< Hosia 14 >

1 Isala: ili dunu! Dilia Hina Godema bu sinidigima! Dilia da wadela: le hamoiba: le, didigabone dafai dagoi.
Yípadà ìwọ Israẹli sí Olúwa Ọlọ́run rẹ. Ẹ̀ṣẹ̀ rẹ ló fa ìparun rẹ!
2 Hina Godema sinidigima! Amola amo sia: ne gadosa gobele iasu defele Ema ima, amane, “Ninia wadela: i hou huluane gogolema: ne olofoma amola ninia sia: ne gadosu nabima! Amalu ninia ilegele sia: i defele, ninia da Dima nodomu.
Ẹ gba ọ̀rọ̀ Olúwa gbọ́, kí ẹ sì yípadà sí Olúwa. Ẹ sọ fún un pé, “Darí gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ wa jì wá kí o sì fi oore-ọ̀fẹ́ gbà wá, kí àwa kí ó lè fi ètè wa sán an fún ọ
3 Asilia da nini gaga: mu hame dawa: , amola gegesu hosi da nini gaga: mu gogolesa. Ninia bu ninia loboga hamoi ogogosu ‘gode’ ilima ‘Godedafa’ dio hame asulimu. Hina Gode! Di da dunu amo da fidisu dunu eno hame gala, ilima gogolema: ne olofosu imunusa: dawa:”
Asiria kò le gbà wá là; a kò ní í gorí ẹṣin ogun. A kò sì ní tún sọ ọ́ mọ́ láé, ‘Àwọn ni òrìṣà wa’ sí àwọn ohun tí ó fi ọwọ́ wa ṣe; nítorí pé lọ́dọ̀ rẹ ni àwọn aláìní baba tí ń rí àánú.”
4 Hina Gode da amane sia: sa, “Na da Na fi dunu Nama bu hiougia guda: mu. Na da Na dogo huluane amoga ilima asigimu. Na da ilima bu hame ougimu.
“Èmi wo àgàbàgebè wọn sàn, Èmi ó sì fẹ́ràn wọn, lọ́fẹ̀ẹ́, nítorí ìbínú mi ti yípadà kúrò lọ́dọ̀ wọn.
5 Na da gibu amo da hafoga: i soge fidibi defele, Na fi dunu fidimu. Ilia da mosoi agoane sogea falegalesimu. Ilia da Lebanone ifa defele, ifa difi modosa: i agoane ba: mu.
Èmi o dàbí ìrì sí Israẹli, wọn o sì yọ ìtànná bi ewéko lílì. Bi kedari ti Lebanoni yóò si ta gbòǹgbò.
6 Ilia da gaheabolo lula heda: su defele, gaheabolo esalusu ba: mu. Amola ilia da olife ifa defele, nina: hamoi dagoi ba: mu. Ilia da Lebanone dolo ifa defele, gabusiga: noga: i nabimu.
Àṣẹ̀ṣẹ̀yọ ẹ̀ka rẹ̀ yóò dàgbà, dídán ẹwà yóò rẹ̀ dànù bí igi olifi. Òórùn rẹ yóò sì dàbí igi kedari ti Lebanoni.
7 Ilia da bu Na Gaga: su hou amoha esalumu. Ilia da ifabi noga: idafa defele, noga: le heda: mu. Ilia da waini sagai defele, fage bagohame legemu. Dunu da Lebanone waini hano amoma nodosa, amo defele fifi asi gala da Na fi dunuma nodomu.
Àwọn ènìyàn yóò tún padà gbé lábẹ́ òjijì rẹ̀. Yóò rúwé bi ọkà. Yóò sì yọ ìtànná bi àjàrà, òórùn rẹ yóò dàbí ti wáìnì Lebanoni.
8 Isala: ili dunu da bu loboga hamoi ogogosu ‘gode’ ilima hame dawa: mu. Na da dialui ifa defele, ili ougigala: mu. Na da ilia hahawane dogolegele hou huluane ea bai gala.”
Ìwọ Efraimu, kín ló tún kù tí mo ní ṣe pẹ̀lú ère òrìṣà? Èmi ó dá a lóhùn, èmi ó sì ṣe ìtọ́jú rẹ. Mo dàbí igi junifa tó ń fi gbogbo ìgbà tutù, èso tí ìwọ ń so si ń wá láti ọ̀dọ̀ mi.”
9 Bagade dawa: su dunu da amo dedena sa: i sia: noga: le dawa: mu da defea. Amola ilia da amo sia: ilia dogo ganodini ligisimu da defea. Hina Gode Ea hou huluane da moloidafa. Amola moloi dunu da amoga fa: no bobogebeba: le, esalusu ba: lala. Be wadela: i hamosu dunu da Gode Ea hou higabeba: le, didigabone dafasa. Sia: ama dagoi
Ta ni ọlọ́gbọ́n? Òun yóò mòye àwọn nǹkan wọ̀nyí. Ta a ní ó mọ̀? Òun yóò ní ìmọ̀ wọn. Títọ́ ni ọ̀nà Olúwa àwọn olódodo si ń rìn nínú wọn, ṣùgbọ́n àwọn ọlọ́tẹ̀ ni yóò kọsẹ̀ nínú wọn.

< Hosia 14 >