. Dilia siga ba: lalumu, be hou hamedafa dawa: mu.”
Òun sì wí pé, “Tọ àwọn ènìyàn yìí lọ kí o sì wí fún wọn pé, “‘Ní gbígbọ́ ẹ̀yin yóò gbọ́, kì yóò sì yé e yín; ní rí rí ẹ̀yin yóò ri, ẹ̀yin kì yóò mọ òye.’
10 Amalalu, E da nama amane sia: i, “Di da amo dunu ilia dogo ga: nasima, amola ilia ge ga: ma, amola ilia si dofoma. Ilia da siga ba: sa: besa: le, amola gega nabasa: besa: le, amola ilia dogoga dawa: sa: besa: le, amola ilia Nama sinidigili bu uhisa: besa: le, agoane hamoma.”
Mú kí àyà àwọn ènìyàn wọ̀nyí yigbì, mú kí etí wọn kí ó wúwo, kí o sì dìwọ́n ní ojú. Kí wọn kí ó má ba fi ojú wọn ríran, kí wọn kí ó má ba fi etí wọn gbọ́rọ̀, kí òye kí ó má ba yé ọkàn wọn, kí wọn kí ó má ba yípadà kí a má ba mú wọn ní ara dá.”
11 Amalalu, na da amane sia: i, “Hina Gode! Eso habodayane amo hou da ba: ma: bela: ?” Amola E bu adole i, “Amo hou da gebe hamonanea, moilai huluane da wadela: lesi dagoi amola dunu afae esalebe hame ba: mu. Diasu huluane da dunu hame, amola soge huluane da wadela: lesi dagoi ba: mu.
Nígbà náà ni mo wí pé, “Báwo ni yóò ti pẹ́ tó Olúwa?” Òun sì dáhùn pé: “Títí àwọn ìlú ńlá yóò fi dahoro, láìsí olùgbé nínú rẹ̀ mọ́, títí tí àwọn ilé yóò fi wà láìsí ènìyàn, títí tí ilẹ̀ yóò fi dahoro pátápátá.
12 Amo hou da gebe hamonanea, Hina Gode da dunu huluane mugululi asili huluane soge sedaga asunasi dagoi ba: mu. Amola soge da fisi dagoi ba: mu.
Títí tí Olúwa yóò fi rán gbogbo wọn jìnnà réré tí ilẹ̀ náà sì di ìkọ̀sílẹ̀ pátápátá.
13 Amola dunu nabuane ganodini, dunu afae fawane da Isala: ili soge ganodini esalebe ba: mu. Be soge da bu wadela: lesi dagoi ba: mu. Be “ouge” ifa abasea, ifadou da ea bai agoane dialebe ba: sa. Amo defele, Na hadigi hawa: da ifa bai agoane, Isala: ili soge ganodini dialumu. (Ifa dou ea dawa: loma: ne da gaheabolo musu amo Gode Ea fi da hamomu galu.)
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ìdámẹ́wàá ṣẹ́kù lórí ilẹ̀ náà, yóò sì tún pàpà padà di rírun. Ṣùgbọ́n gẹ́gẹ́ bí igi tẹrẹbinti àti igi óákù, ti í fi kùkùté sílẹ̀ nígbà tí a bá gé wọn lulẹ̀, bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni irúgbìn mímọ́ náà yóò di kùkùté ní ilẹ̀ náà.”

< Aisaia 6 >