< Aisaia 41 >

1 Gode da amane sia: sa, “Dilia sedaga soge fi! Ouiya: ma! Na sia: nabima! Dilia fofada: su diasu ganodini sia: ma: ne, dilia fofada: su sia: momagema. Dilia da bu sia: mu logo ba: mu. Dilia amola Na da moloidafa hou dawa: ma: ne, fofada: mu da defea.
“Ẹ dákẹ́ jẹ́ẹ́ níwájú mi ẹ̀yin erékùṣù! Jẹ́ kí àwọn orílẹ̀-èdè tún agbára wọn ṣe! Jẹ́ kí wọn wá síwájú kí wọn sọ̀rọ̀, jẹ́ kí a pàdé pọ̀ ní ibi ìdájọ́.
2 Nowa da gusugoe amoga hasalasu dunu oule misibela: ? Nowa da soge huluane e da asi amoga ema hasalasu hou iabela: ? E da hina bagade amola fifi asi gala ilima hasanasima: ne, nowa da ema hasalasu hou iabela: ? Ea gobihei amoga e da fifi asi gala dunu osobo su defele wadela: sa. Ea dadi amoga gala: beba: le, ilia da gisi da foga afafasu defele afafasa.
“Ta ni ó ti ru ẹnìkan sókè láti ìlà-oòrùn wá, tí ó pè é ní olódodo sí iṣẹ́ tirẹ̀? Ó gbé àwọn orílẹ̀-èdè lé e lọ́wọ́ ó sì ṣẹ́gun àwọn ọba níwájú rẹ̀. Ó sọ wọ́n di erùpẹ̀ pẹ̀lú idà rẹ̀, láti kù ú ní ìyàngbò pẹ̀lú ọrun rẹ̀.
3 E da ilia hobeasu amoma fa: no bobogesa amola mogodigili ahoa. E da hehenabeba: le, gadenenewane hagili ahoa.
Ó ń lépa wọn ó sì ń kọjá ní àlàáfíà, ní ojú ọ̀nà tí ẹsẹ̀ rẹ̀ kò rìn rí.
4 Nowa da amo hou misa: ne hamobela: ? Nowa da osobo bagade hou huluane ouligibala: ? Na, Hina Gode, da osobo bagade hemosu eso amoga esalebe ba: i, amola Na, Hina Gode da osobo bagade wadela: mu eso amoga esalebe ba: mu.
Ta ni ó ti ṣe èyí tí ó sì ti jẹ́ kí ó wáyé, tí ó ti pe ìran-ìran láti àtètèkọ́ṣe? Èmi Olúwa pẹ̀lú ẹni kìn-ín-ní wọn àti ẹni tí ó gbẹ̀yìn, Èmi náà ni.”
5 Soge sedaga fi dunu da Na hamobe ba: beba: le, bagadewane beda: beba: le, yagugusa. Amaiba: le, ilia huluane da gilisili, maha.
Àwọn erékùṣù ti rí i wọ́n bẹ̀rù; ìpẹ̀kun ilẹ̀ ayé wárìrì. Wọ́n súnmọ́ tòsí wọ́n sì wá síwájú;
6 Liligi hahamosu dunu ilia enoenoi fidisa amola dogo denesisa.
èkínní ran èkejì lọ́wọ́ ó sì sọ fún arákùnrin rẹ̀ pé, “Jẹ́ alágbára!”
7 Ifa hahamosu dunu da gouli hahamosu dunuma, “Dia da noga: le hamoi,” sia: sa. Dunu amo da ‘gode’ agoaila enemema: ne hamosu da dunu amo da ‘gode’ agoaila gafesiga dabagala: sa amoma dogo denesima: ne sia: sa. Ilia da amane sia: sa, “Gouli madelagisu da defea.” Amasea, ilia da amo loboga hamoi ‘gode’ ea sogebi dialoma: ne, amo gafesiga dabagala: sa.
Oníṣọ̀nà gba alágbẹ̀dẹ wúrà níyànjú, àti ẹni tí ó fi òòlù dán mú òun lọ́kàn le, àní ẹni tí ó ń lu owú. Ó sọ nípa àjópọ̀ náà pé, “Ó dára.” Ó fi ìṣó kan ère náà mọ́lẹ̀ kí ó má ba à wó lulẹ̀.
8 Be di, Isala: ili, Na hawa: hamosu dunu. Dilia da Na fi dunu Na da ilegei dagoi. Dilia da Na dogolegei A: ibalaha: me, amo egaga fi esala.
“Ṣùgbọ́n ìwọ, ìwọ Israẹli, ìránṣẹ́ mi, Jakọbu, ẹni tí mo ti yàn, ẹ̀yin ìran Abrahamu, ọ̀rẹ́ mi,
9 Na da dili osobo bagade bega: bega: amoga dilima wele sia: nanu, oule misini, gilisi. Na da dilima amane sia: i, “Dilia da Na hawa: hamosu dunu. Na da dili hame higasu, be dili Na fi hamoma: ne ilegei dagoi.
mo mú ọ láti ìpẹ̀kun ilẹ̀ ayé, láti kọ̀rọ̀ rẹ̀ tí ó jìnnà jùlọ ni mo ti pè ọ́. Èmi wí pé, ‘Ìwọ ni ìránṣẹ́ mi’; Èmi ti yàn ọ́ bẹ́ẹ̀ ni èmi kò sì tí ì kọ̀ ọ́ sílẹ̀.
10 Mae beda: ma! Ani esala. Na da dilia Gode! Liligi huluane amoma mae beda: ma. Na da dilima gasa imunu amola dili fidimu. Na da dili gaga: mu.
Nítorí náà má bẹ̀rù, nítorí èmi wà pẹ̀lú rẹ; má ṣe jẹ́ kí àyà kí ó fò ọ́, nítorí èmi ni Ọlọ́run rẹ. Èmi yóò fún ọ lókun èmi ó sì ràn ọ́ lọ́wọ́. Èmi ó gbé ọ ró pẹ̀lú ọwọ́ ọ̀tún òdodo mi.
11 Dilia da nowa da dilima ougi galea, ilima hasanasibiba: le, ilia da gogosiamu. Nowa da dilima gegesea da bogole,
“Gbogbo àwọn tí ó bínú sí ọ ni ojú yóò tì, tí wọn yóò sì di ẹlẹ́yà; àwọn tó ń bá ọ jà yóò dàbí asán, wọn yóò ṣègbé.
12 osobo bagadega bu hame ba: ma: ne alalolesimu.
Bó tilẹ̀ jẹ́ pé ìwọ yóò wá àwọn ọ̀tá rẹ, ìwọ kì yóò rí wọn. Gbogbo àwọn tí ó gbóguntì ọ́ yóò dàbí ohun tí kò sí.
13 Na da Hina Gode amo dilia Gode. Na da dilima gasa iaha amola dilima amane sia: sa, “Mae beda: ma! Na da dili fidimu.”
Nítorí Èmi ni Olúwa Ọlọ́run rẹ, tí ó di ọwọ́ ọ̀tún rẹ mú tí ó sì sọ fún ọ pé, má ṣe bẹ̀rù; Èmi yóò ràn ọ́ lọ́wọ́.
14 Hina Gode da amane sia: sa, “Isala: ili fi! Dilia da fonobahadi fi amola gasa hame galebe. Be mae beda: ma! Na da dili fidimu. Na, Isala: ili fi ilia Hadigi Gode, Na da dilia gaga: su dunu esala.
Má ṣe bẹ̀rù, ìwọ Jakọbu kòkòrò, ìwọ Israẹli kékeré, nítorí Èmi fúnra mi yóò ràn ọ́ lọ́wọ́,” ni Olúwa wí, olùdáǹdè rẹ, Ẹni Mímọ́ ti Israẹli.
15 Na da dilia hou afadenene, widi fasu ifa agoane hamomu. Amoga sosu liligi gaheabolo amola agei dagoi agoane ba: mu. Amoga dilia da goumi amo fananu, wadela: lesimu. Dilia da agolo goudane, ilia da osobo su agoane ba: mu.
“Kíyèsi, Èmi yóò sọ ọ́ di òòlù ìpakà tuntun, tí ó mú ti eyín rẹ̀ mú, ìwọ yóò lu àwọn òkè ńlá, ìwọ yóò fọ́ wọn túútúú, a ó sì sọ òkè kékeré di ìyàngbò.
16 Dilia da amo goumi gadodi gasa: le gadosea, ilia da foga mini asi dagoi ba: mu, amola isula bobodobe amoga afafai dagoi ba: mu. Amasea, dilia da hahawane ba: mu. Bai Na da dilia Gode esala. Dilia da Na, Isala: ili fi ilia Hadigi Gode, Nama nodomu.
Ìwọ yóò fẹ́ wọn, afẹ́fẹ́ yóò sì gbá wọn mú, àti ẹ̀fúùfù yóò sì fẹ́ wọn dànù. Ṣùgbọ́n ìwọ yóò yọ̀ nínú Olúwa ìwọ yóò sì ṣògo nínú Ẹni Mímọ́ ti Israẹli.
17 Na fi dunu da hano hanaiba: le, hano hogosea, ilia asogoa da hafoga: i galea, Na, Hina Gode da ilia sia: ne gadosu amoma bu adole imunu. Na, Isala: ili fi ilia Gode, da ili hamedafa yolesimu.
“Àwọn tálákà àti aláìní wá omi, ṣùgbọ́n kò sí; ahọ́n wọn gbẹ fún òǹgbẹ. Ṣùgbọ́n Èmi Olúwa yóò dá wọn lóhùn; Èmi, Ọlọ́run Israẹli, kì yóò kọ̀ wọ́n sílẹ̀.
18 Na da hafog: ai agolo sogega, hano yogosa: ima: ne hamomu. Amola hafoga: i soge ganodini, gu hano hamomu. Na da hafoga: i soge afadenene, bu hano wayabo hamomu. Amola hafoga: i soge gu hano bubuga: su hamomu.
Èmi yóò mú kí odò kí ó sàn ní ibi gíga àti orísun omi ní àárín àfonífojì. Èmi yóò sọ aṣálẹ̀ di adágún omi, àti ilẹ̀ tí ó gbẹ gidigidi di orísun omi.
19 Dolo ifa amola “aga: isia” ifa amola “medili” ifa da hafoga: i soge ganodini heda: lalebe ba: mu. “Baine” ifa amola “yuniba” ifa amola “saibalase” ifa da hafoga: i sogega heda: mu.
Èmi yóò fi sínú aṣálẹ̀ igi kedari àti kasia, maritili àti olifi. Èmi yóò gbin junifa sí inú aginjù, igi firi àti sípírẹ́ṣì papọ̀
20 Dunu da amo hou ba: beba: le, ilia da Na, Hina Gode, da amo hou hamoi dagoi, dawa: mu. Ilia da Isala: ili fi ilia Hadigi Gode da amo hou hamoi dagoi ba: mu.” Hina Gode da Ogogosu ‘gode’ liligi ilima Fofada: sa
tó bẹ́ẹ̀ tí àwọn ènìyàn yóò fi rí i tí wọn yóò sì fi mọ̀, kí wọn ṣàkíyèsí kí ó sì yé wọn, pé ọwọ́ Olúwa ni ó ti ṣe èyí, àti pé, Ẹni Mímọ́ Israẹli ni ó ti dá èyí.
21 Hina Gode, Isala: ili ilia Hina bagade, da amane sia: sa, “Dilia fifi asi gala ‘gode’ liligi! Dilia hou gaga: ma: ne Nama fofada: ma! Sia: gasa bagade dilia hou gaga: ma: ne fofada: ma!
“Mú ẹjọ́ wá,” ni Olúwa wí. “Tẹ́ àwọn àwíjàre rẹ sílẹ̀,” ni ọba Jakọbu wí,
22 Misa! Amola hobea misunu hou ba: la: loma! Amo dilia sia: i liligi da doaga: sea, amo ea bai ninia dawa: ma: ne, ninima olelema. Musa: hamoi liligi amo fofada: su dunuma olelema amola amo ea dawa: loma: ne ninima olelema.
“Mú àwọn ère òrìṣà rẹ wọlé láti sọ fún wa ohun tí yóò ṣẹlẹ̀. Sọ fún wa ohun tí àwọn nǹkan àtijọ́ jẹ́, kí àwa lè ṣe àgbéyẹ̀wò wọn kí àwa sì mọ àbájáde wọn ní ìparí. Tàbí kí o sọ fún wa ohun tí ó ń bọ̀ wá,
23 Hobea misunu hou ninima olelema. Amasea, dilia da dafawane ‘gode’ esala, amo ninia da dawa: mu. Hou noga: iwane hamoma o ninia baligiliwane beda: ma: ne, wadela: lesisu liligi afae hamoma!
ẹ sọ fún wa ohun ti ọjọ́ iwájú mú dání kí àwa kí ó lè mọ̀ pé ọlọ́run ni yín. Ẹ ṣe nǹkan kan, ìbá à ṣe rere tàbí búburú, tó bẹ́ẹ̀ tí àyà yóò fi fò wá tí ẹ̀rù yóò sì fi kún inú wa.
24 Dili amola dilia hamonana huluane da hamedei liligi. Dunu amo da dilima nodone sia: ne gadosa, amo da gogosiasu wadela: idafa.
Ṣùgbọ́n ẹ̀yìn ko jásí nǹkan kan iṣẹ́ yín ni kò sì wúlò fún ohunkóhun; ẹni tí ó yàn yín jẹ́ ẹni ìríra.
25 Na da dunu amo da gusugoe esala, amo e ilegei dagoi. E da gagoe (north) amoga doagala: musa: misunu. E da ouligisu dunu amo ososa: gisa. Ilia da fafu agoai ba: sa, amola e da osoboga ofodo hamosu dunu Amo da fafu ososa: gisa agoane ba: sa.
“Èmi ti ru ẹnìkan sókè láti àríwá, òun sì ń bọ ẹnìkan láti ìlà-oòrùn tí ó pe orúkọ mi. Òun gun àwọn aláṣẹ mọ́lẹ̀ bí ẹni pé odò ni wọ́n, àfi bí ẹni pé amọ̀kòkò nì ti ń gún amọ̀.
26 Amo hou da doaga: ma: ne, dilia gilisisu ganodini, da nowa ba: la: lobala: ? Dilia da amo sia: sia: noba, ninia da dilia da dafawane sia: i dawa: la: loba. Be dilia huluane da hamedafa sia: i. Dunu afae da dilia amane sia: i, hamedafa nabi.
Ta ni ó sọ èyí láti ìbẹ̀rẹ̀ pẹ̀pẹ̀, tí àwa kò bá fi mọ̀, tàbí ṣáájú àkókò, tí àwa kò bá fi wí pé, ‘Òun sọ òtítọ́’? Ẹnikẹ́ni kò sọ nípa èyí, ẹnikẹ́ni kò sàsọtẹ́lẹ̀ rẹ̀, ẹnikẹ́ni kò gbọ́ ọ̀rọ̀ kan láti ọ̀dọ̀ rẹ̀.
27 Na, Hina Gode, da hidadea Saione fi ilima amo sia: olelei. Na da sia: ne iasu dunu Yelusaleme dunu fi hahawane sia: adoma: ne asunasi. Na da ilima amane adole iasi, ‘Dilia fi da ilia sogedafa amoga bu manebe.’
Èmi ni ẹni àkọ́kọ́ tí ó sọ fún Sioni pé, ‘Wò ó, àwọn nìyìí!’ Mo fún Jerusalẹmu ní ìránṣẹ́ ìrò ìròyìn ayọ̀ kan.
28 Be Na da ogogosu ‘gode’ liligi amo ganodini hogoi helebeba: le, moloi sia: su hamedafa ba: i. Ilia da Na adole ba: su amoma bu adole imunu gogolei galu.
Èmi wò, ṣùgbọ́n kò sí ẹnìkan— kò sí ẹnìkan nínú wọn tí ó lè mú ìmọ̀ràn wá, kò sí ẹnìkan tí ó lè dáhùn nígbà tí mo bi wọ́n.
29 Amo ‘gode’ liligi da hamedeidafa. Ilia da hawa: hamomu gogolesa. Ilia da gasa hamedafa.”
Kíyèsi i, irọ́ ni gbogbo wọn! Gbogbo ìṣe wọn jásí asán; àwọn ère wọn kò ṣé kò yà fún afẹ́fẹ́ àti dàrúdàpọ̀.

< Aisaia 41 >