< Aisaia 14 >

1 Fa: no agoane, Hina Gode da Ea fi dunu Isala: ili fi ilima bu asigimu. E da ili Ea fidafa bu ilegemu, amola ilia da ilia sogedafa amo ganodini bu esaloma: ne, E da logo fodomu. Amola ga fi dunu da misini, ilia amola gilisili Isala: ili soge ganodini esalumu.
Olúwa yóò fi àánú hàn fún Jakọbu, yóò tún Israẹli yàn lẹ́ẹ̀kan sí i yóò sì fi ìdí wọn kalẹ̀ ní ilẹ̀ àwọn tìkára wọn. Àwọn àjèjì yóò darapọ̀ mọ́ wọn, wọn yóò sì fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú ilé e Jakọbu.
2 Fifi asi gala bagohame da Isala: ili fi ilia soge amo Hina Gode da ilima i, amoma buhagimusa: ili fidimu. Amola amo ganodini, fifi asi gala dunu da Isala: ili dunu ilia udigili hawa: hamosu dunu ba: mu. Dunu fi da musa: Isala: ili dunu ilima hasanasili, afugili gaguli asi, amoma Isala: ili dunu da hasanasili gaguli masunu. Amola Isala: ili dunu da ilima hinawane esalebe ba: mu.
Àwọn orílẹ̀-èdè yóò gbà wọ́n wọn yóò sì mú wọn wá sí ààyè e wọn. Ilé Israẹli yóò gba àwọn orílẹ̀-èdè gẹ́gẹ́ bí àwọn ẹrúkùnrin àti ẹrúbìnrin ní ilẹ̀ Olúwa. Wọn yóò kó àwọn akónilẹ́rú wọn ní ìgbèkùn wọn yóò sì jẹ ọba lórí àwọn amúnisìn wọn.
3 Hina Gode da Isala: ili dunu ilima helefisu imunu. Ilia da se bu hame nabimu, amola udigili enoga sesebe hawa: hamosu yolesimu.
Ní ọjọ́ tí Olúwa yóò fi ìtura fún un yín kúrò nínú ìpọ́njú àti ìyà àti ìdè ìkà,
4 Hina Gode da agoane hamosea, Isala: ili dunu da Ba: bilone hina bagade ema oufesega: ne amane sia: mu da defea, “Nimi bagade hame asigi hina bagade da dafai dagoi. E da dunu eno ilima se bu hame imunu.
ẹ ó sì fi ọ̀rọ̀ àbùkù yìí kan ọba Babeli pé, báwo ni amúnisìn ṣe wá sí òpin! Báwo ni ìbínú rẹ̀ ṣe parí!
5 Hina Gode da wadela: i ouligisu dunu ilia gasa hedofai dagoi.
Olúwa ti dá ọ̀pá ìkà náà, ọ̀pá àwọn aláṣẹ,
6 Ilia da dunu eno ilima se iasu amola fifi asi gala ilima ilia da hasanasi, ilima se ima: ne hame yolesi.
èyí tí ó ti lu àwọn ènìyàn bolẹ̀ pẹ̀lú ti kò dáwọ́ dúró, nínú ìrunú ni ó ṣẹ́gun àwọn orílẹ̀-èdè pẹ̀lú ìgbónára tí kò lópin.
7 Be wali osobo bagade fifi asi gala huluane da helefili, olofosu ba: sa. Amola dunu huluane da hahawaneba: le, gesami hea: sa.
Gbogbo ilẹ̀ ni ó wà ní ìsinmi àti àlàáfíà, wọ́n bú sí orin.
8 ‘Saibalase’ ifa amola Lebanone dolo ifa da hina bagade dafaiba: le, hahawane nodosa. Bai e da asiba: le, ili hedofama: ne, dunu da hame esala.
Pẹ̀lúpẹ̀lú àwọn igi junifa àti àwọn igi kedari ti Lebanoni ń yọ̀ lórí rẹ wí pé, “Níwọ́n bí a ti rẹ̀ ọ́ sílẹ̀ báyìí, kò sí agégi tí yóò wá láti gé wa lulẹ̀.”
9 Bogoi sogebi ouligisu dunu ilia da Ba: bilone hina bagade aowamusa: momagesa. Musa: esalu osobo bagade ouligisu dunu ilia a: silibu da nedigisa. Ilia da fisu fisili, wa: legadosa. (Sheol h7585)
Ibojì tí ó wà ní ìsàlẹ̀ ni a ru sókè láti pàdé rẹ ní ìpadàbọ̀ rẹ̀ ó ru ẹ̀mí àwọn tí ó ti lọ sókè láti wá kí ọ gbogbo àwọn tí ó jẹ́ olórí ní ayé ó mú kí wọn dìde lórí ìtẹ́ wọn gbogbo àwọn tí ó jẹ ọba lórí àwọn orílẹ̀-èdè. (Sheol h7585)
10 Ilia huluane da ema agoane wele sia: sa, “Di da ninima gilisi dagoi. Dia da wali nini defele gasa hame gala.
Gbogbo wọn yóò dáhùn, wọn yóò wí fún ọ wí pé, “Ìwọ pẹ̀lú ti di aláìlera, gẹ́gẹ́ bí àwa pẹ̀lú ìwọ náà ti dàbí wa.”
11 Musa: dunu da dima nodomusa: , sani baidama dusu, be wali di da guiguda: bogoi sogebi amoga misi doaga: i. Di da ifidi gilisisu amoga diaha amola dia da daba: amoga dedeboi dagoi. (Sheol h7585)
Gbogbo rẹ̀ ni ó di ìrẹ̀sílẹ̀ lọ sí ibojì, pẹ̀lú ariwo àwọn dùùrù rẹ, àwọn ìdin ni wọ́n fọ́nkálẹ̀ lábẹ́ rẹ àwọn ekòló sì ti bò ọ́ mọ́lẹ̀. (Sheol h7585)
12 Ba: bilone hina bagade! Hadigi gusubia gasumuni di! Dia da Hebene amo ganodini esalu, dafai dagoi. Di da musa: fifi asi gala ilima hasanasi, be wali di da osobo bagadega gisalugala: i dagoi ba: sa.
Báwo ni ìwọ ṣe ṣubú lulẹ̀ láti ọ̀run wá, ìwọ ìràwọ̀ òwúrọ̀, ọmọ òwúrọ̀ náà! A ti sọ ọ́ sílẹ̀ sínú ayé, ìwọ tí o ti tẹ orí àwọn orílẹ̀-èdè ba rí!
13 Di da Hebene sogega heda: le, dia fisu amo Gode Ea gadodafa gasumuni amo baligili, gadodafa legemusa: dawa: i galu. Dia da hina bagade agoane, goumi ga (north) gala amoga ogogosu ‘gode’ liligi da gilisisa, amoga fimusa: dawa: i galu.
Ìwọ sọ nínú ọkàn rẹ pé, “Èmi yóò gòkè lọ sí ọ̀run; èmi yóò gbé ìtẹ́ mi sókè ga ju àwọn ìràwọ̀ Ọlọ́run, Èmi yóò gúnwà ní orí òkè àpéjọ ní ṣóńṣó orí òkè mímọ́.
14 Di da heda: le, mu mobi amo da: iya fila heda: le, Hina Gode bagadedafa amo defele esalomusa: dawa: i galu.
Èmi yóò gòkè lọ rékọjá àwọn àwọsánmọ̀; èmi yóò ṣe ara mi gẹ́gẹ́ bí Ọ̀gá-ògo.”
15 Be amo hame hamone, di da bogoi sogebi osodogone amoga gisalugala: i dagoi ba: sa. (Sheol h7585)
Ṣùgbọ́n a ti rẹ̀ ọ́ sílẹ̀ wọ inú ibojì lọ lọ sí ìsàlẹ̀ ọ̀gbun. (Sheol h7585)
16 Bogoi dunu da ilia lafi dagale, dima hamugini ba: mu. Ilia da amane adole ba: mu, “Amo da gasa fi dunu musa: osobo bagade yagugui, amola ea hamoiba: le, fifi asi gala da ugugui. Amo da amo dunula: ?
Àwọn tí ó rí ọ yóò tẹjúmọ́ ọ, wọ́n ronú nípa àtubọ̀tán rẹ: “Ǹjẹ́ èyí ni ẹni tí ó mi ayé tìtì tí ó sì jẹ́ kí àwọn ilẹ̀ ọba wárìrì.
17 Amo dunu da moilai bagohame wadela: lesi, amola ea hamobeba: le, osobo bagade da hafoga: i, wadela: i soge agoane ba: i. Amola ea se iasu diasu hamosu dunu gagui amo ilia sogega buhagima: ne, e da ili se iasu diasu logo hamedafa doasi. Amo da amo dunula: ?”
Ẹni tí ó sọ ayé di aginjù, tí ó sì pa ìlú ńlá ńlá rẹ̀ run tí kò dá àwọn òǹdè rẹ̀ sílẹ̀ láti padà sílé?”
18 Osobo bagade hina bagade dunu huluane ilia da: i hodo da bogoi uli dogoi ida: iwane ganodini diaha.
Gbogbo àwọn ọba orílẹ̀-èdè ni a tẹ́ sílẹ̀ ọ̀kọ̀ọ̀kan nínú ibojì tirẹ̀.
19 Be di da uli dogoi hame gala. Dia da: i hodo da gadili dasama: ne galadigi dagoi. Dia da: i hodo da dadi gagui dunu gegesu ganodini medole legei ilia da: i hodo amoga dedeboi dagoi. Amola di amola ili da gilisili gele gelabo ganodini galadigili banenesi dagoi ba: sa.
Ṣùgbọ́n a jù ọ́ síta kúrò nínú ibojì gẹ́gẹ́ bí ẹ̀ka igi tí a kọ̀sílẹ̀, àwọn tí a pa ni ó bò ọ́ mọ́lẹ̀, àwọn tí idà ti gún, àwọn tí ó sọ̀kalẹ̀ lọ sínú òkúta inú ọ̀gbun. Gẹ́gẹ́ bí òkú ó di ìtẹ̀mọ́lẹ̀ ní abẹ́ àtẹ́lẹsẹ̀,
20 Di da hina bagade eno defele noga: le uli dogoi hame ba: mu, amola dia wadela: i sosogo fi afae esalebe hame ba: mu. Bai di da dia sogedafa wadela: lesi dagoi, amola dia fidafa dunu medole legei dagoi.
a kò ní sin ọ́ pẹ̀lú wọn, nítorí pé o ti ba ilẹ̀ rẹ jẹ́ o sì ti pa àwọn ènìyàn rẹ. Ìran àwọn ìkà ni a kì yóò dárúkọ wọn mọ́.
21 Medole legesu wahadafa muni hamomu da defea. Amo hina bagade ea egefelali ilia da aowalalia wadela: i hou hamoiba: le, bogomu. Afae da osobo bagade ouligima: ne, o osobo bagade amo moilai bai bagade gilisi gaguma: ne, da esalebe hame ba: mu.”
Tọ́jú ibìkan tí a ó ti pa àwọn ọmọkùnrin rẹ nítorí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn baba ńlá wọn, wọn kò gbọdọ̀ dìde láti jogún ilẹ̀ kí wọ́n sì bo orí ilẹ̀ pẹ̀lú àwọn ìlú u wọn.
22 Hina Gode Bagadedafa da amane sia: sa, “Na da Ba: bilone fi amo doagala: le, ili gugunufinisimu. Dunu afae o mano afae esalebe hame ba: mu. Huluane da gugunufinisi dagoi ba: mu. Na, Hina Gode, da sia: i dagoi.
“Èmi yóò dìde sókè sí wọn,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí. “Èmi yóò ké orúkọ rẹ̀ kúrò ní Babeli àti àwọn tí ó sálà, àwọn ọmọ àti ìran rẹ̀,” ni Olúwa wí.
23 Na da Ba: bilone soge wadela: le, bu fafu soge agoane hamomu. Gugunia sio fawane da amogawi esalebe ba: mu. Na da isu doga: su defele amoga Ba: bilone soge doga: le, liligi huluane da hamedafa ba: mu. Na, Hina Gode Bagadedafa da sia: i dagoi.”
Èmi yóò yí i padà sí ibùgbé àwọn òwìwí àti sí irà; Èmi yóò fi ọwọ́ ìparun gbá a, ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
24 Hina Gode Bagadedafa da dafawane hamoma: ne sia: i dagoi, “Na ilegei huluane da ba: mu. Na da hamomu sia: i liligi huluane hamoi dagoi ba: mu.
Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti búra, “Gẹ́gẹ́ bí mo ti ṣètò, bẹ́ẹ̀ ni yóò rí, àti bí mo ti pinnu, bẹ́ẹ̀ ni yóò sì dúró.
25 Na da Asilia dunu amo Na soge Isala: ili amo ganodini gugunufinisimu. Amola Na goumiga Na da ilima osa: gili banenesimu. Asilia dunu da Na fi ilima ‘youge’ dioi bagadewane gala. Be amo ‘youge’ Na da ilima fadegamu.
Èmi yóò run Asiria ní ilẹ̀ mi, ní àwọn orí òkè mi ni èmi yóò ti rún un mọ́lẹ̀. Àjàgà rẹ̀ ni a ó mú kúrò lọ́rùn àwọn ènìyàn mi, ẹrù u rẹ̀ ni ó mú kúrò ní èjìká wọn.”
26 Amo hou Na da osobo bagadega hamoma: ne ilegei dagoi. Amola Na lobo da fifi asi gala ilima se ima: ne, ililua: i dagoi.”
Èyí ni ètò tí a pinnu rẹ̀ fún gbogbo ayé, èyí ni ọwọ́ tí a nà jáde káàkiri gbogbo orílẹ̀-èdè.
27 Hina Gode Bagadedafa da amo hamoma: ne, dafawane ilegei dagoi. E da se ima: ne, lobo ilua: le lela. Amola dunu afae da Ea ilegesu hedofamu hamedei ba: sa.
Nítorí Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti pète, ta ni yóò sì ká a lọ́wọ́ kò? Ọwọ́ọ rẹ ti nà jáde, ta ni ó sì le è fà á padà?
28 Ode afae amoga hina bagade A: iha: se da bogoi, Aisaia da sia: eno dunu huluane nabima: ne sisia: i.
Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ yí wá ní ọdún tí ọba Ahasi kú.
29 Filisidini dunu, dilia! Galiamo da dili fasu amo da fi dagoi. Be dilia da hahawane hame ba: mu. Saya: be afae da bogosea, baligili nimi bagade eno da ea sogebi lama: ne maha. Saya: be ea oso amoga hagili ahoabe hanome agoane da lalelegesa.
Má ṣe yọ̀, gbogbo ẹ̀yin Filistia, pé ọ̀pá tí ó lù ọ́ ti dá; láti ibi gbòǹgbò ejò náà ni paramọ́lẹ̀ yóò ti hù jáde, èso rẹ̀ yóò sì jẹ́ oró ejò tí í jóni.
30 Hina Gode da Ea dunu fi amo ganodini hame gagui dunu ilima sibi ouligisu agoane ba: mu. E da ili gaga: iwane esaloma: ne, noga: le fidimu. Be E da dili Filisidini dunu dilima ha: i bagade iasimuba: le, dilia fi dunu afae esalebe hame ba: mu.
Ẹni tí ó kúṣẹ̀ẹ́ jù yóò ní pápá oko, àwọn aláìní yóò sì dùbúlẹ̀ láìléwu. Ṣùgbọ́n gbòǹgbò o rẹ̀ ni èmi ó fi ìyàn parun, yóò sì ké àwọn ẹni rẹ tí ó sálà kúrò.
31 Dilia Filisidini moilai bai bagade esalebe dunu! Digini wele sia: ma! Fidima: ne wele sia: ma! Dilia huluane beda: mu da defea! Osobo su mobi agoane da ga (north) amoga maha. Amo mobi da dadi gagui gilisisu defele ba: sa, amola amo gilisisu ganodini, beda: i dunu o hobeale ahoasu dunu da hame ba: sa.
Hu, ìwọ ẹnu-ọ̀nà! Kígbe, ìwọ ìlú! Yọ́ kúrò, gbogbo ẹ̀yin Filistia! Èéfín kurukuru kan ti àríwá wá, kò sì ṣí amóríbọ́ kan nínú ẹgbẹ́ wọn.
32 Filisidini dunu fi da ninima sia: adole ba: su dunu asunasi. Ninia ilima adi adole ima: bela: ? Ninia da ilima amane sia: mu, “Hina Gode da Saione Goumi amo mae muguluma: ne ilegei dagoi. Amola Ea fi dunu wali se nabaha, amo da amogawi gaga: su ba: mu.”
Kí ni ìdáhùn tí a ó fún agbẹnusọ orílẹ̀-èdè náà? “Olúwa ti fi ìdí Sioni kalẹ̀, àti nínú rẹ̀ ni àwọn ènìyàn rẹ̀ tí a ti pọ́n ọn lójú yóò ti rí ààbò o wọn.”

< Aisaia 14 >