< Aisaia 45 >

1 Hina Gode da Sailase hina bagade hamoma: ne ilegei dagoi. E da Sailase amo fifi asi gala ilima hasanasima: ne ilegei dagoi. Sailase da hina bagade eno ilia gasa wadela: lesimu. Hina Gode da Sailase golili sa: ima: ne, moilai bai bagade ilia ga: su doasimu. Hina Gode da Sailasema amane sia: sa,
“Èyí ni ohun tí Olúwa sọ fún ẹni òróró rẹ̀, sí Kirusi, ọwọ́ ọ̀tún ẹni tí mo dì mú láti dojú àwọn orílẹ̀-èdè bolẹ̀ níwájú rẹ̀ àti láti gba ohun ìjà àwọn ọba lọ́wọ́ wọn, láti ṣí àwọn ìlẹ̀kùn níwájú rẹ̀ tí ó fi jẹ́ pé a kì yóò ti àwọn ẹnu-ọ̀nà.
2 “Na Nisu da dia logo fodomu. Na da goumi amola agolo mugululi, umi hamomu. Na da “balase” logo ga: su mugulumu amola ouli galiamo agoai ga: su liligi goudamu.
Èmi yóò lọ síwájú rẹ, Èmi ó sì tẹ́ àwọn òkè ńlá pẹrẹsẹ Èmi yóò fọ gbogbo ẹnu-ọ̀nà idẹ èmi ó sì gé ọ̀pá irin.
3 Na da liligi noga: idafa gasi agoai sogebi ganodini wamolegei, amo dima imunu. Amasea, Na da Hina Gode amo di da dawa: mu. Amola Isala: ili Godedafa da dia dio dawa: beba: le, dima wele sia: i dagoi.
Èmi yóò sì fún ọ ní àwọn ọrọ̀ ibi òkùnkùn, ọrọ̀ tí a kó pamọ́ sí àwọn ibi tí ó fi ara sin, tó bẹ́ẹ̀ tí ìwọ yóò fi mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, ẹni tí ó pè ọ́ pẹ̀lú orúkọ rẹ.
4 Di da Na hawa: hamosu dunu amo Isala: ili (Na ilegei dunu fi) amo fidima: ne, Na da di ilegei dagoi. Di da Na hame dawa: , be eno dunu ilia da dima nodoma: ne, Na da ilegei dagoi.
Nítorí Jakọbu ìránṣẹ́ mi àti Israẹli ẹni tí mo yàn, Mo pè ọ́ pẹ̀lú orúkọ rẹ, mo sì gbé oyè kan kà ọ́ lórí bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ìwọ kò gbà mí.
5 Na da Hina God! Eno ‘gode’ da hame gala. Dia da Na hame dawa: , be Na da dia hawa: hamomu defele, gasa dima imunu.
Èmi ni Olúwa, àti pé kò sí ẹlòmíràn; yàtọ̀ sí èmi kò sí ọlọ́run kan, Èmi yóò fún ọ ní okun, bí o kò tilẹ̀ tí ì gbà mí,
6 Dunu huluanedafa, osobo bagade bega: asili eno bega: doaga: sa, amo huluane ilia da Na da Hina Gode amola eno ‘gode’ da hame gala amo dawa: ma: ne, Na da agoane hamomu.
tí o fi jẹ́ pé láti ìlà-oòrùn títí dé ibi ìwọ̀ rẹ̀ kí ènìyàn le mọ̀, kò sí ẹnìkan lẹ́yìn mi. Èmi ni Olúwa, lẹ́yìn mi kò sí ẹlòmíràn mọ́.
7 Na da hadigi amola gasi hahamosa. Na da hahawane hou amola gugunufinisisu hou gaguli maha. Na, Hina Gode, da amo hou huluane hamonana.
Mo dá ìmọ́lẹ̀, mo sì dá òkùnkùn, Mo mú àlàáfíà wá, Mo sì dá àjálù; Èmi Olúwa ni ó ṣe nǹkan wọ̀nyí.
8 Na da muagado mabe gibu defele hasalasu hou iasimu. Fedege agoane, osobo bagade da ea lafi dagale, amo hou da: gimu. Amasea, sogea fudagala: su defele, hahawane dogolegele ahoasu hou amola moloidafa hou da osobo bagadega dialebe ba: mu. Na, Hina Gode da amo hou misa: ne, hamomu.
“Ìwọ ọ̀run lókè rọ òjò òdodo sílẹ̀; jẹ́ kí àwọsánmọ̀ kí ó rọ̀ ọ́ sílẹ̀. Jẹ́ kí ilẹ̀ kí ó yanu gbagada, jẹ́ kí ìgbàlà kí ó dìde sókè, jẹ́ kí òdodo kí ó dàgbà pẹ̀lú rẹ̀; Èmi Olúwa ni ó ti dá a.
9 Laga osoboga hamoi ofodo, amo ofodo eno huluane defele da ea hahamosu dunuma sia: ga gegemu da defeala: ? Laga osobo da ofodo hahamosu dunuma ea hamobe adole ba: sala: ? Laga osoboga hamoi ofodo da e hahamosu dunu amoma, “Di da hahamosu hou hame dawa: !” amo sia: sia: sala: ?
“Ègbé ni fún ènìyàn tí ó ń bá Ẹlẹ́dàá rẹ̀ jà, ẹni tí òun jẹ́ àpáàdì kan láàrín àwọn àpáàdì tí ó wà lórí ilẹ̀. Ǹjẹ́ amọ̀ lè sọ fún amọ̀kòkò, pé: ‘Kí ni ohun tí ò ń ṣe?’ Ǹjẹ́ iṣẹ́ rẹ lè sọ pé, ‘Òun kò ní ọwọ́?’ (questioned)
10 Nowa da ea ada amola ame elama, “Ali da abuliba: le na agoane hahamobela: ?” Elama agoane adole ba: sala: ?
Ègbé ni fún ẹni tí ó sọ fún baba rẹ̀ pé, ‘Kí ni o bí?’ tàbí sí ìyá rẹ̀, ‘Kí ni ìwọ ti bí?’
11 Hina Gode, Isala: ili ea Hadigi Gode da dunu ilia hobea misunu hou hahamonana, amola e da amane sia: sa, “Dilia da Na manolali ilima Na hamosu, amo da noga: i hame sia: mu da defea hame galebe. Dilia da Nama, “agoane hamoma!” sia: mu da hamedei.
“Ohun tí Olúwa wí nìyìí, Ẹni Mímọ́ Israẹli, àti Ẹlẹ́dàá rẹ̀. Nípa ohun tí ó ń bọ̀, ǹjẹ́ o ń bi mí léèrè nípa àwọn ọmọ mi, tàbí kí o pàṣẹ fún mi nípa iṣẹ́ ọwọ́ mi bí?
12 Na fawane da osobo bagade amo ganodini dunu fi esaloma: ne, hahamoi dagoi. Na gasaga Na da mu fadegale gai. Na da eso amola oubi amola gasumuni ouligisa.
Èmi ni ẹni tí ó dá ilẹ̀ ayé tí ó sì da ọmọ ènìyàn sórí i rẹ̀. Ọwọ́ mi ni ó ti ta àwọn ọ̀run; mo sì kó àwọn àgbájọ ìràwọ̀ rẹ̀ síta.
13 Na Nisu da Sailasema Na hanai hamoma: ne, amola hou huluane moloma: ne, sia: i dagoi. Ea logo ahoabe huluane, Na da molomu. E da Na moilai bai bagade Yelusaleme amo bu gagumu. Amola Sailase da Na fi dunu (amo da wali udigili hawa: hamonana, ) amo ilia halegale masa: ne logo doasimu. Dunu eno da amo hamoma: ne, ema bidi o hano suligili hame iasu.” Hina Gode Bagadedafa da sia: i dagoi.
Èmi yóò gbé Kirusi sókè nínú òdodo mi. Èmi yóò mú kí gbogbo ọ̀nà rẹ̀ kí ó tọ́. Òun yóò tún ìlú mi kọ́ yóò sì tú àwọn àtìpó mi sílẹ̀, ṣùgbọ́n kì í ṣe fún owó tàbí ẹ̀bùn kan, ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.”
14 Hina Gode da Isala: ili fi ilima amane sia: sa, “Dilia da Idibidi amola Sudane ilia gagui liligi huluane lamu. Amola Siba dunu sedade da dilia udigili hawa: hamosu dunu ba: mu. Ilia da sia: ine amoga la: gili, dilima fa: no bobogemu. Ilia da dilima beguduli, amane sia: mu, ‘Gode da dili esala - Hi fawane da Godedafa.
Ohun tí Olúwa wí nìyìí: “Àwọn èròjà ilẹ̀ Ejibiti àti àwọn ọjà ilẹ̀ Kuṣi, àti àwọn Sabeani— wọn yóò wá sọ́dọ̀ rẹ wọn yóò sì jẹ́ tìrẹ; wọn yóò máa wọ́ tẹ̀lé ọ lẹ́yìn, wọn yóò máa wá lọ́wọ̀ọ̀wọ́. Wọn yóò máa foríbalẹ̀ níwájú rẹ̀, wọn yóò sì máa bẹ̀bẹ̀ níwájú rẹ pé, ‘Nítòótọ́ Ọlọ́run wà pẹ̀lú rẹ kò sì ṣí ẹlòmíràn; kò sí ọlọ́run mìíràn.’”
15 Isala: ili fi ilia Gode, ilia Gaga: su dunu, E da hou agoane hamosa. E da wamoaligisa.
Nítòótọ́ ìwọ jẹ́ Ọlọ́run tí ó fi ara rẹ̀ pamọ́, Ìwọ Ọlọ́run àti Olùgbàlà Israẹli,
16 Dunu amo da ogogosu ‘gode’ hahamobe da gogosiasu ba: mu. Dunu eno da ili higamu.
Gbogbo àwọn tí ó ń gbẹ́ ère ni ojú yóò tì wọn yóò sì kan àbùkù; gbogbo wọn ni yóò bọ́ sínú àbùkù papọ̀.
17 Be Hina God da Isala: ili dunu gaga: i dagoi. Ilia hasalasu hou da mae fisili dialalalumu. Amola ilia da gogosiasu hamedafa ba: mu.’”
Ṣùgbọ́n Israẹli ni a ó gbàlà láti ọwọ́ Olúwa pẹ̀lú ìgbàlà ayérayé; a kì yóò kàn yín lábùkù tàbí kí a dójútì yín, títí ayé àìnípẹ̀kun.
18 Hina Gode da mu hahamoi. Hi fawane da Godedafa. E da osobo bagade hahamoi-E da amo mae muguluma: ne, gasawane hamoi. E da soge wadela: i hame be noga: idafa hamoi, Amola dunu da hahawane ganodini esaloma: ne, hamoi dagoi. Hi fawane da amane sia: sa, “Na da Hina Gode. Eno ‘gode’ da hamedafa.
Nítorí èyí ni ohun tí Olúwa wí, ẹni tí ó dá àwọn ọ̀run, Òun ni Ọlọ́run; ẹni tí ó mọ tí ó sì dá ayé, Òun ló ṣe é; Òun kò dá a láti wà lófo, ṣùgbọ́n ó ṣe é kí a lè máa gbé ibẹ̀, Òun wí pé: “Èmi ni Olúwa, kò sì ṣí ẹlòmíràn.
19 Na da wamowane hame sia: i. Amola Na hanai hame wamolegei. Na da Isala: ili dunu ilia gugunufinisi soge amo ganodini Na hogomu, hame sia: i. Na da Hina Gode amola Na sia: da dafawane. Na da moloidafa hou olelesa.
Èmi kò sọ̀rọ̀ níbi tí ó fi ara sin, láti ibìkan ní ilẹ̀ òkùnkùn, Èmi kò tí ì sọ fún àwọn ìran Jakọbu pé, ‘Ẹ wá mi lórí asán.’ Èmi Olúwa sọ òtítọ́, Mo sì sọ èyí tí ó tọ̀nà.
20 Hina Gode da amane sia: sa, “Dilia fifi asi gala huluane! Gilisima! Nowa da Ba: bilone ea dafai mae bogole esala. Dilia fofada: musa: misa! Dunu ilia da ifaga hamoi ‘gode’ liligi gaguli, mogodigili ahoa amola amo ‘gode’ liligi ilima sia: ne gadosa, amo dunu ilia asigi dawa: su da hamedeidafa.
“Ẹ kó ara yín jọ kí ẹ sì wá; ẹ kórajọ, ẹ̀yin ìsáǹsá láti àwọn orílẹ̀-èdè wá. Aláìmọ̀kan ni àwọn tí ó ń ru ère igi káàkiri, tí wọ́n gbàdúrà sí àwọn òrìṣà tí kò le gba ni.
21 Dilia sia: sia: musa: fofada: su diasuga misa. Dilia da Nama fofada: sea, dunu enoenoi gilisili sia: sa: ima. Nowa da musa: hemonega hobea misunu hou amo dawa: beba: le, olelebela: ? Na, Ni fawane, Hina Gode Ea fi Gaga: su dunu, da amo hou ba: la: lusu.
Jẹ́ kí a mọ ohun tí yóò ṣẹlẹ̀, fihàn wá, jẹ́ kí wọn jọ dámọ̀ràn papọ̀. Ta ló ti sọ èyí lọ́jọ́ tí o ti pẹ́, ta ló ti wí èyí láti àtètèkọ́ṣe? Kì í ha á ṣe Èmi, Olúwa? Àti pé kò sí Ọlọ́run mìíràn lẹ́yìn mi, Ọlọ́run olódodo àti olùgbàlà; kò sí ẹlòmíràn àfi èmi.
22 Osobo bagade fifi asi gala dunu huluane! Nama sinidigima! Amasea, dilia Na Gaga: su ba: mu. Ni fawane da Godedafa, eno hame.
“Yípadà sí mi kí a sì gbà ọ́ là, ẹ̀yin ìpẹ̀kun ilẹ̀ ayé; nítorí Èmi ni Ọlọ́run kò sì ṣí ẹlòmíràn.
23 Na ilegei sia: da dafawane, amola Na da amo afedenemu hame dawa: Na da Na hou huluane amoga Na ilegei sia: i defele hamoma: ne sia: sa. Dunu huluanedafa da Nama misini, muguni bugili, Na mae yolesima: ne ilia da sia: mu.
Nípa èmi tìkára mi ni mo ti búra, ẹnu mi ni ó ti sọ ọ́ pẹ̀lú gbogbo ipá mi, ọ̀rọ̀ náà tí a kì yóò lè parẹ́. Níwájú mi ni gbogbo orúnkún yóò wólẹ̀; nípa mi ni gbogbo ahọ́n yóò búra.
24 Na hamobeba: le fawane, hasalasu hou amola gasa bagade hou da ba: mu, amo ilia da sia: mu. Be huluane da Na higasea da gogosiamu.
Wọn yóò sọ ní ti èmi, ‘Nínú Olúwa nìkan ni òdodo àti agbára wà.’” Gbogbo àwọn tí ó ti bínú sí; yóò wá sọ́dọ̀ rẹ̀ a ó sì dójútì wọn.
25 Na, Hina Gode, da Ya: igobe egaga fi huluane gaga: mu. Amasea, ilia da Nama nodosu imunu.”
Ṣùgbọ́n nínú Olúwa gbogbo àwọn ìran Israẹli ni a ó rí ní òdodo, a o sì gbé wọn ga.

< Aisaia 45 >