< Isigiele 34 >

1 Hina Gode da nama amane sia: i,
Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ́ mi wá:
2 “Dunu egefe! Isala: ili sibi ouligisu dunu ilima mimogoa fofada: ma. Na, Ouligisudafa Hina Gode, Na sia: ilima adosima, ‘Dilia Isala: ili sibi ouligisu dunu! Dilia da wadela: lesi dagoi ba: mu. Dilia da dilila: hou noga: le ouligisa be sibi hamedafa ouligisa.
“Ọmọ ènìyàn, fi àsọtẹ́lẹ̀ tako Olùṣọ́-àgùntàn Israẹli; sọtẹ́lẹ̀ fún wọn pé: ‘Èyí yìí ni Olúwa Olódùmarè wí: Ègbé ni fún olùṣọ́-àgùntàn Israẹli tí ó ń tọ́jú ara wọn nìkan! Ṣé ó dára kí olùṣọ́-àgùntàn ṣaláì tọ́jú agbo ẹran?
3 Dilia da sibi dodo maga: me naha. Dilia da ilia hinabo amoga abula hamoi ga: sa amola sibi noga: idafa medole naha. Be sibi hamedafa ouligisa.
Ìwọ jẹ wàrà. O sì wọ aṣọ olówùú sí ara rẹ, o sì ń pa ẹran tí ó wù ọ́, ṣùgbọ́n ìwọ kò tọ́jú agbo ẹran.
4 Dilia gasa hamedei sibi hame ouligisu. Dilia da oloi galea hame uhinisisu amola fofa: ginisi amo hame la: gisu, amola udigili ahoasu bu hame oule masu, amola sibi fisi amo hame hogoi helesu. Be amomane, dilia da sibi mi hanane sediginisisa ouligisu.
Ìwọ kò ì tí ì mú aláìlágbára lára le tàbí wo aláìsàn sàn tàbí di ọgbẹ́ fún ẹni tí o fi ara pa. Ìwọ kò í tí ì mú aṣáko padà tàbí wá ẹni tí ó nù. Ìwọ ṣe àkóso wọn ní ọ̀nà lílé pẹ̀lú ìwà òǹrorò.
5 Dilia sibi noga: le hame ouligibiba: le, ilia da afagogole, amola sigua ohega medole mai dagoi ba: i.
Nítorí náà wọn fọ́n káàkiri nítorí àìsí olùṣọ́-àgùntàn, nígbà tí wọ́n fọ́nká tán wọn di ìjẹ fún gbogbo ẹranko búburú.
6 Amaiba: le, Na sibi da hisu agologa amola goumiba: le udigili doulasi. Ilia da osobo bagade da: iya afagogole asili, amola enoga ili hame hogole ba: i.
Àgùntàn mi n rin ìrìn àrè kiri ní gbogbo àwọn òkè gíga àti òkè kékeré. A fọ́n wọn ká gbogbo orí ilẹ̀ ẹni kankan kò sì wá wọn.
7 Wali, sibi ouligisu dilia! Nabima! Na, Hina Gode, Na sia: be amo nabima.
“‘Nítorí náà, ìwọ olùṣọ́-àgùntàn, gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa.
8 Na, Dafawanedafa Fifi Ahoanusu Gode da Na Dioba: le, dilima nabima: ne sia: sa. Na sibi da ouligisu hameba: le, sigua ohega fane mai dagoi ba: i. Na sibi ouligisu dunu da Na sibi amo hame hogosu. Ilia da ilila: musu, ilia hou fawane ouligisu amola sibi gogolei.
Níwọ́n ìgbà tí mo wà láààyè ní Olúwa Olódùmarè wí, nítorí pé agbo ẹran mi kò ní olùṣọ́-àgùntàn nítorí tí a kọ̀ wọ́n, tì wọ́n sì di ìjẹ fún ẹranko búburú gbogbo àti pé, nítorí tí àwọn olùṣọ́-àgùntàn mi kò ṣe àwárí agbo ẹran mi, ṣùgbọ́n wọn ń ṣe ìtọ́jú ara wọn dípò ìtọ́jú agbo ẹran mi,
9 Amaiba: le, dilia sibi ouligisu dunu, Na sia: nabima!
nítorí náà, ẹ̀yin olùṣọ́-àgùntàn, gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa.
10 Na, Ouligisudafa Hina Gode, Na da dilia ha lai dunu sia: sa. Na da Na sibi diliga bu samogemu. Amola dilia ouligisu logo Na da hedofamu. Dilia da bu hamedafa Na sibi ouligimu. Amola dilila: musu ouligisu hou, amo Na da hedofamu. Dilia da agoane bu hamedafa hamomu. Na da Na sibi dili bu hame fane moma: ne, dilima fadegale, gaga: mu.”
Èyí yìí ni Olúwa Olódùmarè wí: Èmi ṣe ìlòdì sí àwọn Olùṣọ́-àgùntàn, èmi yóò sì béèrè agbo ẹran mi lọ́wọ́ wọn. Èmi yóò sì mú wọn dẹ́kun àti máa darí agbo ẹran mi, tí àwọn olùṣọ́-àgùntàn náà kò sì ní lè bọ́ ara wọn mọ́. Èmi yóò gba agbo ẹran mi kúrò ni ẹnu wọn, kì yóò sì jẹ́ oúnjẹ fún wọn mọ́.
11 “Na, Ouligisudafa Hina Gode, da dilima amane sia: sa, ‘Na Nisu fawane da Na sibi hogole ba: sea, noga: le ouligimu.
“‘Nítorí èyí ni Olúwa Olódùmarè wí: Èmi fúnra mi yóò wá àgùntàn mi kiri, èmi yóò sì ṣe àwárí wọn.
12 Sibi ouligisu da ea sibi amo afagogoi amo gilisili, bu oule ahoanu, noga: le ouligisa, amo defele Na da Na fi dunu huluane amo da gasi bidi hamosu esoga, sogebi huluane amoga afagogoi ba: i, amoga lale, bu oule misini, noga: le ouligimu.
Gẹ́gẹ́ bí olùṣọ́-àgùntàn ṣe fojú tó agbo ẹran rẹ̀ tí ó fọ́nká nígbà tí ó wà pẹ̀lú wọn, bẹ́ẹ̀ ni èmi yóò ṣe fojú tó àgùntàn mi. Èmi yóò gbá wọn kúrò ni gbogbo ibi tí wọ́n fọ́nká sí ni ọjọ́ ìkùùkuu àti òkùnkùn.
13 Na da ga fi soge amoga ili fadegale, ili gilisili, ilia sogedafa amoga bu oule misunu. Na da Isala: ili goumi amola hano noga: i amoga oule misunu, amola gisi noga: i ili moma: ne olelemu.
Èmi yóò mú wọn jáde kúrò ní àwọn orílẹ̀-èdè, èmi yóò sì kó wọn jọ láti inú àwọn ìlú, èmi yóò sì mú wọn wá sí ilẹ̀ ara wọn. Èmi yóò mú wọn jẹ ni orí àwọn òkè gíga Israẹli, ni àárín àwọn òkè àti ní gbogbo ibùdó ilẹ̀ náà.
14 Ilia da mae beda: iwane gaga: iwane, goumia amola fagoga amola umiga hahawane gisi moma: ne, Na da ili ouligimu.
Èmi yóò ṣe ìtọ́jú wọn ní pápá oko tútù dáradára, àní orí àwọn òkè gíga ti Israẹli ni yóò jẹ́ ilẹ̀ ìjẹ koríko wọ́n. Níbẹ̀ wọn yóò dùbúlẹ̀ ní ilẹ̀ ìjẹ koríko dídára, níbẹ̀ wọn yóò jẹun ní pápá oko tútù tí ó dara ní orí òkè ti Israẹli.
15 Na, Nisu fawane da Na sibi ouligisu dunu esalumu. Amola, ilia helefima: ne, Na da soge hogole ba: mu. Na, Ouligisudafa Hina Gode da sia: i dagoi.
Èmi fúnra mi yóò darí àgùntàn mi, èmi yóò mú wọn dùbúlẹ̀, ni Olúwa Olódùmarè wí.
16 Na da sibi fisi amo hogole ba: mu. Na da udigili dadoulasi sibi bu oule misunu. Na da oloi galea sibi uhinisimu. Be sibi amo da sefena amola gasa bagade, amo Na da gugunufinisimu. Bai Na da moloidafa hamobe sibi ouligisu dunu esala.
Èmi yóò ṣe àwárí àwọn tí ó nú, èmi yóò mú àwọn tí ó ń rin ìrìn àrè kiri padà. Èmi yóò di ọgbẹ́ àwọn tí ó fi ara pa, èmi yóò sì fún àwọn aláìlágbára ni okun, ṣùgbọ́n àwọn tí ó sanra tí ó sì ni agbára ní èmi yóò parun. Èmi yóò ṣe olùṣọ́ àwọn agbo ẹran náà pẹ̀lú òdodo.
17 Wali, Na sibi wa: i! Na, Ouligisudafa Hina Gode, da dilima Na hamomu olelemu. Na da dili afae afae amoma fofada: nanu dili afafamu. Noga: i mogili gamu, amola wadela: i na: iyado mogili gamu. Sibi da mogili gamu amola goudi da hisu na: iyado mogili gamu.
“‘Ní tìrẹ, agbo ẹran mi, èyí yìí ni Olúwa Olódùmarè wí: Èmi yóò ṣe ìdájọ́ láàrín àgùntàn kan àti òmíràn, àti láàrín àgbò àti ewúrẹ́.
18 Dilia mogili da gisi noga: idafa nabeba: le, hame sadisa. Be gisi noga: i amo dilia hame mai gala, amo dilia da emoga osa: gili, wadela: lesisa. Dilia da hano noga: i amo nanu, bu hano diala amo uba: genesili, wadela: lesisa.
Ṣé oúnjẹ jíjẹ ní pápá oko tútù dídára kò tó yín! Ṣé ó jẹ́ dandan fún ọ láti fi ẹsẹ̀ tẹ pápá oko tútù rẹ tí ó kù? Ṣé omi tí ó tòrò kò tó fún yín ní mímu? Ṣe dandan ni kí ó fi ẹrẹ̀ yí ẹsẹ̀ yín?
19 Na sibi eno da gisi amo dilia da osa: gili wadela: lesi amo fawane naha, amola hano amo dilia uba: genesili wadela: lesi amo fawane nasu dawa:
Ṣé dandan ni kí agbo ẹran mi jẹ́ koríko tí ẹ ti tẹ̀ mọ́lẹ̀, kí wọn sì mú omi tí wọ́n ti fi ẹsẹ̀ wọn sọ di ẹrẹ̀?
20 Amaiba: le, wali, Na, Ouligisudafa Hina Gode da dilima amane sia: sa, ‘Na da dili gasa fi sibi dilima amola gasa hamedei sibi ilima afaeafae fofada: mu.
“‘Nítorí náà, èyí yìí ni Olúwa Olódùmarè wí fún wọn: Wò ó, èmi fúnra mi yóò ṣe ìdájọ́ láàrín àgùntàn tí ó sanra àti èyí tí ó rù.
21 Dilia gasa fi sibi da oloi gasa hamedei sibi amo sibi wa: i bega: fuli fasi dagoi.
Nítorí ti ìwọ sún síwájú pẹ̀lú ìhà àti èjìká, tí ìwọ sì kan aláìlágbára àgùntàn pẹ̀lú ìwo rẹ títí ìwọ fi lé wọn lọ,
22 Be Na da Na sibi gaga: mu, amola eno ilima bu mae wadela: ma: ne gaga: mu. Na da Na sibi ilima afaeafae fofada: nanu, noga: i mogili gamu amola wadela: i na: iyado mogili gamu.
Èmi yóò gba agbo ẹran mi là, a kì yóò sì kò wọ́n tì mọ́. Èmi yóò ṣe ìdájọ́ láàrín àgùntàn kan àti òmíràn.
23 Na da ilima hina bagade, Na hawa: hamosu dunu Da: ibidi defele, ilima imunu. E da ili noga: le ouligimu.
Èmi yóò fi Olùṣọ́-àgùntàn kan ṣe olórí wọn, ìránṣẹ́ mi Dafidi, òun yóò sì tọ́jú wọn; òun yóò bọ́ wọn yóò sì jẹ́ Olùṣọ́-àgùntàn wọn.
24 Na, Hina Gode, da ilia Gode esalumu, amola hina bagade, Na hawa: hamosu dunu Da: ibidi agoai, da ilia ouligisu esalumu. Na da sia: i dagoi.
Èmi Olúwa yóò sì jẹ́ Ọlọ́run wọn, ìránṣẹ́ mi Dafidi yóò jẹ́ ọmọ-aládé láàrín wọn. Èmi Olúwa ní o sọ̀rọ̀.
25 Na da ilima gousa: su, amo da ili dafawane gaga: ma: ne, hamomu. Amola Na sibi da soge ganodini gaga: iwane esaloma: ne, amola iwila ganodini hahawane golama: ne, Na da nimi bagade sigua ohe soge ganodini esala, amo huluane fadegale sefasimu.
“‘Èmi yóò dá májẹ̀mú àlàáfíà pẹ̀lú wọn, èmi yóò sì gba ilẹ̀ náà kúrò lọ́wọ́ ẹranko búburú, kí wọn kí o lè gbé ní aṣálẹ̀, kí àgùntàn sì gbé ní inú igbó ní àìléwu.
26 Ilia da Na sema agolo hahawane sisiga: le esaloma: ne, Na da ilima hahawane hamomu. Ilima hahawane hamoma: ne, Na da ilia hanai defele, gibu sasafugi ilima imunu.
Èmi yóò bùkún wọn àti ibi agbègbè ti ó yí òkè mi ká. Èmi yóò rán ọ̀wààrà òjò ni àkókò; òjò ìbùkún yóò sì wà.
27 Ifa huluane da dulu legemu. Ifabi da ha: i manu legemu. Amola dunu huluane da gaga: iwane hina: sogea esalumu. Eno dunu da Na dunu afugili asili, ilia udigili hawa: hamosu dunu hamoi. Be Na da ilia lala: gilisi amo fadegale fasili, ilia da hahawane halegale lalumu.
Àwọn igi igbó yóò mú èso wọn jáde, ilẹ̀ yóò sì mu irúgbìn jáde; A yóò sì dá ààbò bo àwọn ènìyàn ní ilẹ̀ náà. Wọn yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa, nígbà tí mo bá já àwọn ohun tí ó ṣe okùnfà àjàgà, tí mo sì gbà wọ́n kúrò lọ́wọ́ àwọn tí ó fi wọ́n ṣe ẹrú.
28 Gode Ea hou hame lalegagui fifi asi gala da ili bu hame wadela: lesimu. Amola sigua ohe da ili bu hame fane manu. Ilia da gaga: iwane, amola eno dunuma mae beda: ne esalumu.
Àwọn orílẹ̀-èdè kì yóò lè kó wọn ní ẹrú mọ́, àwọn ẹranko búburú kì yóò lè pa wọn mọ́. Wọn yóò gbé ni àìléwu, kò sì ṣí ẹni kankan tí yóò le dẹ́rùbà wọ́n.
29 Na da osobo nasegagi ilima imunu. Amola ilia sogega ha: su hame ba: mu. Amola fifi asi gala eno fi dunu da ilima bu hame ba: sola: mu.
Èmi yóò pèsè ilẹ̀ ti o ní oríyìn fún èso rẹ̀ fún wọn, wọn kì yóò sì jìyà nípasẹ̀ ìyàn mọ́ ni ilẹ̀ náà tàbí ru ẹ̀gàn àwọn orílẹ̀-èdè.
30 Dunu huluanedafa da Na da Isala: ili fi gaga: lala amola ilia da Na fi dunu esala, amo dawa: mu. Na, Ouligisudafa Hina Gode da sia: i dagoi.
Nígbà náà ni wọn yóò mọ̀ pé, èmi ni Olúwa Ọlọ́run wọn, èmi wà pẹ̀lú wọn àti pé, àwọn ilé Israẹli jẹ́ ènìyàn mi, ni Olúwa Olódùmarè wí.
31 Dilia, Na sibi, sibi wa: i amoga Na da ha: i manu iaha, dilia da Na: , amola Na da dilia Gode,” Ouligisudafa Hina Gode da amane sia: sa.
Ìwọ àgùntàn mi, àgùntàn pápá mi; ni ènìyàn, èmi sì ni Ọlọ́run rẹ; ni Olúwa Olódùmarè wí.’”

< Isigiele 34 >