< Aisaia 27 >

1 Amo esoga, fedege agoane, Hina Gode da E gobiheiga Lifaiada: ne (hanome waibulusa ahoabe agoane ahoa) amola hano wayabo bagade amo ganodini esalebe ohe fi ilima se imunu.
Ní ọjọ́ náà, Olúwa yóò fi idà rẹ̀ jẹ ni ní yà idà rẹ̀ a mú bí iná tí ó tóbi tí ó sì lágbára Lefitani ejò tí ń yọ̀ tẹ̀ẹ̀rẹ̀ n nì, Lefitani ejò tí ń lọ́ bìrìkìtì; Òun yóò sì pa ẹ̀mí búburú inú Òkun náà.
2 Amo esoga, Hina Gode da Ea hahawane waini efe sagai ea hou olelema: ne, amane sia: mu,
Ní ọjọ́ náà, “Kọrin nípa ọgbà àjàrà eléso kan.
3 “Na da Na waini efe sagai amoma hano iaha. Dunu eno da mae wadela: lesima: ne, na da gasia amola esosea, sosodo aligisa.
Èmi Olúwa ń bojútó o, Èmi ó bomirin ín láti ìgbàdégbà. Èmi ó ṣọ́ ọ tọ̀sán tòru kí ẹnikẹ́ni má ba à pa á lára.
4 Na waini sagai amoma Na da ougi galu, be wali amo ougi Na da yolesi dagoi. Na da aya: gaga: nomei amola gagalobo amoga fawane gegemusa: ganiaba, Na da amo huluane nene dagola: loba.
Inú kò bí mi. Bí ẹ̀gún àti ẹ̀wọ̀n bá dojú ìjà kọ mí! Èmi yóò dìde sí wọn ní ogun, Èmi yóò sì dáná sun gbogbo wọn.
5 Be Na Fi ilia ha lai da Na gaga: su hanai galea, ilia da Nama olofosu hogoi helemu da defea.
Bí bẹ́ẹ̀ kọ́, jẹ́ kí wọn wá sọ́dọ̀ mi fún ààbò; jẹ́ kí wọ́n wá àlàáfíà pẹ̀lú mi, bẹ́ẹ̀ ni, jẹ́ kí wọn wá àlàáfíà pẹ̀lú mi.”
6 Hobea, Isala: ili fi dunu (Ya: igobe egaga fi), da ifa agoane difi legemu amola dobea amola yebese legemu. Ilia fage legei da osobo bagade dedebomu.
Ní ọjọ́ iwájú Jakọbu yóò ta gbòǹgbò, Israẹli yóò tanná yóò sì rudi èso rẹ̀ yóò sì kún gbogbo ayé.
7 Hina Gode da Isala: ili fi ilima se iasu. Be ilia ha lai dunu ilia se lasu da Isala: ili fi ilia se baligisu, amola ilia dunu bogoi idi da Isala: ili ilia bogoi idi baligisu.
Ǹjẹ́ Olúwa ti lù ú gẹ́gẹ́ bí ó ti lu àwọn tí ó lù ú bolẹ̀? Ǹjẹ́ a ti pa á gẹ́gẹ́ bí a ti pa àwọn tí ó pa á?
8 Hina Gode da Ea fi dunu se ima: ne, mugululi ga asunasi. Fedege agoane E da wadela: i gusugoe mabe fo amoga ili mugululi ga mini asi.
Nípa ogun jíjà àti ìjìyà ti o le ni ó fi dojúkọ ọ́ pẹ̀lú ìjì gbígbóná ni ó lé e jáde, gẹ́gẹ́ bí ọjọ́ tí afẹ́fẹ́ ìlà-oòrùn fẹ́.
9 Be Isala: ili dunu da hame lalegagui dunu ilia ‘oloda’ igi goudane, osobo su agoane hamosea, amola gabusiga: manoma gobesu ‘oloda’ amola ogogosu uda ‘gode’ amo A: sela ea dawa: digisu hahamosu liligi da wadela: lesi dagoi ba: sea, amo esoga fawane Hina Gode da ilia wadela: i hou gogolema: ne olofomu.
Nítorí èyí báyìí ni ètùtù yóò ṣe wà fún ẹ̀ṣẹ̀ Jakọbu, èyí ni yóò sì jẹ́ èso kíkún ti ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ rẹ. Nígbà tí ó bá mú kí àwọn òkúta pẹpẹ dàbí òkúta ẹfun tí a fọ́ sí wẹ́wẹ́, kì yóò sí ère Aṣerah tàbí pẹpẹ tùràrí tí yóò wà ní ìdúró.
10 Moilai, amo musa: gagoi gasa bagade amoga gaga: i da wali mugululi, wadela: lesi dagoi ba: sa. Wali, amo sogebiga, bulamagau amola sibi da gisi naha amola helefisa.
Ìlú olódi náà ti dahoro, ibùdó ìkọ̀sílẹ̀, tí a kọ̀ tì gẹ́gẹ́ bí aginjù; níbẹ̀ ni àwọn ọmọ màlúù ti ń jẹ oko níbẹ̀ ni wọn ń sùn sílẹ̀; wọn sì jẹ gbogbo ẹ̀ka rẹ̀ tán.
11 Ifa huluane ilia amoda da bioi amola fi dagoi ba: sa. Amola uda ilia da amo lalu ifa agoane gagadosa. Dunu huluane da Gode Ea hou dawa: hame laiba: le, ilia Hahamosu dunu Gode da ilima hame asigimu amola se imunu.
Nígbà tí àwọn ẹ̀ka rẹ̀ bá rọ, a ó ya wọn dànù àwọn obìnrin dé, wọ́n sì fi wọ́n dáná nítorí aláìlóye ènìyàn ni wọn jẹ́, nítorí náà ni ẹni tí ó dá wọn kì yóò ṣàánú fún wọn; bẹ́ẹ̀ ni ẹni tí ó mọ wọn kì yóò sì fi ojúrere wò wọ́n.
12 Amo esoga, Hina Gode da dunu da widi amola gisi afafasa, amo defele soge amo da Iufala: idisi Hano muni asili, Idibidi alalo legei amoga doaga: sa, amoga Ea fi dunu afae afae E da gilisimu.
Ní ọjọ́ náà Olúwa yóò sì kó oore láti ìṣàn omi odo Eufurate wá títí dé Wadi ti Ejibiti, àti ìwọ, ìwọ ọmọ Israẹli, ni a ó kójọ ní ọ̀kọ̀ọ̀kan.
13 Amo eso da doaga: sea, dalabede dusu da Isala: ili dunu mugululi asi Asilia soge amola Idibidi soge ganodini esalu, amo buhagima: ne olelemu. Ilia da misini, sema agolo Yelusaleme amo ganodini diala, amoga ilia da Hina Godema nodone sia: ne gadomu.
Àti ní ọjọ́ náà, a ó fun fèrè ńlá kan. Gbogbo àwọn tí ń ṣègbé lọ ní Asiria àti àwọn tí ń ṣe àtìpó ní Ejibiti yóò wá sin Olúwa ní òkè mímọ́ ní Jerusalẹmu.

< Aisaia 27 >