< Isigiele 35 >

1 Hina Gode da nama amane sia: i,
Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá:
2 “Dunu egefe! Idome fi ilima fofada: ma!
“Ọmọ ènìyàn kọjú sí òkè Seiri; sọtẹ́lẹ̀ sí i,
3 Na, Ouligisudafa Hina Gode, Na sia: ilima alofele olelema, amane, ‘Idome goumi! Na da dilia ha lai. Na da dili gugunufinisimu.
kí o sì sọ wí pé, ‘Èyí ni Olúwa Olódùmarè wí: Èmí lòdì sí ọ, òkè Seiri, Èmi yóò sì na ọwọ́ mi síta ní ìlòdì sí ọ, èmi yóò sì mú kí ó di ahoro.
4 Na da dilia moilai amola soge huluane wadela: lesimu. Amasea, dilia da Na da Hina Gode dawa: mu.
Èmi yóò pa àwọn ìlú rẹ run, ìwọ yóò sì di ahoro. Nígbà náà ni ìwọ yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa.
5 Dilia da eso huluane Isala: ili fi ilima ha laiwane esalu. Amola Isala: ili fi da ilia dagomusa: se bidi laloba, amo esoga dilia da Isala: ili hame fidi, be udigili Isala: ili fi dunu huluane medole legelalu ba: i.
“‘Nítorí ìwọ dá ààbò bo ọ̀tẹ̀ àtayébáyé, tí ìwọ sì fi Israẹli lé idà lọ́wọ́, ní àsìkò ìdààmú wọn, ní àsìkò tí ìjìyà wọn dé góńgó,
6 Amaiba: le, Na, Ouligisudafa Fifi Ahoanusu Hina Gode da Na Dioba: le amane sia: sa, ‘Dilia da bogomu. Hobeale masunu da hamedei. Dilia da fane legesu hou hamonanu, amola dilia fane legesu hou amoga bogomu.
nítorí náà bi mo ti wà láààyè, ni Olúwa Olódùmarè wí, èmi yóò fi ọ kalẹ̀ fún ìtàjẹ̀ sílẹ̀, ìtàjẹ̀ sílẹ̀ yóò sì lépa rẹ. Níwọ́n ìgbà tí ìwọ kò ti kórìíra ìtàjẹ̀ sílẹ̀, ìtàjẹ̀ sílẹ̀ yóò sì lépa rẹ.
7 Na da Idome agolo soge gugunufinisimu, amola nowa amodili ahoasea, amo medole legemu.
Èmi yóò mú kí òkè Seiri di ahoro; ọ̀fọ̀ gbogbo àwọn tí ó ń lọ tí ó ń bọ̀ ní èmi yóò gé kúrò lára rẹ.
8 Na da goumi huluane amo bogoi da: i hodo amoga dedebolesimu, amola agolo amola fago amoga dunu da gegesu ganodini bogoi, ilia da: i hodo dedebolesimu.
Èmi yóò fi àwọn tí a pa kún orí òkè rẹ, àwọn tí a fi idà pa yóò ṣubú ní orí òkè rẹ, àti ní àárín àwọn òkè rẹ.
9 Na eso huluane agoaiwane dialoma: ne, dili wadela: lesimu amola dilia moilai amo ganodini fa: no, dunu da hamedafa esalebe ba: mu.
Èmi yóò mú kí ó di ahoro títí láé, kò ní sí olùgbé ní ìlú rẹ. Nígbà náà ni ìwọ yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa.
10 Na, Hina Gode da Isala: ili fi amola Yuda fi ela Gode esala. Be dilia da giadofale, amo fi aduna amola ela soge huluane, da dilia soge dialoma: ne sia: i.
“‘Nítorí tí ìwọ sọ pé, “Àwọn orílẹ̀-èdè àti ilẹ̀ méjì wọ̀nyí yóò jẹ́ tiwa, àwa yóò sì gbà wọ́n ní ìní,” bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, Èmi Olúwa wà níbẹ̀,
11 Amaiba: le, Na, Ouligisudafa Hina Gode, Na da Fifi Ahoanusu Godeba: le, amane sia: sa, ‘Na da dilia ougi hou amola mudasu amola Na fi ilima higasu hou, amoba: le Na da dilima dabe imunu. Amola Na fi dunu ilia da amane dawa: mu. Na da dilima se bidi iabe ea bai da dilia Na fi ilima wadela: le hamoi.
nítorí náà níwọ̀n ìgbà tí mo ti wà láààyè, ní Olúwa Olódùmarè wí, èmi yóò hùwà sí ọ ní ìbámu pẹ̀lú ìbínú àti owú tí o fihàn nínú ìkórìíra rẹ sí wọn, èmi yóò fi ara mi hàn ní àárín wọn, nígbà tí mo bá ṣe ìdájọ́ rẹ.
12 Dilia da higale agoane sia: i, ‘Isala: ili goumi da wadela: lesi dagoi. Amola dilia amo na dagomu da defea, sia: i. Be Na, Hina Gode, da amo sia: nabi. Amola, dilia da Na se dabe iasu ba: sea, amo dawa: mu.
Nígbà náà ni ìwọ yóò mọ̀ pé, Èmi Olúwa ti gbọ́ gbogbo ohun ẹ̀gàn tí ìwọ ti sọ lòdì sí àwọn òkè Israẹli náà. Ìwọ wí pé, “A sọ wọ́n di ahoro, a sì fi wọ́n fún wa láti run.”
13 Dilia da Nama nimi bagade hidale sia: i. Amola amo hidale gasa fi sia: , Na da nabi.”
Ìwọ lérí sí mi, ó sì sọ̀rọ̀ lòdì sí mí láìsí ìdádúró, èmi sì gbọ́ ọ.
14 Ouligisudafa Hina Gode da amane sia: sa, “Na da dili baligili wadela: lesisia, osobo bagade fifi asi gala huluane da dilia dafai ba: beba: le, nodomu.
Èyí ni Olúwa Olódùmarè wí: Nígbà tí gbogbo ayé bá ń yọ̀, èmi yóò mú kí ó di ahoro.
15 Dilia da Isala: ili (Na fi amola Na soge) ea wadela: lesisu ba: beba: le, nodosu, amo defele ilia da dilia dafai ba: beba: le, nodomu. Sie goumi amola Idome soge huluane da baligili wadela: lesi dagoi ba: mu. Amasea, dunu huluanedafa da Na da Hina Gode dawa: mu.”
Nítorí pé ìwọ ń yọ̀ nígbà tí ìní ilé Israẹli di ahoro, bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni èmi yóò ṣe hùwà sí ọ. Ìwọ yóò di ahoro, ìwọ òkè Seiri, ìwọ àti gbogbo ará Edomu. Nígbà náà, wọn yóò mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa.’”

< Isigiele 35 >