< Mui 17 >

1 A: ibala: me ea lalelegei ode 99 da gidigiloba, Hina Gode da ema misini, amane sia: i, “Na da Gode Bagadedafa. Di da Na hadigi ganodini ahoanoma amola hou moloidafa fawane hamoma.
Ní ìgbà tí Abramu di ẹni ọ̀kàndínlọ́gọ́rùn-ún ọdún, Olúwa farahàn án, ó sì wí pé, “Èmi ni Ọlọ́run alágbára, máa rìn níwájú mi, kí o sì jẹ́ aláìlábùkù.
2 Na da ania gousa: su hamoi amo dafawane hamomu. Na da digaga dunu bagohame dima imunu.”
Èmi yóò sì fi ìdí májẹ̀mú mi múlẹ̀ pẹ̀lú rẹ. Èmi yóò sì sọ ọ́ di púpọ̀ gidigidi.”
3 A: ibala: me da beguduli ea odagiga osobo digila sa: i. Amalalu, Gode da ema amane sia: i,
Abramu sì dojúbolẹ̀, Ọlọ́run sì wí fún un pé.
4 “Na gousa: su dima da agoane. Di da dunu fi bagohame ilima eda agoane ba: mu.
“Ní ti èmi, májẹ̀mú mi pẹ̀lú rẹ nìyí. Ìwọ yóò di baba orílẹ̀-èdè púpọ̀.
5 Na da di dunu fi bagohame ilima eda hamoi dagoiba: le, wali dia dio da A: ibala: me hame, be bu afadenene A: ibalaha: me hamoi dagoi.
A kì yóò pe orúkọ rẹ̀ ní Abramu mọ́, bí kò ṣe Abrahamu, nítorí, mo ti sọ ọ́ di baba orílẹ̀-èdè púpọ̀.
6 Di da mano bagohame lamu. Di da dunu fi bagohame lamu, amola fi hina bagade dunu bagohame di da lamu.
Èmi yóò mú ọ bí si lọ́pọ̀lọ́pọ̀, ọ̀pọ̀ orílẹ̀-èdè ni èmi yóò sì mú ti ara rẹ jáde wá, àwọn ọba pẹ̀lú yóò sì ti inú rẹ jáde.
7 Na gousa: su Na da di amola digaga mano dilima Na da hamomu, da mae dagole dialalalumu. Na da dia Gode esalumu amola digaga mano huluane ilia Gode esalumu.
Èmi yóò sì gbé májẹ̀mú mi kalẹ̀ láàrín tèmi tìrẹ, ní májẹ̀mú ayérayé àti láàrín irú-ọmọ rẹ ní ìran-ìran wọn, láti máa ṣe Ọlọ́run rẹ àti ti irú-ọmọ rẹ lẹ́yìn rẹ.
8 Di da wali Ga: ina: ne soge ganodini ga fi dunu agoane ba: sa. Be amo soge huluane, di eso huluane mae yolesili gagulaloma: ne, Na da di amola dia fa: no lalelegemu manolali dilima imunu. Amola Na da ilia Gode esalumu.”
Gbogbo ilẹ̀ Kenaani níbi tí ìwọ ti ṣe àjèjì ni èmi yóò fi fún ọ àti fún irú-ọmọ rẹ lẹ́yìn rẹ láéláé. Èmi yóò sì jẹ́ Ọlọ́run wọn.”
9 Amalalu, Gode da A: ibalaha: mema amane sia: i, “Be di da Na gousa: su noga: le ouligima. Di amola digaga fa: no lalelegemu fi.
Nígbà náà ni Ọlọ́run wí fún Abrahamu pé, “Ìwọ máa pa májẹ̀mú mi mọ́, ìwọ àti irú-ọmọ rẹ lẹ́yìn rẹ àti àwọn ìran tí ó ń bọ̀.
10 Na gousa: su dima amola dia manolali ilima - amo gousa: su di noga: le agoane ouligima. Dunu huluane dia fi amo ganodini da ilia gadofo damuma: mu.
Èyí ni májẹ̀mú mi pẹ̀lú rẹ àti ìran rẹ lẹ́yìn rẹ, májẹ̀mú tí ẹ̀yin yóò máa pamọ́. Gbogbo ọkùnrin yín ni a gbọdọ̀ kọ ní ilà.
11 Dilia huluane gadofo damuma: mu. Amo da Na gousa: su dilima amo dawa: digima: ne olelesu gala.
Ẹ̀yin yóò kọ ara yín ní ilà, èyí ni yóò jẹ́ àmì májẹ̀mú láàrín tèmi tiyín.
12 Dunu huluane dia fi ganodini fa: no lalelegesea, dunu mano huluane da lalelegesea, eso godoane fisili ilia gadofo damuma: mu. Amo da huluanedafa - dia fi amo ganodini lalelegei amola dunu mano ga fi amoga bidilai, amo huluane.
Ní gbogbo ìran tí ń bọ̀ lẹ́yìn, gbogbo ọkùnrin ni a gbọdọ̀ kọ ni ilà ní ọjọ́ kẹjọ tí a bí wọn, àti àwọn tí a bí ní ilé rẹ, tàbí tí a fi owó rà lọ́wọ́ àwọn àjèjì, àwọn tí kì í ṣe ọmọ rẹ̀. Èyí yóò sì jẹ́ májẹ̀mú láéláé tí yóò wà láàrín Èmi àti irú-ọmọ rẹ.
13 Dia fi amo ganodini lalelegei o ga fi ilima bidi lai - huluane. Na gousa: su defei dilia hu amo ganodini hamoi da eso huluane mae dagole dialalalumu. Amo da Na dilima gousa: su hamoi dagoi olelesa.
Ìbá à ṣe ẹni tí a bí nínú ilé rẹ, tàbí ẹni tí o fi owó rà, a gbọdọ̀ kọ wọ́n ní ilà; májẹ̀mú mí lára yín yóò jẹ́ májẹ̀mú ayérayé.
14 Be nowa dunu da dia fi amo ganodini ea hu gadofo hame damui ba: sea, amo dunu da Na gousa: su fi dagoiba: le, fadegale fasima.”
Gbogbo ọmọkùnrin tí kò bá kọ ilà, tí a kò kọ ní ilà abẹ́, ni a ó gé kúrò láàrín àwọn ènìyàn rẹ̀, nítorí pé ó da májẹ̀mú mi.”
15 Gode da A: ibalaha: mema eno amane sia: i, “Dia uda Selai ema Selai dio bu mae sia: ma. Ea dio da wali Sela.
Ọlọ́run wí fún Abrahamu pé, “Ní ti Sarai, aya rẹ̀, ìwọ kì yóò pè é ní Sarai mọ́, bí kò ṣe Sara.
16 Na da ema hahawane dogolegele ilegemu. Amola e da diagofe lalelegemu. E da dunu fi bagohame ilima eme esalumu. Dunu fi hina dunu bagohame da ema lalelegemu.”
Èmi yóò bùkún fún un, èmi yóò sì fun ọ ní ọmọkùnrin kan nípasẹ̀ rẹ̀. Èmi yóò bùkún un, yóò sì di ìyá àwọn orílẹ̀-èdè, àwọn ọba àwọn orílẹ̀-èdè yóò sì ti ara rẹ̀ jáde wá.”
17 A: ibalaha: me da beguduli ea odagiga osobo digila sa: ili, hahawane bagade ousu. E da ea dogo ganodini amane sia: i, “Dunu da 100 ode lai, amo mano lamu da defelela: ? Sela amola da ode 90 lai dagoiba: le, mano lama: bela: ?”
Abrahamu sì dojúbolẹ̀, ó rẹ́rìn-ín, ó sì wí fún ara rẹ̀ pé, “A ó ha bí ọmọ fún ẹni ọgọ́rùn-ún ọdún? Sara tí í ṣe ẹni àádọ́rùn-ún ọdún yóò ha bímọ bí?”
18 E da Godema amane adole ba: i, “Isiama: ile da na fi ganodini na sogebi lamu da defeala: ?”
Abrahamu sì wí fún Ọlọ́run pé, “Sá à jẹ́ kí Iṣmaeli kí ó wà láààyè lábẹ́ ìbùkún rẹ.”
19 Be Gode bu adole i, “Hame mabu! Dia uda Sela da dia manodafa dia da: i amoga hamoi, amo lalelegemu. Di da ema Aisage dio asulima. Na da Na gousa: su ema amola egaga mano ilima hamoi, amo hamedafa yolesimu. Amo gousa: su da mae dagole eso huluane dialalalusu liligi.
Nígbà náà ni Ọlọ́run wí pé, “Mo gbọ́, ṣùgbọ́n Sara aya rẹ̀ yóò bí ọmọkùnrin kan fún ọ, ìwọ yóò sì pe orúkọ rẹ̀ ní Isaaki, èmi yóò fi ìdí májẹ̀mú mi múlẹ̀ pẹ̀lú rẹ̀ ní májẹ̀mú ayérayé àti àwọn irú-ọmọ rẹ̀ lẹ́yìn rẹ̀.
20 Dia adole ba: su amo Isiama: ile fidima: ne Na da nabi dagoi. Amaiba: le, Na da ema amola hahawane dogolegele ilegemu. Na da ema mano bagohame imunu. Ema da fi hina bagade dunu fagoyale amo lalelegemu, amola ea mano da dunu fi bagadedafa hamomu.
Ṣùgbọ́n ní ti Iṣmaeli, mo gbọ́ ohun tí ìwọ wí, èmi yóò bùkún fún un nítòótọ́, èmi ó sì mú un bí sí i, yóò sì pọ̀ sí i, òun yóò sì jẹ́ baba fún àwọn ọmọ ọba méjìlá, bẹ́ẹ̀ ni èmi yóò sì sọ ọ́ di orílẹ̀-èdè ńlá.
21 Be Na gousa: sudafa da dia mano Aisage ema dialumu. Waha oubi wewaba amo ode enoga e da Selama lalelegemu.”
Ṣùgbọ́n èmi yóò fi ìdí májẹ̀mú mi múlẹ̀ pẹ̀lú Isaaki, ẹni tí Sara yóò bí fún ọ ni ìwòyí àmọ́dún.”
22 Gode da A: ibalaha: mema sia: i dagoiba: le, yolesili asi.
Nígbà tí ó ti bá Abrahamu sọ̀rọ̀ tán, Ọlọ́run sì gòkè lọ kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀.
23 Amo esoga A: ibalaha: me da hedolo nabasu hou hamoi. E da Isiama: ile amola ea fi dunu huluane amola dunu da ea fi amo ganodini lalelegei amola udigili hawa: hamosu dunu e bidi lai, amo huluane ilia gadofo damui.
Ní ọjọ́ náà gan an ni Abrahamu mú Iṣmaeli ọmọ rẹ̀ àti àwọn ẹrú tí a bí ní ilé rẹ̀ àti àwọn tí ó fi owó rà, ó sì kọ wọ́n ní ilà. Bẹ́ẹ̀ ni ó sì kọ gbogbo ọkùnrin tí ń bẹ ní ilé rẹ̀ ní ilà gẹ́gẹ́ bí àṣẹ Ọlọ́run.
24 A: ibalaha: me da lalelegele, ode 99 doaga: le, gadofo damui.
Abrahamu jẹ́ ẹni ọ̀kàndínlọ́gọ́rùn-ún ọdún nígbà tí a kọ ọ́ ní ilà.
25 Amola Isiama: ile da ea ode 13 amoga gadofo damui ba: i.
Iṣmaeli ọmọ rẹ̀ jẹ́ ẹni ọdún mẹ́tàlá.
26 A: ibalaha: me amola egefe Isiama: ile ela da eso afae ganodini gadofo damui.
Ní ọjọ́ náà gan an ni a kọ Abrahamu ní ilà pẹ̀lú Iṣmaeli ọmọ rẹ̀ ọkùnrin.
27 Amola dunu huluane A: ibalaha: me ea sosogo fi ganodini-amo da ea fi ganodini lalelegei, amola ga fi dunu e da bidilai dagoi-huluane da e amola gilisili gadofo damui ba: i.
Àti gbogbo ọkùnrin tí ó wà ní ilé Abrahamu, ìbá à ṣe èyí tí a bí ní ilé rẹ̀ tàbí èyí tí a fi owó rà lọ́wọ́ àlejò ni a kọ ní ilà pẹ̀lú rẹ̀.

< Mui 17 >