< Hosia 1 >

1 Hina Gode da Hosia (Bialai egefe) ema sia: adole i. Amo esoha galu, Asaia, Youdame, A:ihase amola Hesigaia da Yuda dunu fi ilima hina bagade galu. Amola Yelouboua: me (Yihoua: se egefe) da Isala: ili fi amo ilia hina bagade esalu.
Ọ̀rọ̀ Olúwa tí ó tọ Hosea ọmọ Beeri wá ní àkókò ìjọba Ussiah, Jotamu, Ahasi àti Hesekiah; àwọn ọba Juda àti ní àkókò ọba Jeroboamu ọmọ Jehoaṣi ní Israẹli.
2 Hina Gode da bisili Hosia ea lafidili Isala: ili fi ilima adomusa: galea, E da Hosiama amane sia: i, “Di da asili uda lama. Be dia uda da di baligi fa: mu, amola dia mano da dia uda ea hou defele, hame nabasu mano ba: mu. Amo defele, Na fi dunu ilia da Na yolesili, baligi fa: i dagoi.
Nígbà tí Olúwa bẹ̀rẹ̀ sí ní sọ̀rọ̀ láti ẹnu Hosea, Olúwa wí fún un pé, “Lọ, fẹ́ àgbèrè obìnrin kan fún ara rẹ, kí ó sì bí ọmọ àgbèrè fún ọ nípasẹ̀ àwọn ọkùnrin mìíràn, nítorí ilẹ̀ ti ṣẹ ẹ̀ṣẹ̀ àgbèrè púpọ̀ nípa yíyapa kúrò lọ́dọ̀ Olúwa.”
3 Amaiba: le, Hosia da Dibala: ime ea uda mano Gouma amo lai dagoi. Amalalu ela da dunu mano lalelegei.
Nígbà náà ni ó sì lọ, ó sì fẹ́ Gomeri ọmọbìnrin Diblaimu, ọmọbìnrin náà sì lóyún, ó sì bí ọmọkùnrin kan fún un.
4 Amalalu, Hina Gode da Hosiama amane sia: i, “Dia mano ea dio Yeseliele asulima. Bai Na da gadenenewane Isala: ili hina bagade ema se nabasu bagade imunu. Amo se imunu ea bai da ea aowa Yihiu da musa: Yeseliele moilai bai bagadega dunu bagohame medole lelegei. Na da Yihiu ea fi ouligisu hou dagolesimu.
Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Hosea pé, “Pe orúkọ ọmọ náà ní Jesreeli, nítorí pé láìpẹ́ ni èmi yóò jẹ ìdílé Jehu ní ìyà fún ẹ̀jẹ̀ àwọn ènìyàn tó pa ní ìpakúpa ní Jesreeli, Èmi yóò sì mú ìjọba Israẹli wá sí òpin.
5 Amola amo esoha, Na da Yeseliele Fago ganodini, Isala: ili fi ilia gegemusa: sasanega: nanusu wadela: lesimu.
Ní ọjọ́ náà ni Èmi yóò ṣẹ́ ọrun Israẹli ní àfonífojì Jesreeli.”
6 Gouma da mano eno lalelegei. Waha lalelegei amo da uda mano. Hina Gode da Hosiama amane sia: i, “Ea dio ‘Ema hame asigisa’ asulima. Bai Na da Isala: ili dunu huluanema bu hame asigimu, amola ilia wadela: i hou bu hame gogolema: ne olofomu.
Gomeri sì tún lóyún, ó sì bí ọmọbìnrin kan. Olúwa sọ fún un pé, “Pe orúkọ rẹ̀ ní Lo-ruhama, nítorí pé, Èmi kò ní ṣàánú fún ilé Israẹli mọ́, Èmi kò sì ní dáríjì wọ́n.
7 Be Na da Yuda dunuma asigimu. Na, ilia Hina Gode, da ili gaga: mu. Be amo gaga: su hou Na da gegesu amoga amola gegesu dadi amola gegesu gobihei sedade amola hosiga fila heda: le gegesu dunu, amoga hame hamomu.
Síbẹ̀, èmi yóò ṣàánú fún ilé Juda, èmi ó gbà wọ́n—kì í ṣe nípa ọfà, idà tàbí ogun, ẹṣin tàbí kẹ̀kẹ́ ẹlẹ́ṣin bí kò ṣe nípa Olúwa Ọlọ́run wọn.”
8 Gouma da ea uda mano dodo fisilalu, abula eno agui ba: i. Amalu dunu mano eno lalelegei.
Lẹ́yìn ìgbà tí ó gba ọmú lẹ́nu Lo-ruhama, ó sì lóyún ó sì bí ọmọkùnrin mìíràn. Nígbà náà ni
9 Hina Gode da Hosiama amane sia: i, “Mano ea dio ‘Na fi dunu hame’ amo asulima. Bai wali Isala: ili dunu da Na fi dunu hame. Amola Na da ilia Gode hame.”
Olúwa sì sọ fún un pé, “Pe orúkọ rẹ̀ ní Lo-Ammi, nítorí pé ẹ kì í ṣe ènìyàn mi, èmi náà kì í sì í ṣe Ọlọ́run yín.
10 Isala: ili dunu fi da afadenene hano bega: bosoda: i dialebe agoai ba: mu. Bagadeba: le, idimu da hamedei ba: mu. Wali, Gode da ilima amane sia: sa, “Dili da Na dunu hame,” be eso da misunu amoga E da ilima amane sia: mu, “Dilia da Esalalalusu Gode Ea mano esala.”
“Ṣùgbọ́n àwọn ọmọ Israẹli yóò pọ̀ bí i iyanrìn etí Òkun tí a kò le wọ́n, tí a kò sì le è kà, yóò sì ṣe. Ní ibi tí wọ́n ti sọ fún wọn pé. ‘Ẹ̀yin kì í ṣe ènìyàn mi,’ níbẹ̀ ni a ó ti máa pè wọ́n ní ‘Ọmọ Ọlọ́run alààyè.’
11 Yuda fi dunu amola Isala: ili fi dunu ilia da bu gilisili fi afae hamoi ba: mu. Amola ilia da dunu afae amo ili ouligima: ne ilegemu. Amola ilia fi da bu heda: mu amola ilia soge ganodini hahawane esalumu. Dafawane! Yeseliele ea eso misunu hou da hou bagadedafa ba: mu.”
Àwọn ènìyàn Juda àti àwọn ènìyàn Israẹli yóò parapọ̀, wọn yóò sì yan olórí kan tí yóò jáde láti ilẹ̀ náà, nítorí pé ọjọ́ ńlá ni ọjọ́ Jesreeli yóò jẹ́.

< Hosia 1 >