< Aisaia 22 >

1 Amo sia: da Esala Ba: su Fago sogebi ea hou olelesa. Wali da adi hou hamosala: ? Abuliba: le, dunu huluane da diasu gadodili da: iya heda: le, hahawane gilisisu hamosala: ?
Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ tí ó jẹ mọ́ àfonífojì ìran. Kí ni ó ń dààmú yín báyìí, tí gbogbo yín fi gun orí òrùlé lọ?
2 Moilai bai bagade fi huluane da hahawane halasa. Sia: bagade da moilai ganodini nabasa. Be dilia fi dunu amo da gegesu ganodini bogoi da gegebeba: le hame bogoi.
Ìwọ ìlú tí ó kún fún rúkèrúdò, ìwọ ìlú àìtòrò òun rògbòdìyàn a kò fi idà pa àwọn òkú rẹ, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò kú ní ojú ogun.
3 Dilia dadi gagui ouligisu dunu huluane da mae gala: le, hobeale, ilia ha lai amoga suguli lai dagoi ba: i.
Gbogbo àwọn olórí i yín ti jùmọ̀ sálọ; a ti kó wọn nígbèkùn láìlo ọfà. Ẹ̀yin tí a mú ni a ti kó lẹ́rú papọ̀, lẹ́yìn tí ẹ ti sá nígbà tí ọ̀tá ṣì wà lọ́nà jíjìn réré.
4 Amaiba: le, dilia na yolesima! Bai na da na fi dunu bagohame bogoiba: le, na da ha: giwane dimusa: dawa: lala. Na dogo denesima: ne mae misa.
Nítorí náà ni mo wí pé, “Yípadà kúrò lọ́dọ̀ mi: jẹ́ kí n sọkún kíkorò. Má ṣe gbìyànjú àti tù mí nínú nítorí ìparun àwọn ènìyàn mi.”
5 Ninia da Esala Ba: su Fago amo ganodini, ninima hasalasu amola beda: su amola ededenasu hou fawane ba: sa. Amola, Hina Gode Bagadedafa, E da liligi huluanedafa Ouligisu, Hi fawane da amo hou ninima iasi. Ninia moilai gagoi huluane da fabeba: le, mugului dagoi, amola dunu da fidima: ne wele sia: beba: le, ilia sia: da agologa gobagala: lala.
Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun ní ọjọ́ kan tí rúkèrúdò àti rògbòdìyàn àti ẹ̀rùjẹ̀jẹ̀ ní àfonífojì ìmọ̀, ọjọ́ tí a ń wó ògiri lulẹ̀ àti sísun ẹkún lọ sí àwọn orí òkè.
6 Ila: me soge fi dadi gagui dunu da hosi da: iya fila heda: le, oulali amola dadi gaguiwane misi. Eno dadi gagui dunu, ilia da: igene gaga: su liligi gaguiwane, amo Gia sogega misi.
Elamu mú apó-ọfà lọ́wọ́, pẹ̀lú àwọn agun-kẹ̀kẹ́-ogun àti àwọn ẹṣin, Kiri yọ àpáta rẹ̀ síta.
7 Nasegagi fago soge Yuda soge amo ganodini diala, da sa: liode amoga nabai dagoi ba: i. Dadi gagui dunu amo hosi da: iya fila heda: i, da Yelusaleme logo ga: su gadenene lelebe ba: i.
Àyànfẹ́ àfonífojì rẹ kún fún kẹ̀kẹ́ ogun, àwọn ẹlẹ́ṣin ni a gbá jọ sí ẹnu-bodè ìlú.
8 Yuda soge ea gaga: su liligi huluane wadela: lesi dagoi ba: i. Amalalu, dilia da gegesu liligi huluane, amo gegesu liligi ligisisu diasu amoga lale, gadili gaguli misi.
Gbogbo ààbò Juda ni a ti ká kúrò. Ìwọ sì gbójú sókè ní ọjọ́ náà sí àwọn ohun ìjà ní ààfin ti inú aginjù.
9
Ìwọ rí i pé ìlú u Dafidi ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ ààyè níbi ààbò rẹ̀, ìwọ ti tọ́jú omi sínú adágún ti ìsàlẹ̀.
10 Dilia da Yelusaleme gagoi ba: lu, amo ganodini sogebi afae afae da wadela: lesi dagoi ba: i. Dilia da Yelusaleme huluane ba: i. Dilia mogili, Yelusaleme gagoi bu hahamoma: ne, igi lamusa: , diasu mogili mugului dagoi.
Ìwọ ka àwọn ilé tí ó wà ní Jerusalẹmu ó sì wó ọ̀pọ̀lọpọ̀ ilé lulẹ̀ láti fún ògiri lágbára.
11 Dilia da hano amo da hemone wayabo amoga maha, amo hai dialoma: ne dilia da hihiga: le gagui. Be dilia da Gode (amo da hemone waha doaga: be hou ilegele, hamomusa: hamoi) Ema hamedafa dawa: i.
Ìwọ mọ agbemi sí àárín ògiri méjì fún omi inú adágún àtijọ́, ṣùgbọ́n ìwọ kò wo ẹni tí ó ṣe é tẹ́lẹ̀ tàbí kí o kọbi ara sí ẹni tí ó gbèrò rẹ̀ ní ìgbà pípẹ́ sẹ́yìn.
12 Ouligisudafa Hina Gode Bagadedafa da amane wele sia: i, “Dilia da dialuma hinabo waga: ne, gogolole abula eboboi ga: ne, didigia: ma!”
Olúwa, àní Olúwa àwọn ọmọ-ogun, pè ọ́ ní ọjọ́ náà láti sọkún kí o sì pohùnréré, kí o tu irun rẹ dànù kí o sì da aṣọ ọ̀fọ̀ bora.
13 Be amo mae dawa: le, dilia da oufesega: i amola hahawane lolo nasu. Dilia da sibi amola bulamagau moma: ne, medole legei. Amola dilia da waini hano mai. Dilia da amane sia: i, “Ninia da ha: i amola waini hano manu da defea. Bai aya ninia bogomu.”
Ṣùgbọ́n wò ó, ayọ̀ àti ayẹyẹ wà; màlúù pípa àti àgùntàn pípa, ẹran jíjẹ àti ọtí wáìnì mímu! Ẹ̀yin wí pé, “Jẹ́ kí a jẹ kí a mu, nítorí pé lọ́la àwa ó kú!”
14 Hina Gode Ouligisu Bagadedafa Hisu da nama amane sia: i, “Ilia da baligili wadela: idafa hamobeba: le, ilia da osobo bagadega esalea, Na da ilia hou hamedafa gogolema: ne olofomu. Na, Hina Gode Ouligisu Bagadedafa da sia: i dagoi.”
Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti sọ èyí di mí mọ̀ létí ì mi: “Títí di ọjọ́ ikú yín a kò ní ṣe ètùtù fún ẹ̀ṣẹ̀ yìí,” ni Olúwa wí, àní Olúwa àwọn ọmọ-ogun.
15 Ouligisudafa Hina Gode Bagadedafa da na da Siebena (hina bagade diasu ouligisu dunu) amoma asili, ema sisasu amane iasima: ne sia: i,
Èyí ni ohun tí Olúwa, àní Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí, “Lọ, sọ fún ìríjú yìí pé, fún Ṣebna, ẹni tí ààfin wà ní ìkáwọ́ rẹ̀.
16 “Di dawa: loba, di da nowayale dawa: bela: ? Disu da dia bogoi uli dogoi igi agolo la: ididili dogomu, amo di hamoma: ne da hame ilegei.
Kí ni ohun tí ò ń ṣe níhìn-ín yìí àti pé ta ni ó sì fún ọ ní àṣẹ láti gbẹ́ ibojì kan fún ara rẹ níhìn-ín yìí, tí ó gbẹ́ ibojì ní ibi gíga tí ó sì gbẹ́ ibi ìsinmi rẹ nínú àpáta?
17 Disu da dia hou da bagadedafa dawa: Be Hina Gode da di gaguia gadole galagamu.
“Kíyèsára, Olúwa fẹ́ gbá ọ mú gírígírí kí ó sì jù ọ́ nù, ìwọ ọkùnrin alágbára.
18 E da di bolo agoane gaguia gadole, soge eno amo dia soge bagade baligisa, amoga di galadigimu. Amo ganodini, di da sa: liode amo di da hahawane ba: sa, amoga dafulili di da bogomu. Dia hou hamobeba: le, dia hina bagade ea fi da gogosiamu.
Òun yóò ká ọ rúgúdù bí i òkìtì yóò sì sọ ọ́ sí orílẹ̀-èdè ńlá kan. Níbẹ̀ ni ìwọ yóò sì kú sí àti níbẹ̀ pẹ̀lú ni àwọn kẹ̀kẹ́ ogun àràmọ̀ǹdà rẹ yóò wà— ìwọ di ìtìjú sí ilé ọ̀gá rẹ!
19 Hina Gode da dia ouligisu sogebi amoga di fadegamu. Dia da gaguia gadoi, be Hina Gode da di hedofale gisalugala: mu.”
Èmi yóò yọ ọ́ kúrò ní ipò rẹ, a ó sì lé ọ kúrò ní ipò rẹ.
20 Hina Gode da Siebenama amane sia: i, “Na da amo hou hamosea, Na da Na hawa: hamosu dunu amo Ilaiagime (Hiligaia egefe) amo misa: ne sia: mu.
“Ní ọjọ́ náà. Èmi yóò ké sí ọmọ ọ̀dọ̀ mi, Eliakimu ọmọ Hilkiah.
21 Na da dia hawa: hamomusa: ilegei abula amola dia bulu ema idiniginisimu, amola dia ouligisu hou huluane ema imunu. E da Yelusaleme fi dunu amola Yuda soge fi dunu ilima ada agoane esalumu.
Èmi yóò fi aṣọ rẹ wọ̀ ọ́, n ó sì so ẹ̀wọ̀n rẹ mọ́ ọn ní ọrùn, èmi ó sì gbé àṣẹ rẹ lé e lọ́wọ́. Òun yó sì jẹ́ baba fún gbogbo olùgbé e Jerusalẹmu àti fún ilé e Juda.
22 Na da e Da: ibidi egaga fi hina bagade amo fawane hagudu ouligisudafa agoane hamomu. E da fedege agoane, ouligisu doasisu “gi” gagulaligi agoane ba: mu. Ea doasi liligi enoga ga: mu da hamedei ba: mu, amola ea ga: si liligi, enoga doasimu da hamedei ba: mu.
Èmi yóò sì fi kọ́kọ́rọ́ ilé e Dafidi lé e ní èjìká; ohunkóhun tí ó bá ṣí, ẹnikẹ́ni kì yóò lè ti, ohunkóhun tí ó bá sì tì, ẹnikẹ́ni kì yóò le è ṣí.
23 Na da fedege agoane Ilaiagime gosagisisu liligi agoane, ea sogebi amoga mae muguluma: ne, gasawane lala: gimu. Amola ea sosogo fi dunu huluane da ea houba: le nodomu.
Èmi yóò sì kàn mọ́lẹ̀ bí èèkàn tí ó dúró gírígírí ní ààyè e rẹ̀; òun yóò sì jẹ́ ibùjókòó ọlá fún ilé baba rẹ̀.
24 Be fa: no, ea sosogo fi amola ea ouligi dunu huluane da ema dioi liligi bagadewane ba: mu. Ilia da fedege agoane, ofodo amola gaga amola gosagisisu liligi amo defele ema gosagisi dialebe ba: mu.
Gbogbo ògo ìdílé rẹ̀ ni wọn yóò sì fi kọ ní ọrùn: ìran rẹ̀ àti àrọ́mọdọ́mọ rẹ̀, gbogbo ohun èlò ife, títí dé orí ago ọtí.
25 Amo hou doaga: sea, agenesi gosagisisu musa: gasawane lala: gi dialu da hoholigili fadegale, sa: imu. Amasea, liligi amoga gosagisi dialu da wadela: lesi dagoi ba: mu,” Hina Gode da sia: i dagoi.
“Ní ọjọ́ náà,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí, “Èèkàn tí a kàn mọ́lẹ̀ gírígírí ní ààyè e rẹ̀ yóò yẹrí, yóò dẹ̀gbẹ́ yóò sì fẹ̀gbẹ́ lélẹ̀ àti ẹrù tí ó létéńté lórí i rẹ̀ ni a ó gé lulẹ̀.” Olúwa ni ó ti sọ ọ́.

< Aisaia 22 >