< Gadili Asi 2 >

1 Amo esoga, Lifai fi dunu afae da Lifai fi a: fini lai.
Ó sì ṣe, ọkùnrin ará ilé Lefi kan fẹ́ ọmọbìnrin ará Lefi kan ni ìyàwó.
2 Amo uda da ema dunu mano lalelegei. E da ea mano da noga: i mano ba: beba: le, e da oubi udiana amoga mano wamolegei.
Obìnrin náà sì lóyún, ó sì bí ọmọkùnrin kan. Nígbà tí ó rí í pé ọmọ náà rẹwà, ó gbé ọmọ náà pamọ́ fún oṣù mẹ́ta.
3 Be bu wamolegemu hamedei ba: loba, e da daba saga: amoga amuni lale, hano da amoga mae ha: ina sa: ima: ne edele amoga legei. E da ea mano amo ganodini sanasili, Naile hano bega: saga: sedade amo ganodini ligisi.
Ṣùgbọ́n nígbà tí kò le è gbé e pamọ́ mọ́, ó fi ewé papirusi hun apẹ̀rẹ̀, ó sì fi ọ̀dà àti òjé igi sán apẹ̀rẹ̀ náà. Ó sì tẹ́ ọmọ náà sínú rẹ̀, ó sì gbe é sí inú eèsún ni etí odò Naili.
4 Mano dudubu ea dalusi da fonobahadi sedagawane fa: no misunu hou ba: musa: lelu.
Arábìnrin rẹ̀ dúró ni òkèèrè láti wo ohun tí yóò ṣẹlẹ̀ sí ọmọ náà.
5 Felou idiwi da hano ulimusa: misi. Ea hawa: hamosu a: fini ilia da hano bega: lalu. E da daba amo saga: ganodini dialebe ba: i. E da ea udigili hawa: hamosu a: fini afae amo lama: ne asunasi.
Nígbà náà ni ọmọbìnrin Farao sọ̀kalẹ̀ wá sí etí odò Naili láti wẹ̀, àwọn ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ sì ń rìn ni etí bèbè odò. Ó sì ri apẹ̀rẹ̀ náà ni àárín eèsún, ó sì rán ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ obìnrin kan láti lọ gbé e wá,
6 Felou idiwi da daba ea figisu doagadole, dunu mano dudubu ganodini dialebe ba: i. E da dinanu amola Felou idiwi da e asigili ba: i. E amane sia: i, “Amo da Hibulu mano esala.”
ó ṣí i, ó sì rí ọmọ náà. Ọmọ náà ń sọkún, àánú ọmọ náà sì ṣe é. Ó wí pé, “Ọ̀kan nínú àwọn ọmọ Heberu ni èyí.”
7 Amalalu, amo mano dudubu ea dalusi da Felou idiwi ema amane adole ba: i, “Na da Hibulu uda amo di fidima: ne, amo manoma dodo ima: ne misa: ne sia: mu da defeala: ?
Nígbà náà ni arábìnrin rẹ̀ béèrè lọ́wọ́ ọmọbìnrin Farao pé, “Ṣé kí èmi lọ wá ọ̀kan lára àwọn obìnrin Heberu wá fún ọ láti bá ọ tọ́jú ọmọ náà?”
8 Felou idiwi da bu adole i, “Defea! Amo misa: ne sia: ma.” Amalalu, mano ea dalusi da asili, mano dudubu hi amedafa ema oule misi.
Ó sì dáhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ ni; lọ.” Arábìnrin náà sì lọ, ó sì pe ìyá ọmọ náà wá.
9 Felou idiwi da amo udama amane sia: i, “Di amo mano dudubu lale, nama bu imunusa: ouligima. Na da dima bidi imunu.” Amalalu, e da mano dudubu lale, dodo ianu.
Ọmọbìnrin Farao sì wí fún un pé, “Gba ọmọ yìí kí o sì tọ́jú rẹ̀ fún mi, èmi yóò san owó iṣẹ́ ẹ̀ rẹ fún ọ.” Ọmọbìnrin náà sì gbé ọmọ náà lọ, ó sì tọ́jú rẹ̀.
10 Fa: no, mano da fonobahadi asigilaloba, ea ame da e Felou idiwima bu oule asi. Amalalu, e da amo mano fofoi dagoi. E da hima adole i, “Na da amo mano hano ganodini dialu lai. Amaiba: le, na da ema Mousese dio asula.” (Mousese dawa: loma: ne Idibidi sia: ga da ‘lalelegei’ amola Hibulu sia: ga da ‘ganodini dialu lai.’)
Nígbà tí ọmọ náà sì dàgbà, ó mú un tọ ọmọbìnrin Farao wá, ó sì di ọmọ rẹ̀. Ó sì pe orúkọ rẹ̀ ní Mose, ó wí pé, “Nítorí tí mo fà á jáde nínú omi.”
11 Mousese da asigi laloba, e da ea fi dunu (Hibulu dunu) amo ba: musa: sofe asi. E da Idibidi dunu da ilima gasa fili, hawa: hamosu gasa bagade ilima i, amo ba: i dagoi. Amola Idibidi dunu afae e da Mousese ea fi Hibulu dunu amo fanelegei dagoi, amo Mousese da ba: i dagoi.
Ní ọjọ́ kan, nígbà tí Mose ti dàgbà, ó jáde lọ sí ibi ti àwọn ènìyàn rẹ̀ wà, ó ń wò wọ́n lẹ́nu iṣẹ́ líle wọn, ó ri ará Ejibiti tí ń lu ará Heberu, ọ̀kan nínú àwọn ènìyàn rẹ̀.
12 Mousese da la: idi ba: lega, la: idi ba: lega hogolalu, dunu eno hame ba: beba: le, e da amo Idibidi dunu fanelegele, ea da: i hodo wamolegemusa: , sa: i boso amoga uli dogone sali.
Ó wo ìhín, ó wo ọ̀hún, nígbà tí kò rí ẹnìkankan, ni ó bá pa ará Ejibiti náà, ó sì bò ó mọ́ inú iyanrìn.
13 Aya esoga, e da bu asili, Hibulu dunu aduna gegenanebe ba: i. E da giadofale hamoi dunuma amane sia: i, “Dia da abuliba: le dia Hibulu na: iyado fananala: ?”
Ní ọjọ́ kejì, ó jáde lọ, ó rí àwọn ará Heberu méjì tí wọ́n ń jà. Ó béèrè lọ́wọ́ èyí tí ó jẹ̀bi pé, “Èéṣe tí ìwọ fi ń lu Heberu arákùnrin rẹ?”
14 Amo dunu da bu adole i, “Di da ninia fofada: su dunu amola ouligisu dunu, nowa da hamobela: ? Di da aya Idibidi dunu medole legei amo defele na amola medole legema: bela: ?” Amalalu, Mousese da beda: i ba: i. E da ea dogo ganodini amane sia: i “Dunu huluane da na hamoi dawa: dagoi.”
Ọkùnrin náà sì dáhùn pé, “Ta ni ó fi ọ́ jẹ olórí àti onídàájọ́ lórí wa? Ṣé ìwọ fẹ́ pa mí bí o ti pa ará Ejibiti?” Nígbà náà ni ẹ̀rù ba Mose, ó sì wí pé, “Lóòótọ́ ni ọ̀ràn yìí ti di mí mọ̀.”
15 Felou da amo hou nababeba: le, e da Mousese fanelegema: ne sia: i, be Mousese da hobeale asili, Midia: ne sogega wamoaligimusa: asi. Eso afaega, Mousese da hano nasu uli dogoi gadenene esalu. Yedelou (Midia: ne gobele salasu dunu) amo ea uda mano fesuale gala da ilia ada ea sibi amola goudi, hano nasu ofodoga nabama: ne, hano dimusa: misi.
Nígbà ti Farao sì gbọ́ nípa èyí, ó wá ọ̀nà láti pa Mose, ṣùgbọ́n Mose sá kúrò ní àrọ́wọ́tó o Farao, ó lọ sí Midiani láti máa gbé, nígbà tí ó dé bẹ̀, ó jókòó ni ẹ̀bá a kànga kan.
Ó sì ṣe, àlùfáà Midiani kan ni àwọn ọmọbìnrin méje, wọn sì wá láti pọn omi kún ọpọ́n ìmumi fún ẹran ọ̀sìn baba wọn.
17 Be sibi ouligisu dunu eno da Yedelou ea uda manolali sefasi. Amalalu, Mousese da ili gaga: musa: misini, ilia lai gebo amoma ima: ne hano dili i.
Àwọn darandaran kan wá, wọ́n sì lé wọn sẹ́yìn, ṣùgbọ́n Mose dìde láti gbà wọ́n sílẹ̀ àti láti ràn wọ́n lọ́wọ́ láti fún ẹran wọn ní omi.
18 Ilia da ilia adama bu misini, e fofogadigili ilima amane, adole ba: i, “Dilia da habodane hedolo bu misibala: ?”
Nígbà ti àwọn ọmọbìnrin náà padà dé ọ̀dọ̀ Reueli baba wọn, ó béèrè lọ́wọ́ wọn pé, “Èéṣe tí ẹ̀yin fi tètè dé ni òní?”
19 Ilia da bu adole i, “Sibi ouligisu dunu da nini sefasisia, Idibidi dunu afae da nini gaga: i dagoi. Amola e da ninia lai gebo moma: ne, hano dili i.”
Wọ́n dá a lóhùn pé, “Ará Ejibiti kan ni ó gbà wá sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn darandaran, ó tilẹ̀ ràn wá lọ́wọ́ láti fa omi àti láti fún agbo ẹran ní omi.”
20 Yedelou da ea idiwi amoma amane adole ba: i, “E da habila: ? Dilia da abuliba: le e gadili leloma: ne yolesila: ? Masa! E da nini gilisili ha: i manusa: misa: ne sia: ma.”
Ó sọ fún àwọn ọmọbìnrin rẹ̀, “Níbo ni ó wà? Èéṣe ti ẹ fi fi ọkùnrin náà sílẹ̀? Ẹ pè é wá jẹun.”
21 Amaiba: le, Mousese da Midia: ne soge ganodini esalumusa: dawa: i galu. Amalalu, Yedelou da idiwi Siboula e lama: ne Mousesema i dagoi.
Mose gbà láti dúró lọ́dọ̀ ọkùnrin náà, ẹni tí o fi Sippora, ọmọbìnrin rẹ̀ fún Mose láti fi ṣe aya.
22 Siboula da ema dunu mano lalelegei. Mousese da ea dogo ganodini amane sia: i, “Na da amo soge ganodini ga fi esala. Amaiba: le, amo manoma na da Gesiome (ga fi dunu) dio asula.”
Ó sì bí ọmọkùnrin kan tí ó pe orúkọ rẹ̀ ní Gerṣomu, ó wí pé, “Èmi ń ṣe àtìpó ní ilẹ̀ àjèjì.”
23 Ode eno ilia da gidigili, Idibidi hina bagade (Felou) da bogoi. Be gasa bagade udigili hawa: hamosu hamobeba: le, Isala: ili dunu da gogonomane, Gode fidima: ne dinanawane wesu.
Lẹ́yìn ìgbà pípẹ́, ọba Ejibiti kú. Àwọn ará Israẹli ń kérora ní oko ẹrú wọn, wọ́n ń ké fún ìrànlọ́wọ́ nítorí oko ẹrú tí wọ́n wà, igbe wọ́n sì dé ọ̀dọ̀ Ọlọ́run.
24 Gode da ilia dinanawane wesu nabi dagoi. E da Ea gousa: su, amo E da A: ibalaha: me, Aisage amola Ya: igobe ilima hamoi bu dawa: i.
Ọlọ́run gbọ́ igbe wọn, Ó sì rántí májẹ̀mú rẹ̀ pẹ̀lú Abrahamu, Isaaki àti pẹ̀lú Jakọbu.
25 E da Isala: ili dunu amo ilia se nabawane udigili hawa: hamosu ba: i dagoi. Amola E da ilima bagade asigisu.
Nítorí náà, Ọlọ́run bojú wo àwọn ará Israẹli, Ó sì wà láti gbà wọ́n sílẹ̀.

< Gadili Asi 2 >