< Isigiele 22 >

1 Hina Gode da nama amane sia: i,
Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá:
2 “Dunu egefe! Yelusaleme da fane legesu dunu amoga nabaiba: le, di da ema fofada: musa: momagebela: ? E da noga: le dawa: ma: ne, ea wadela: i hou amo ema bu olelema.
“Ọmọ ènìyàn ǹjẹ́ ìwọ yóò ha ṣe ìdájọ́ rẹ̀? Ǹjẹ́ ìwọ ha ṣe ìdájọ́ ìlú atàjẹ̀sílẹ̀? Tó bá rí bẹ́ẹ̀ dojúkọ wọn pẹ̀lú gbogbo ìwà ìríra wọn.
3 Yelusaleme fi ilima, Na, Ouligisudafa Hina Gode, Na sia: ilima olelema, amane, ‘Dilia da dilila: fi dunu bagohame medole lelegei dagoiba: le, amola ogogosu ‘gode’ ilima dilia hou ledo hamoma: ne, nodone sia: ne gadoiba: le, dilia wadela: mu eso da mana.
Kí ó sì wí pé, ‘Èyí yìí ní ohun tí Olúwa Olódùmarè wí: Ìwọ ìlú ńlá tí ó mú ìparun wá sórí ara rẹ nípa títàjẹ̀sílẹ̀ ní àárín rẹ, tí ó sì ba ara rẹ̀ jẹ́ nípa ṣíṣe àwọn ère.
4 Dilia da amo medole legesu hou hamobeba: le, amola ogogosu ‘gode’ loboga hamoiba: le dilila: hou ledo hamoiba: le, dilima wadela: mu eso da gadenene doaga: i dagoi. Amaiba: le, Na da eno fifi asi gala dilima lalasogole oufesega: ma: ne, logo doasi dagoi.
Ìwọ ti jẹ̀bi nítorí ẹ̀jẹ̀ tí ìwọ ti ta sílẹ̀, àti pé àwọn ère tí ó ṣe tí bà ọ́ jẹ́. Ìwọ tí mú ọjọ́ rẹ súnmọ́ tòsí, ìparí àwọn ọdún rẹ sì ti dé. Nítorí náà èmi yóò fi ọ ṣe ohun ẹ̀gàn lójú àwọn orílẹ̀-èdè àti ohun ẹ̀sín lójú gbogbo ìlú.
5 Dilima gadenene fifi asi gala, amola badilia fifi asi gala da dilia sema hame nabasu hou ba: beba: le, dilima ba: sola: le oufesega: sa.
Àwọn tí ó wà ní tòsí àti àwọn tí ó jìnnà sí ọ, yóò fi ọ ṣe ẹlẹ́yà, ìwọ ìlú ẹlẹ́gàn, tí ó kún fún làálàá.
6 Isala: ili ouligisu dunu huluane da ilila: gasa da defele dawa: beba: le, medole legesu hou hamonanebe.
“‘Wo bí ọ̀kọ̀ọ̀kan nínú àwọn ọmọbìnrin ọba Israẹli tí ó wà nínú yín ti ń lo agbára rẹ̀ láti tàjẹ̀ sílẹ̀.
7 Yelusaleme amo ganodini, mano huluane da ilia edalalima hame nodosa. Dilia da ga fi ilima ogogosa. Amola, dilia da didalo amola guluba: mano ilima da: da: losa.
Nínú rẹ wọn ti hùwà sí baba àti ìyá pẹ̀lú ìfojú tínrín; nínú rẹ wọn ti ni àwọn àlejò lára, wọn sì hùwàkiwà sí aláìní baba àti opó.
8 Dilia da hadigidafa sogebi amoma hame nodosa, amola Sa: bade sema hame hamosa.
Ìwọ tí kọ àwọn ohun mímọ́ mi sílẹ̀, ìwọ sì ti lo ọjọ́ ìsinmi mi ní ìlòkulò.
9 Dilia mogili da eno dunu, ilia bogoma: ne se bidi lama: ne, ilia hou ogogole sia: sa. Dilia mogili da ohe amo ogogosu ‘gode’ ilima gobele sali, amo ea hu naha. Mogili da ilia wadela: i hanai gumimusa: dawa: lala.
Nínú rẹ ni àwọn ayannijẹ ènìyàn pinnu láti tàjẹ̀ sílẹ̀; nínú rẹ ní àwọn tí ó ń jẹun ní orí òkè ojúbọ òrìṣà, wọn sì hùwà ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́.
10 Mogili ilia da ilia eda ea uda amo gilisili golasa. Mogili da uda da sioi fisia, ilima gasa fili lelele logesa.
Nínú rẹ ní àwọn ti kò bu ọlá fún àwọn àkéte baba wọn; nínú rẹ ni àwọn tí o ń bá àwọn obìnrin lò nígbà tí wọ́n ń ṣe àkókò lọ́wọ́, ní àsìkò tí a ka wọn sì aláìmọ́.
11 Mogili da inia uda adole laha. Mogili da ilila: nawi amola gawia adole lasa.
Nínú rẹ ọkùnrin kan ti dá ẹ̀ṣẹ̀ ìríra pẹ̀lú aya aládùúgbò rẹ̀, òmíràn bá ìyàwó ọmọ rẹ̀ jẹ́, òmíràn sì bá arábìnrin rẹ̀ lòpọ̀ èyí tí í ṣe ọbàkan rẹ̀.
12 Mogili da bidi lamusa: , dunu medole legesa. Mogili da fa: no dabema: ne muni bu lama: ne, eno dunuma iasea, ilia amo muni bagade baligiwane bu laha. Amola ilia eno dunuma da: da: lobeba: le, muni bagade gagusa. Ilia da Na gogolei dagoi.” Ouligisu Hina Gode da sia: i dagoi.
Nínú rẹ àwọn ènìyàn gba àbẹ̀tẹ́lẹ̀ láti tàjẹ̀ sílẹ̀; ìwọ gba èlé ìlọ́po láti mú aláìṣòótọ́ jèrè láti ara aládùúgbò rẹ nípa ìrẹ́jẹ. Ìwọ sì ti gbàgbé èmi; ni Olúwa Olódùmarè wí.
13 “Na da Na loboga dilia wamolasu dunu amola medole legesu dunu banenesimu.
“‘Èmi yóò kúkú pàtẹ́wọ́ lórí èrè àìmọ̀ tí ìwọ ti jẹ, àti lórí ẹ̀jẹ̀ tí ìwọ ti ta sílẹ̀ ní àárín yín.
14 Na da dilima se ia dagosea, dilia da gasa hamedei ba: mu. Dilia da gasa hameba: le, dilia lobo gaguia gadomu hamedei ba: mu. Na, Hina Gode, da sia: i dagoi. Amola, Na da ogogosu hame dawa:
Ọkàn rẹ le gbà á, tàbí ọwọ́ rẹ lè le, ní ọjọ́ tí èmi yóò bá ọ ṣé? Èmi Olúwa ti sọ̀rọ̀, Èmi yóò sì ṣe é.
15 Na da dilia wadela: i hamobe dagolesima: ne, Na da dili fifi asi gala fi huluane amo ganodini esaloma: ne, dili afagogolesimu.
Èmi yóò tú yin ká ní àárín àwọn orílẹ̀-èdè, èmi yóò fọ́n ọ ká sí àwọn ìlú; èmi yóò sì fi òpin sí àìmọ́ rẹ.
16 Amola eno fifi asi gala da dilima mae nodone, banenesimu. Be dilia da Na da Hina Gode amo dafawaneyale dawa: mu.”
Nígbà tí a ó bà ọ́ jẹ́ lójú àwọn orílẹ̀-èdè, ìwọ yóò mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa.’”
17 Hina Gode da nama amane sia: i,
Nígbà náà ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá:
18 “Dunu egefe! Isala: ili dunu da Nama hamedei liligi agoai. Ilia da fedege agoane, silifa da gobesu lalu amo ganodini adoba: ma: ne gobesea, isui ouli amo dialebe agoai ba: sa.
“Ọmọ ènìyàn, ilé Israẹli ti di ìdàrọ́ sí mi; gbogbo wọn jẹ́ bàbà, idẹ, irin àti òjé ti a fi sínú iná ìléru. Wọn jẹ́ ìdàrọ́ ti fàdákà.
19 Amaiba: le, Na, Ouligisudafa Hina Gode, da wali ilia da amo isui ouli defele, hamedei liligi, ilima adosa. Na da ili huluane gilisili, Yelusalemega oule misunu.
Nítorí náà èyí yìí ni ohun ti Olúwa Olódùmarè wí: ‘Nítorí tí ìwọ ti di ìdàrọ́, èmi yóò kó yín jọ sí Jerusalẹmu.
20 Dunu da igi (amo ganodini da silifa, gula, balase, lede amola dini gala) amo gilisili, gobesu laluga gaguli maha, amo defele Na da Isala: ili dunu oule misunu. Amola, lalu da amo liligi daeabe defele, Na ougi bagadedafa da ili daeamu.
Gẹ́gẹ́ bí ènìyàn ṣe ń kó fàdákà, bàbà, irin, òjé àti idẹ jọ sínú iná ìléru láti fi iná yọ́ ọ, bẹ́ẹ̀ ni èmi yóò kó ọ jọ ní ìbínú àti ìrunú mi, èmi yóò sì fi ọ sì àárín ìlú, èmi yóò sì yọ́ ọ. Níbẹ̀ ní ìwọ yóò sì ti yọ́.
21 Dafawane! Na da ili gagadole, Yelusaleme amoma oule misini, ili hagudu lalu didili, Na ougiga ili daeamu.
Èmi yóò kó yín jọ, èmi o sì fín iná ìbínú mi si yin lára, ẹ o si di yíyọ́ láàrín rẹ̀.
22 Dunu ilia da silifa amo lalu gobesu amo ganodini silifa daeabe, amo defele Na da ili Yelusaleme ganodini daeamu. Amasea, ilia da Hina Gode Ea ougi nabaha, amo noga: le dawa: mu.”
Bí a ti ń yọ́ fàdákà nínú iná ìléru bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ní ìwọ yóò ṣe yọ́ nínú rẹ̀, ìwọ yóò sì mọ̀ wí pé, Èmi Olúwa ti tú ìbínú mi sórí rẹ.’”
23 Hina Gode da nama bu amane sia: i,
Lẹ́ẹ̀kan sí i ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá wí pé,
24 “Dunu egefe! Isala: ili dunu amo ilia soge da ledo bagade, hadigi hame, amo ilima sia: ma. Amaiba: le, Na da ougili, ilima se imunu.
“Ọmọ ènìyàn, sọ fún ilẹ̀ náà, ‘Ìwọ ní ilẹ̀ tí kò gbá mọ́, ti kò sì rọ òjò tàbí ìrì ní àkókò ìbínú.’
25 Ilia ouligisu dunu da laione wa: me amo da ohe ilia fai amo enoga lasa: besa: le, gesenebe agoai gala. Ilia dunu eno medole legesa, ilia soge amola muni amo ilia hanai defele laha. Amalu, didalo bagohame esalebe ba: sa.
Ìdìtẹ̀ sì wà láàrín àwọn ọmọ-aládé inú rẹ̀, tó dàbí bíbú kìnnìún tó ń fà ẹran ya, wọ́n ń ba àwọn ènìyàn jẹ́, wọ́n ń kó ìṣúra àti àwọn ohun iyebíye wọ́n sì ń sọ púpọ̀ di opó nínú rẹ̀.
26 Gobele salasu ouligisu dunu da Na sema fili, hadigi liligi amoma hame dawa: digisa. Ilia da hadigi liligi amola ledo liligi, amo afafamusa: hame dawa: Ilia da foloai amola ledo da hisu hame olelesa. Amola ilia da Sa: bade eso sema amoma higasa. Amaiba: le, Isala: ili dunu da Nama hame nodosa.
Àwọn àlùfáà rẹ̀ ti rú òfin mi, wọn si ti sọ ohun mímọ́ mi di àìlọ́wọ̀: wọn kò fi ìyàtọ̀ sáàrín ohun mímọ́ àti àìlọ́wọ̀, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò fi ìyàtọ̀ hàn láàrín ohun àìmọ́, àti mímọ́, wọn sì ti fi ojú wọn pamọ́ kúrò ní ọjọ́ ìsinmi mi, mó sì dí ẹni àìlọ́wọ̀ láàrín wọn.
27 Eagene ouligisu dunu da wufi gasonasu wa: me da ilia medole legei ohe liligi dodosa: sa, amo defele hamosa. Ilia muni bagade lamusa: , medole legesu hou hamosa.
Àwọn ọmọ-aládé àárín rẹ̀ dàbí ìkookò ti ń ṣọdẹ, láti tàjẹ̀ sílẹ̀, láti pa ọkàn run, láti jèrè àìṣòótọ́.
28 Ogogosu balofede dunu da dunu ilia gagoi damana ahea: iai ulasuga ulasu defele, amo wadela: i hou dedebosu. Ilia da ogogosu esala ba: su olelesa, amola ogogosu ba: la: lusu hamosa. Ilia da Ouligisu Hina Gode Ea sia: olelelala, ilisu sia: sa. Be Na, Hina Gode, da ilima hamedafa sia: i.
Àti àwọn wòlíì rẹ́ ti ṣẹ̀tàn sí wọn, wọn ń rì ìran asán, wọn sì ń fọ àfọ̀ṣẹ èké sí wọn, wí pé, ‘Báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí,’ nígbà tí ó ṣépè Olúwa kò sọ̀rọ̀.
29 Bagade gagui dunu da ogogosu amola gegene lasu hou hamosa. Ilia da hame gagui dunu amola ga fi dunu ilima da: da: losa.
Àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà, tí lo ìwà ìninilára, wọn sì já olè, wọn sì ni àwọn tálákà àti aláìní lára; nítòótọ́, wọn tí ní àlejò lára láìnídìí. Kò sì ṣí ìdájọ́ òdodo.
30 Na da gaga: su dunu, amo da gagoi gadelale sa: i sogebi amo gaga: le, Na soge Na ougiga wadela: mu gadenesa amo gaga: musa: aligima: ne, agoai dunu hogoi helele hame ba: i.
“Èmi si wá ẹnìkan láàrín wọn, tí ìbá tún odi náà mọ́, tí ìbá dúró ní ibi tí ó ya náà níwájú mi fún ilẹ̀ náà, kí èmi má bá à parun: ṣùgbọ́n èmi kò rí ẹnìkan.
31 Amaiba: le, Na da Na ougi bu hame bugimu. Na ougi da ilima lalu agoane doagala: mu. Na da ilima se imunu. Ilia wadela: le hamoiba: le, Na da ili wadela: lesimu.” Ouligisudafa Hina Gode da sia: i dagoi.
Nítorí náà ni mo ṣe da ìbínú mi sí wọn lórí, mo ti fi iná ìbínú mi run wọn, mo si ti fi ọ̀nà wọn gbẹ̀san lórí ara wọn, ní Olúwa Olódùmarè wí.”

< Isigiele 22 >