< Mui 15 >

1 Amo hou fa: no, A:ibala: me da Gode sia: esala ba: su ganodini nabi. Gode da amane sia: i, “A: ibala: me! Mae beda: ma! Na da dima Gaga: su esala. Na da dima baligili bidi ida: iwane imunu.”
Lẹ́yìn èyí, ọ̀rọ̀ Olúwa tọ Abramu wá lójú ìran pé, “Abramu má ṣe bẹ̀rù. Èmi ni ààbò rẹ, Èmi sì ni èrè ńlá rẹ.”
2 Be A: ibala: me da bu adole i, “Ouligisu Hina Bagadedafa! Di da nama habodane ima: bela: ? Na da mano hame lai. Na bogosea, na hawa: hamosu dunu, Dama: sagase dunu amo Elia: isa amo da na nana liligi huluane lamu.”
Ṣùgbọ́n Abramu wí pé, “Olúwa Olódùmarè, kí ni ìwọ yóò fi fún mi níwọ̀n ìgbà tí èmi kò bímọ, Elieseri ará Damasku ni yóò sì jogún mi,”
3 Amola A: ibala: me amane sia: i, “Di da mano nama hame iba: le, na hawa: hamosu dunu fawane da na nana liligi huluane lamu.”
Abramu sì tún tẹ̀síwájú pé, “Ìwọ kò fún mi ní ọmọ, nítorí náà ẹrú nínú ilé mi sì ni yóò jẹ́ àrólé mi.”
4 Amalalu, Hina Gode Ea sia: ema amane misi, “Amo dunu da dia nana liligi hamedafa lamu. Be diagofedafa amo dia da: i hodo hamoi, hi fawane da dia nana liligi lamu.”
Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tún tọ̀ ọ́ wá pé, “Ọkùnrin yìí kọ́ ni yóò jẹ́ àrólé rẹ bí kò ṣe ọmọ tí ìwọ bí fúnra rẹ̀ ni yóò jẹ́ àrólé rẹ.”
5 Gode da A: ibala: me gadili oule asili, amane sia: i, “Muagado ba: legadoma! Gasumuni idima! Be huluane idimu da hamedei.” Amalalu, E da ema amane sia: i, “Dia mano ilia da amo gasumuni ilia idi defele ba: mu.”
Olúwa sì mú Abramu jáde sí ìta ó sì wí fún un pé, “Gbé ojú sókè sí ọ̀run kí o sì ka àwọn ìràwọ̀ bí ó bá ṣe pé ìwọ le è kà wọ́n.” Ó sì wí fun un pé, “Nítorí náà, báyìí ni irú-ọmọ rẹ yóò rí.”
6 A: ibala: me da Hina Gode dafawaneyale dawa: i galu. Amaiba: le, Gode da A: ibala: me ea hou moloidafa hamoi defele ba: i.
Abramu gba Olúwa gbọ́, a sì kà á sí òdodo fún un.
7 E da bu A: ibala: mema amane sia: i, “Na da Hina Godedafa. Na da di Ga: ladia fi moilai bai bagade E, amoga fisili masa: ne, amo soge lalegagumusa: guiguda: oule misi.”
Ó sì tún wí fún un pé, “Èmi ni Olúwa tí ó mú ọ jáde láti Uri ti Kaldea láti fún ọ ní ilẹ̀ yìí láti jogún.”
8 Be A: ibala: me amane sia: i, “Hina Gode Ouligisudafa! Na da amo soge lalegagumusa: habodane dawa: ma: bela: ?”
Ṣùgbọ́n Abramu wí pé, “Olúwa Olódùmarè, báwo ni mo ṣe lè mọ̀ pé ilẹ̀ náà yóò jẹ́ ohun ìní mi?”
9 Amaiba: le, Hina Gode da ema amane sia: i, “Di bulamagau aseme, goudi amola sibi gawali amo huluane da ode osodoyale baligi, amo gaguli misa. Amola ‘dafe’ sio amola musuni sio gaguli misa.
Nítorí náà, Olúwa wí fún un pé, “Mú abo màlúù, ewúrẹ́ àti àgbò ọlọ́dún mẹ́ta mẹ́ta wá, àti àdàbà kan àti ọmọ ẹyẹlé kan.”
10 A: ibala: me da amo liligi huluane gaguli misini, dogoa oudahida: le, la: idi afae la: idili ligisili, eno afae eno la: idili legei. Be sio e da dogoa hame oudahida: i.
Abramu sì mú gbogbo nǹkan wọ̀nyí wá, ó sì là wọ́n sí méjì méjì, ó sì fi ẹ̀là èkínní kọjú sí èkejì, ṣùgbọ́n kò la àwọn ẹyẹ ní tiwọn.
11 Amalalu, gasa bagade sio buhiba eno ilia da amo liligi wamolamusa: misi. Be A: ibala: me da amo sio sefasi.
Àwọn ẹyẹ igún sì ń wá sórí òkú ẹran náà, Abramu sì ń lé wọn.
12 Eso da daloba, A:ibala: me da golai nanabunina asi ba: i. Amoga e da gasi dunasi bagade ba: beba: le, bagadewane beda: i galu.
Bí oòrùn ti ń wọ̀, Abramu sùn lọ fọnfọn, òkùnkùn biribiri tí ó kún fún ẹ̀rù sì bò ó.
13 Amalalu, Hina Gode da ema amane sia: i, “Hou noga: le dawa: ma! Dia fa: no lalelegemu fi da eno dunu ilia soge ganodini, udigili hawa: hamosu dunu agoane esalumu. Ode 400 agoane, ilia da amo soge ganodini se nabawane esalumu.
Nígbà náà ni Olúwa wí fún Abramu pé, “Mọ èyí dájú pé, irú-ọmọ rẹ yóò ṣe àtìpó ní ilẹ̀ àjèjì, wọn ó sì sọ wọn di ẹrú, wọn ó sì pọ́n wọn lójú fún irinwó ọdún.
14 Be Na da fa: no ilima se iabe dunu fi ilima se iasu bidi imunu. Dia fi da fa: no amo soge yolesili, gadili masunu. Ilia da liligi bagade gagumu.
Ṣùgbọ́n orílẹ̀-èdè náà tí wọn yóò máa sìn, ni èmi ó dá lẹ́jọ́, lẹ́yìn náà ni wọn ó sì jáde pẹ̀lú ọrọ̀ púpọ̀.
15 Be di da ode bagohame esalu, gagoalumu, olofoiwane dia aowalali amoga bu masunu. Dia da: i hodo da bogole, uli dogoi ganodini ba: mu.
Ṣùgbọ́n ìwọ yóò tọ àwọn baba rẹ lọ ni àlàáfíà, bẹ́ẹ̀ ni ìwọ yóò sì di arúgbó kí a tó gbé ọ sin.
16 Be dia fi da asili, fi biyaduyale fifilai dagosea, ilia da guiguda: bu misunu. A: moulaide dunu ilia wadela: i hou da Na se iasu defei lama: ne amoga hame doaga: iba: le, dia fi da ode agoane aligili, bu misunu.
Ní ìran kẹrin àwọn ìran rẹ yóò padà wá sí ibi. Nítorí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn ará Amori kò ì tí ì kún òsùwọ̀n.”
17 Eso da gudu sa: i dagoi, amola gasi da doaga: loba, ganagu amoga mobi heda: lebe ba: i amola hanu gadodili nene, amo da lai gebo hu dadega: i gilisisu amo ganodini udigili asi.
Nígbà tí oòrùn wọ̀ tí ilẹ̀ sì ṣú, ìkòkò iná tí ń ṣèéfín àti ọwọ́ iná sì ń kọjá láàrín ẹ̀là ẹran náà.
18 Amo esoga, Hina Gode da A: ibala: mema gousa: su hamoi. E amane sia: i, “Soge amo ea defei da Idibidi hano asili hano bagadedafa ea dio amo Iufala: idisi amoga doaga: le, amo soge huluane Na da dia mano fi ilima iaha.
Ní ọjọ́ náà gan an ni Olúwa dá májẹ̀mú pẹ̀lú Abramu, ó sì wí pé, “Àwọn ìran rẹ ni èmi yóò fi ilẹ̀ yìí fún, láti odò Ejibiti dé odò ńlá Eufurate:
19 Amo soge ganodini dunu fi esalebe da Ginaide, Genisaide, Gadamunaide,
ilẹ̀ àwọn ará Keni, àti ti ará Kenissiti, àti ará Kadmoni,
20 Hidaide, Belisaide, Lefa: ide,
àti ti ará Hiti, àti ti ará Peresi, àti ti ará Refaimu.
21 A: moulaide, Ga: ina: naide, Gegasaide amola Yebusaide - amo dunu fi huluane ilia soge, Na da digaga fi ilima imunu.”
Àti ti ará Amori, àti ti ará Kenaani, àti ti ará Girgaṣi àti ti ará Jebusi.”

< Mui 15 >