< Hosia 11 >

1 Hina Gode da amane sia: sa, “Isala: ili ea goi hadini esoga, Na da ema asigisu. Na da e Nagofe agoane e Idibidi sogega esalu amo gadili welegai.
“Nígbà tí Israẹli wà ní ọmọdé mo fẹ́ràn rẹ̀, mo sì pe ọmọ mi jáde láti Ejibiti wá.
2 Na ema bagohame wei, be e da Nama bagohame baligi fa: i. Na dunu da Ba: ilema gobele salasu. Ilia da loboga hamoi ogogole ‘gode’ ilima gabusiga: manoma gobele salasu.
Bí a ti ń pe wọn, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ṣe ń sá kúrò lọ́dọ̀ mi, wọn rú ẹbọ sí Baali, wọn sì fi tùràrí jóná sí ère fínfín.
3 Be Na Nisu da Isala: ilima ahoasu hou olelei. Na da Na fi dunu Nima sogoba: le guda: i. Na da ili noga: le ouligi. Be ilia da Nama hame nodoi.
Lóòtítọ́ mo kọ́ Efraimu pẹ̀lú ní ìrìn mo di wọ́n mú ní apá, ṣùgbọ́n wọn kò mọ̀ pé mo ti mú wọn láradá.
4 Na da asigiliwane ili Nima hiougia guda: i. Na da youge ilia mugia galu amo fadegai amola Na da ilima ha: i manu imunusa: begudui.
Mo fi okùn ènìyàn fà wọ́n àti ìdè ìfẹ́. Mo mú àjàgà kúrò ni ọrùn wọn, Mo sì fi ara balẹ̀ fún wọn ni oúnjẹ.
5 Ilia Nama sinidigimu higasa. Amaiba: le, ilia da Idibidi sogega dafawane buhagima: ma. Amola Asilia fi da ili ouligimu.
“Ṣé wọn ò wá ní padà sí Ejibiti bí. Ṣé Asiria kò sì ní jẹ ọba lé wọn lórí bí nítorí pé wọ́n kọ̀ jálẹ̀ láti ronúpìwàdà?
6 Gegesu da ilia moilai ganodini doasa: ili, moilai logo ga: su da mugululi sa: imu. Na fi dunu da ilia hanaiga hamobeba: le, gegesu da ili wadela: lesimu.
Idà yóò kọ mọ̀nà ní gbogbo ìlú wọn yóò si bá gbogbo irin ẹnu odi ìlú wọn jẹ́ yóò sì fi òpin sí gbogbo èrò wọn.
7 Ilia da dafawane Nama baligi fa: lala. Youge da ilia mugi da: iya dialebeba: le, ilia da a: iya gusa: mu. Be enoga da amo youge hame gaguia gadolesimu.
Àwọn ènìyàn mi ti pinnu láti pẹ̀yìndà kúrò lọ́dọ̀ mi bí wọ́n tilẹ̀ pè wọ́n sọ́dọ̀ Ọ̀gá-ògo jùlọ, kò ní gbé wọn ga rárá.
8 Isala: ili! Na da habodane di yolesima: bela: ? Na da habodane di fisima: bela: ? Na da A: dama moilai bai bagade amola Siboime moilai bai bagade Amo wadela: lesi dagoi. Be Na da habodane amo defele di gugunufinisima: bela: ? Na dima bagadewane asigisa. Amaiba: le, Na da di gugunufinisimu hamedei ba: sa.
“Báwo ni èmi ó ṣe fi ọ́ sílẹ̀, Efraimu? Báwo ni èmi ó ṣe yọ̀ǹda rẹ̀, Israẹli? Báwo ni mo ṣe lè ṣe ọ bi i Adma? Báwo ni mo ṣe lè ṣe ọ bi i Seboimu? Ọkàn mi yípadà nínú mi àánú mi sì ru sókè.
9 Na da dima ougili se bidi hame imunu. Na da Isala: ili bu hame wadela: lesimu. Bai Na da mafua dunu hame, Na da Gode. Na, Hadigi Gode, Na da ani esala. Na ougiliwane dima hame misunu.
Èmi kò ni mú ìbínú gbígbóná mi ṣẹ, tàbí kí èmi wá sọ Efraimu di ahoro. Nítorí pé èmi ni Ọlọ́run, àní, èmi kì í ṣe ènìyàn. Ẹni mímọ́ láàrín yín, Èmi kò ní í wá nínú ìbínú.
10 Na da Na fi ilia ha lai dunu ilima laione wa: me agoane gogonomomu. Amasea, Na fi da Nama fa: no bobogemu. Ilia da guma: dini esalu, hedolo Nama misunu.
Wọn yóò máa tẹ̀lé Olúwa; òun yóò bú ramúramù bí i kìnnìún. Nígbà tó bá bú, àwọn ọmọ rẹ yóò wá ní ìwárìrì láti ìwọ̀-oòrùn.
11 Ilia da Idibidi ganini, sio agoane hedolo hagili misunu, amola Asilia ganini, ‘dafe’ sio defele hedolo hagili misunu. Na da ilia ilila: diasudafa amoga bu oule misunu. Na, Hina Gode, da sia: i dagoi.”
Wọn ó wá pẹ̀lú ẹ̀rù bí i ẹyẹ láti Ejibiti, bí i àdàbà láti Asiria, Èmi ó mú wọn padà sí ilé wọn,” ni Olúwa wí.
12 Hina Gode da amane sia: sa, “Isala: ili dunu ilia ogogosu hou da Na sisiga: sa. Na da Dafawanedafa amola Hadigi Gode. Be Yuda fi dunu da Nama lelesu hou gebewane hamonana.”
Efraimu tí fi irọ́ yí mi ká ilé Israẹli pẹ̀lú ẹ̀tàn. Ṣùgbọ́n Juda sì dúró ṣinṣin pẹ̀lú Ọlọ́run. Ó sì ṣe olóòtítọ́ sí Ẹni mímọ́ Israẹli.

< Hosia 11 >