< Mui 32 >

1 Ya: igobe da logoga ahoanoba, a:igele dunu ilia da ema doaga: i.
Jakọbu sì ń bá ọ̀nà tirẹ̀ lọ, àwọn angẹli Ọlọ́run sì pàdé rẹ̀.
2 Amo ba: beba: le e amane sia: i, “Amo sogebi da Gode Ea Aligibi Sogebi.” Amaiba: le, e da amo sogebi dio asuli amo Ma: ihana: ime.
Nígbà tí Jakọbu rí wọn, ó wí pé, “Àgọ́ Ọlọ́run ni èyí!” Ó sì pe orúkọ ibẹ̀ ni Mahanaimu.
3 Ya: igobe da sia: adole iasu dunu, ili da e bisimusa: , Iso amo gousa: musa: asunasi. Iso da Idome sogega esalu.
Jakọbu sì rán àwọn oníṣẹ́ ṣáájú ara rẹ̀ sí Esau arákùnrin rẹ̀ ni ilẹ̀ Seiri ní orílẹ̀-èdè Edomu.
4 Ya: igobe da sia: adole iasu dunu ilima amane olelei, “Isoma amane sia: ma, ‘Na, Ya: igobe, dia nabasu hawa: hamosu dunu da na hina Isoma sia: iaha. Na da La: iba: nema ouesalu, hedolo hame buhagi be wali buhagisa.
Ó pàṣẹ fún wọn pé, “Èyí ni ẹ̀yin yóò wí fún Esau olúwa mi, Jakọbu ìránṣẹ́ rẹ̀ wí pé, ‘Mo ti ṣe àtìpó lọ́dọ̀ Labani títí ó fi di àsìkò yìí.
5 Na da bulamagau, dougi, sibi, goudi, amola udigili hawa: hamosu dunu gagui gala. Na da di hahawane ba: ma: ne dima sia: adole iaha.’”
Mo ní màlúù, kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, àgùntàn àti ewúrẹ́. Mo tún ni àwọn ìránṣẹ́kùnrin àti ìránṣẹ́bìnrin. Mo ń ránṣẹ́ yìí sí olúwa mi kí èmi le è rí ojúrere rẹ.’”
6 Sia: adole iasu dunu da Ya: igobema bu misini, amane sia: i, “Ninia da dia ola Iso ema doaga: i. E da wali dima doaga: musa: , logoga ahoanebe. E da dunu 400 agoane oule maha.”
Nígbà tí àwọn ìránṣẹ́ náà padà tọ Jakọbu wà, wọ́n wí pé “Esau arákùnrin rẹ ti múra láti wá pàdé rẹ pẹ̀lú irinwó ọkùnrin.”
7 Ya: igobe da beda: i bagade amola da: i dioi. Ema misi dunu, sibi, goudi, bulamagau, amola ga: mele, e da afafane gilisisu aduna hamoi.
Pẹ̀lú ìbẹ̀rù àti ìbànújẹ́ ni Jakọbu fi pín àwọn ènìyàn tí ó wà lọ́dọ̀ rẹ̀ sí ìpín méjì, ó sì pín àwọn ẹran ọ̀sìn, agbo ẹran àti ìbákasẹ bẹ́ẹ̀ pẹ̀lú.
8 E amane dawa: i, “Iso da na bisili gilisisu amoga doagala: ma: ne masea, - amabela: ? - na eno gilisisu da se mae nabawane hobeama: bela: ?”
Nítorí ó rò ó nínú rẹ̀ pé, “Bí Esau bá kọjú ogun sí ìpín kan, ìpín kejì yóò sá àsálà.”
9 Amalalu Ya: igobe da amane sia: ne gadoi, “Na aowa A: ibalaha: me amola na ada Aisage, amo elea Gode! Na sia: nabima! Hina Gode, Di da nama na soge amola na fi dunu amoga buhagima: ne sia: noba, Di da na noga: le fidima: ne sia: i.
Nígbà náà ni Jakọbu gbàdúrà pe, “Ọlọ́run Abrahamu baba mi, àti Ọlọ́run Isaaki baba mi, Olúwa tí ó wí fún mi pé, ‘Padà sí orílẹ̀-èdè rẹ àti sọ́dọ̀ àwọn ìbátan rẹ, èmi yóò sì ṣe ọ́ ní rere,’
10 Na hou da wadela: i, be Di da nama asigi hou noga: idafa olelei. Na da dagulu fawane gaguli, Yodane hano degei, be wali na da buhagili, amo gilisisu aduna gaguiwane bu maha.
èmi kò tilẹ̀ yẹ fún àánú àti òtítọ́ tí o ń fihàn fún ìránṣẹ́ rẹ. Nítorí pé, kìkì ọ̀pá mi ni mo mu kúrò ni ilé kọjá Jordani yìí, ṣùgbọ́n nísinsin yìí, èmi ti di ẹgbẹ́ méjì.
11 Gode! Dia na gaga: ma! Na da na ola Isoba: le bagade beda: i galebe. E da ninima doagala: sa: besa: le amola nini huluane amola uda amola mano wadela: sa: besa: le na da bagade beda: i.
Jọ̀wọ́ Olúwa gbà mí lọ́wọ́ Esau arákùnrin mi, nítorí ẹ̀rù ń bà mí pé yóò wá dojú ìjà kọ mí àti àwọn ìyàwó pẹ̀lú àwọn ọmọ mi.
12 Di da musa: na logo hahamoma: ne sia: i. Amola nama mano idimu hamedei amo sa: i hano wayabo bagade bega: amo idi defele amo imunu sia: i. Amo mae gogolema.”
Ṣùgbọ́n ìwọ ti ṣèlérí pé, ‘Èmi yóò mú ọ gbilẹ̀, èmi yóò sì mú kí àwọn ìran rẹ dà bì í yanrìn òkun tí ẹnikẹ́ni kò le è kà.’”
13 Amo gasi afae amo sogebi esalu, Ya: igobe da ea lai gebo fi mogili, hahawane udigili iasu Isoma imunusa: dawa: i. E da goudi aseme 200, goudi gawali 20, sibi aseme 200, sibi gawali 20, ga: mele aseme dodo maga: me gala 30, amola ilia mano, bulamagau aseme 40, bulamagau gawali 10, dougi aseme 20 amola gawali 10, amo huluane Isoma imunusa: afafai.
Ó sì lo òru ọjọ́ náà níbẹ̀. Ó mú ẹ̀bùn fún Esau arákùnrin rẹ̀ nínú ohun ìní rẹ̀.
Igba ewúrẹ́, ogún òbúkọ, igba àgùntàn, ogún àgbò,
ọgbọ̀n abo ìbákasẹ pẹ̀lú ọmọ wọn, ogójì abo màlúù àti akọ màlúù mẹ́wàá, ogún abo kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ àti akọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ mẹ́wàá.
16 E da gilisisu afae afae hamone, amo afae afaega hawa: hamosu dunu afae ouligima: ne sia: i. E da amane sia: i, “Nama bisili masa. Gilisisu afae asili, dibi yolesima. Amalalu, gilisisu eno amola eno agoaiwane masa.
Ó sì fi wọ́n lé àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ lọ́wọ́ ní ọ̀wọ̀ọ̀wọ́, ó sì wí fún wọn pé, “Ẹ lọ ṣáájú mi, kí ẹ sì jẹ́ kí àlàfo wà láàrín ọ̀wọ́ agbo ẹran kọ̀ọ̀kan sí èkejì.”
17 E da bisili ahoasu hawa: hamosu dunu ilima amane sia: i, “Na ola Iso da dima doaga: sea, e da dima, ‘Dia hina da nowala: ? Di da habi ahoa? Lai gebo fi di da amoga fa: no bobogesa. Amo da nowa eala: ?’ amane adole ba: sea,
Ó pàṣẹ fún èyí tí ó ṣáájú pé, “Nígbà tí arákùnrin mi Esau bá pàdé rẹ tí ó sì béèrè ẹni tí ìwọ í ṣe àti ibi tí ìwọ ń lọ àti ẹni tí ó ni agbo ẹran tí ó wà lọ́dọ̀ rẹ,
18 di agoane adole ima, ‘Amo huluane da dia hawa: hamosu dunu Ya: igobe amo ea: Amo huluane e da ea hina Isoma iaha. Ya: igobe hisu da fa: no maha.’”
nígbà náà ni ìwọ yóò wí pé, ‘Ti ìránṣẹ́ rẹ Jakọbu ni wọ́n. Ẹ̀bùn ni ó sì fi wọ́n ṣe fún Esau olúwa mi, òun pàápàá ń bọ̀ lẹ́yìn wa.’”
19 Ya: igobe da amo sia: defele gilisisu ouligisu dunu ageyadu amola gilisisu ouligisu dunu osoda amola gilisisu ouligisu huluane ilima amo defele olelei. E amane sia: i, “Dilia Isoma amane sia: ma,
Jakọbu sì pàṣẹ bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ fún ọ̀wọ́ kejì àti ẹ̀kẹta àti àwọn tókù tí ó tẹ̀lé agbo ẹran pé, “Ohun kan ṣoṣo yìí náà ni kí ẹ sọ fún Esau nígbà tí ẹ bá pàdé rẹ̀.
20 ‘Defea! Dia hawa: hamosu dunu Ya: igobe da ninima gadenene fa: no maha.’” Ya: igobe da agoane dawa: lalu, “Amabela: ? Na da hahawane udigili iasu ema iasea, e da olofosu ba: ma: bela: ? Amasea, e da na gogolema: ne olofoma: bela: ?”
Kí ẹ rí i dájú wí pé, ẹ sọ fún un pé, ‘Jakọbu ìránṣẹ́ rẹ̀ ń bọ̀ lẹ́yìn wa.’” Èrò Jakọbu ni láti fi àwọn ẹ̀bùn wọ̀nyí tu Esau lójú pé bóyá inú Esau yóò dùn sí òun nígbà tí àwọn bá pàdé.
21 E da amo hahawane udigili iasu bisili asunasi. Amalalu e da amo sogebi abula diasuga esalu.
Nítorí náà ẹ̀bùn Jakọbu ṣáájú rẹ̀ lọ, Jakọbu pàápàá sì lo òru ọjọ́ náà nínú àgọ́.
22 Amo gasia, Ya: igobe da wa: legadole, ea uda aduna, ea gidisedagi uda aduna, ea dunu mano gidayale gala, amo huluane Ya: boge Hano degemusa: oule asi.
Ó sì dìde ní òru ọjọ́ náà, ó mú àwọn aya rẹ̀ méjèèjì, àwọn ìránṣẹ́bìnrin rẹ̀ méjèèjì, àti àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ mọ́kọ̀ọ̀kànlá, wọ́n sì kọjá ní ìwọdò Jabbok.
23 E da amo huluane asunasili, ea liligi huluane asunasi.
Lẹ́yìn ìgbà tí ó ti rán wọn kọjá odò tán sí òkè odò, ó sì rán àwọn ohun ìní rẹ̀ kọjá pẹ̀lú.
24 Be hisu da hame asi. Amalalu, dunu afae da ema misini ema ouga: ne ludui. Ludulalu, gasia huluane mae yolesili, ludui.
Ó sì ku Jakọbu nìkan, ọkùnrin kan sì bá a ja ìjàkadì títí ó fi di àfẹ̀mọ́júmọ́.
25 Ya: igobe da gasa bagadewane ludubiba: le, amo dunu da ema osa: le heda: mu hamedeiwane ba: i. Amaiba: le, e da Ya: igobe ea masele digili ba: beba: le, Ya: igobe ea masele momoge dagai dagoi ba: i.
Ṣùgbọ́n nígbà tí ọkùnrin náà rí i pé òun kò le borí Jakọbu, ó fọwọ́ kàn án ní ọ̀ọ́kán ibi tí eegun itan ti bẹ̀rẹ̀, egungun náà sì yẹ̀ kúrò lórí ike, bí ó ti ń ja ìjàkadì.
26 Amalalu, amo dunu da Ya: igobema amane sia: i, “Nama yolesima! Eso da heda: i dagoi.” Be Ya: igobe da bu adole i, “Di da nama hahawane dogolegele fidimusa: sia: beba: le fawane, na da yolesimu.”
Nígbà náà ni ọkùnrin náà wí fún un pé, “Jẹ́ kí ń máa lọ, nítorí ojúmọ́ ti mọ́.” Ṣùgbọ́n Jakọbu dá a lóhùn pé, “Èmi kò ní jẹ́ kí o lọ, àyàfi bí o bá súre fún mi.”
27 Dunu da Ya: igobema amane adole ba: i, “Dia dio da nowala: ?” E bu adole i, “Ya: igobe!”
Ọkùnrin náà béèrè orúkọ rẹ̀. Ó sì wí fún un pé, “Jakọbu ni òun ń jẹ́.”
28 Amalalu amo dunu da amane sia: i, “Defea! Dia dio da wali Ya: igobe hame. Dia dio da wali Isala: ili. Bai di da Godema amola osobo bagade dunuma ouga: ne ludulalu, hasali dagoi.”
Nígbà náà ni ọkùnrin náà wí pé, “Orúkọ rẹ kì yóò jẹ́ Jakọbu mọ́ bí kò ṣe Israẹli, nítorí pé ìwọ ti bá Ọlọ́run àti ènìyàn jà, o sì borí.”
29 Ya: igobe da amane sia: i, “Dia dio nama adoma!” Be E bu adole i, “Dia da abuliba: le Na dio adole ba: sala: ?” Amalalu, e da amogai Ya: igobema hahawane dogolegele lama: ne sia: i.
Jakọbu sì bẹ ọkùnrin náà pé, “Sọ orúkọ rẹ fún mi.” Ṣùgbọ́n ọkùnrin náà sá à dáhùn pé, “Èéṣe tí o ń béèrè orúkọ mi?” Lẹ́yìn náà ó súre fún Jakọbu níbẹ̀.
30 Amaiba: le, Ya: igobe da amo sogebiga Biniele dio asuli. E amane sia: i, “Bai na da Gode Ea odagi ba: i dagoi, be na hame bogoi.”
Jakọbu sì pe orúkọ ibẹ̀ ní Penieli pé, “Mo rí Ọlọ́run ní ojúkojú, síbẹ̀ a dá ẹ̀mí mi sí.”
31 E da Biniele baligili, eso da heda: i dagoi ba: i. Ea masele momoge dagaiba: le, e da gasuga: igili ahoanu.
Bí ó sì ti ń kọjá Penieli, oòrùn ràn bá a, ó sì ń tiro nítorí itan rẹ̀.
32 Amaiba: le, musa: amola wali Isala: ili dunu da masele momoge huluane hame naha. Bai Biniele sogega musa: Gode da Ya: igobe (Isala: ili) amo ea masele momoge dagai. (Isala: ili dawa: loma: ne da ‘E da Godema ludusa.”)
Ìdí nìyí tí àwọn ọmọ Israẹli kì í fi í jẹ iṣan tí ó wà ní ọ̀ọ́kán ibi tí eegun itan ti bẹ̀rẹ̀ títí di òní olónìí, nítorí níbi iṣan náà ni a ti fọwọ́ kan ibi tí egungun itan Jakọbu ti bẹ̀rẹ̀.

< Mui 32 >