< Hosia 6 >

1 Isala: ili dunu da amane sia: sa, “Ninia da Hina Godema sinidigimu. E da ninima se iasu. Be E da dafawane nini uhinisimu. E da nini fofa: ginisi, be E da nini fofa: gi amo lala: gilisimu.
“Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí a padà sọ́dọ̀ Olúwa ó ti fà wá ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ ṣùgbọ́n yóò mú wa láradá Ó ti pa wá lára ṣùgbọ́n yóò dí ojú ọgbẹ́ wa.
2 E da eso aduna o udiana ouesalu, nini bu wa: lesimu. Amasea, ninia da Ea midadi amoga bu esalumu.
Lẹ́yìn ọjọ́ méjì, yóò sọ wá jí ní ọjọ́ kẹta yóò mú wa padà bọ̀ sípò kí a ba à le wá gbé níwájú rẹ̀.
3 Ninia Hina Gode da Godedafa sia: mu da defea. Eso huluane amoga, hehebolo da maha amola woufo mubi galu gibu da mae yolele osoboga daha. Amo defele, Hina Gode da ninima bu misunu.”
Ẹ jẹ́ kí a mọ Olúwa; ẹ jẹ́ kí a tẹ̀síwájú láti mọ̀ ọ́n. Gẹ́gẹ́ bí oòrùn ṣe ń yọ, yóò jáde; yóò tọ̀ wá wá bí òjò, bí òjò àkọ́rọ̀ ti ń bomirin ilẹ̀.”
4 Be Hina Gode da amane sia: sa, “Isala: ili amola Yuda! Na da alima adi hamoma: bela: ? Alia Nama asigi hou da hahabe mobi defele hedolowane geasa. Amola alia Nama asigi hou da oubi baea amo da hahabe hedolowane geabe defele ba: sa.
“Kí ni èmi ó ṣe pẹ̀lú rẹ, Efraimu? Kí ni èmi ó ṣe pẹ̀lú rẹ, Juda? Ìfẹ́ rẹ dàbí ìkùùkuu òwúrọ̀ bí ìrì ìdájí tí ó kọjá lọ kíákíá.
5 Amaiba: le, Na da Na balofede dunu alima Na wadela: lesimusa: sia: ne iasu ima: ne asunasi dagoi. Alia da Nama sinidigimu Na da hanai. Amola Na da moloiwane amo hou alima olelei, amane.
Nítorí náà ni mo ṣe gé e yín sí wẹ́wẹ́ láti ọwọ́ àwọn wòlíì, Mo pa yín pẹ̀lú ọ̀rọ̀ ẹnu mi, ìdájọ́ mi tàn bí i mọ̀nàmọ́ná lórí yín.
6 Na da alia Nama mae yolele asigi hou amo hanai gala. Be alia ohe gobele salasu Na higasa. Na fi dunu da ilia asigi dawa: su ganodini Na hou dawa: mu, amo da ohe gobele salasu hou baligisa.
Nítorí àánú ni mo fẹ́, kì í ṣe ẹbọ; àti ìmọ̀ Ọlọ́run ju ọrẹ ẹbọ sísun lọ.
7 Be Na fi dunu da Ga: ina: ne soge ganodini sa: ili, A:dame moilaiga doaga: le, ilia da Na gousa: su hamoi hedolowane giadofai.
Bí i Adamu, wọ́n da májẹ̀mú wọ́n jẹ́ aláìṣòótọ́ sí mi níbẹ̀.
8 Gilia: de soge da wadela: i hamosu dunu amola fane legesu dunu amoga nabai gala.
Gileadi jẹ́ ìlú àwọn ènìyàn búburú tí ń ṣiṣẹ́ ẹ̀ṣẹ̀, a sí ti fi ẹ̀ṣẹ̀ bà á jẹ́.
9 Gobele salasu dunu da wamolasu dunu gilisisu amo da logoga desegaligi dialebe agoane ba: sa. Ilia da Siegeme hadigi sogebi ahoasu logo amogawi fane legesu hou hamonana. Amola ilia da amo hanaiba: le hamosa.
Bí adigunjalè ṣe ń ba ní bùba de àwọn ènìyàn bẹ́ẹ̀ ni àwọn àlùfáà, ń parapọ̀; tí wọ́n sì ń pànìyàn lójú ọ̀nà tó lọ sí Ṣekemu, tí wọ́n sì ń dá ẹ̀ṣẹ̀ tí ó ti ni lójú.
10 Na da Isala: ili soge ganodini wadela: idafa liligi ba: i dagoi. Na fi dunu ilila: da loboga hamoi ‘gode’ ilima nodone sia: ne gadoiba: le, ilia hou wadela: lesi dagoi.
Mo ti rí ohun tó ba ni lẹ́rù ní ilé Israẹli. Níbẹ̀ Efraimu, fi ara rẹ̀ fún àgbèrè Israẹli sì di aláìmọ́.
11 Amola dilia Yuda fi dunu! Dilia da wadela: i hou hamobeba: le Na da dilima amolawane se imunusa: eso ilegei dagoi.”
“Àti fún ìwọ, Juda, a ti yan ọjọ́ ìkórè rẹ. “Nígbà tí mo bá fẹ́ dá ohun ìní àwọn ènìyàn mi padà,

< Hosia 6 >