< Da:niele 9 >

1 Da: liase (Segesisi egefe, e da Midia fi dunu) amo da Ba: bilone fi amoga hina bagade esalu.
Ní ọdún kìn-ín-ní Dariusi ọmọ Ahaswerusi, ẹni tí a bí ní Media, òun ló jẹ ọba lórí ìjọba Babeli.
2 Ea ouligisu hou ode bisili amoga na da Gode Ea sia: buga ganodini dedei amo idilalu. Amo ganodini, Hina Gode da balofede dunu Yelemaiama agoane olelei. Yelusaleme moilai bai bagade da wadela: lesi dagoi amola ode 70amoga amaiwane mugului agoane dialebe ba: mu. Amo sia: na idi amola na da dadawa: lalu.
Ní ọdún kìn-ín-ní ìjọba rẹ̀, èmi Daniẹli fi iyè sí i láti inú ìwé, gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ Olúwa tí wòlíì Jeremiah, wá pé, àádọ́rin ọdún ni Jerusalẹmu yóò fi wà ní ahoro.
3 Amola na da ha: giwane Hina Godema sia: ne gadosu. Na da wadela: i eboboi abula salawane, ha: i mae nawane amola nasubu ganodini fili, ha: giwane Ema adole ba: i.
Nígbà náà, ni mo yípadà sí Olúwa Ọlọ́run, mo bẹ̀ ẹ́ pẹ̀lú àdúrà àti ẹ̀bẹ̀, pẹ̀lú àwẹ̀, aṣọ ọ̀fọ̀ àti eérú.
4 Na da na Hina Godema sia: ne gadole, na fi dunu amola uda ilia wadela: i hou Ema olelei. Na da amane sia: ne gadoi, “Hina Gode! Dia hou da bagadedafa amola hadigidafa. Ninia da Dima nodosa. Dia da Dia gousa: su hamoi amoma mae fisili, ouligisa. Nowa dunu da Dima asigi galea amola Dia sia: noga: le nabasea, amo dunuma Di da mae fisili asigilala.
Mo gbàdúrà sí Olúwa Ọlọ́run mi, mo sì jẹ́wọ́ wí pé: “Ìwọ Olúwa, Ọlọ́run tí ó tóbi, tí ó sì ní ẹ̀rù, ẹni tí ń pa májẹ̀mú ìfẹ́ mọ́, pẹ̀lú àwọn tí ó ní ìfẹ́ rẹ̀ àti àwọn tí ó ń pa àwọn òfin rẹ̀ mọ́.
5 Ninia da wadela: idafa fi. Ninia da wadela: i hou bagadedafa hamonanu. Ninia da Dia hamoma: ne sia: i amola sema higale yolesi dagoi. Dia da ninima moloidafa hou olelei, be ninia da amo hou higale yolesi dagoi.
Àwa ti ṣẹ̀, a sì ti ṣe búburú. Àwa ti hu ìwà búburú, a sì ti ṣe ọ̀tẹ̀, a ti yí padà kúrò nínú àwọn àṣẹ àti àwọn ìlànà rẹ̀.
6 Dia hawa: hamosu dunu amo balofede dunu, ilia Dia Dioba: le, hina bagade, ouligisu dunu, ninia aowalalia amola ninia fi huluane ilima sia: olelei. Be ninia da ilia sia: hame nabi.
Àwa kò fetí sí àwọn wòlíì ìránṣẹ́ rẹ, ẹni tí ó sọ̀rọ̀ ní orúkọ rẹ sí àwọn ọba wa, àwọn ọmọ-aládé àti àwọn baba wa, àti sí gbogbo ènìyàn ilẹ̀ náà.
7 Di, Hina Gode, da eso huluane moloidafa hou hamonana. Be ninia da eso huluane ninisu gogosiama: ne, wadela: i hou hamonana. Ninia huluanedafa agoane hamosa. Mogili da Yuda soge amola Yelusaleme moilai bai bagade amo ganodini esala. Mogili da Dia sia: hame nababeba: le, Di da ili soge gadenene amola sedagadafa, amo soge hisu hisu amo ganodini esaloma: ne sefasi dagoi. Be huluanedafa da Dia sia: hame nabasu dunu.
“Olúwa ìwọ ni olódodo, ṣùgbọ́n báyìí ìtìjú dé bá àwọn ènìyàn Juda, àwọn ènìyàn Jerusalẹmu àti gbogbo Israẹli ní gbogbo orílẹ̀-èdè tí ìwọ ti fọ́n wa ká sí nítorí àìṣòótọ́ ọ wa sí ọ.
8 Hina Gode! Dafawane! Ninia hina bagade huluane, ninia ouligisu dunu amola ninia aowalalia da Dima wadela: i hou bagade hamonanu.
Háà! Olúwa, àwa àti àwọn ọba wa, àwọn ọmọ-aládé, àti àwọn baba wa, ìtìjú dé bá wa nítorí àwa ti dẹ́ṣẹ̀ sí ọ.
9 Ninia da Dima fa: no bobogesu yolesi dagoi. Be Di da ninima asigisa amola Di da gogolema: ne olofosu dawa:
Olúwa Ọlọ́run wa ní àánú, ó sì ń dáríjì, bí àwa tilẹ̀ ti ṣe ọ̀tẹ̀ sí i;
10 Di da nini amo sema Di da Dia hawa: hamosu dunu amo balofede dunu ilia lafidili ninima olelei, amo sema defele esaloma: ne ninima sia: i. Be ninia da Dia sia: hame nabi.
àwa kò gbọ́rọ̀ sí Olúwa Ọlọ́run wa, a kò sì pa àwọn òfin rẹ mọ́, èyí tí ó fún wa nípasẹ̀ àwọn wòlíì ìránṣẹ́ rẹ̀.
11 Isala: ili fi huluane da Dia sema wadela: lesi dagoi amola Dia sia: nabimu higalalu. Amaiba: le, gagabusu aligima: ne amo da Dia hawa: hamosu dunu Mousese ea sema buga ganodini dedei, amoga Di da ninima se iasu.
Gbogbo Israẹli ti ṣẹ̀ sí òfin rẹ, wọ́n ti yípadà kúrò ní ọ̀dọ̀ rẹ, wọ́n kọ̀ láti ṣe ìgbọ́ràn sí ọ. “Nígbà náà ni ègún àti ìdájọ́ tí a kọ sílẹ̀ pẹ̀lú ìbúra nínú òfin Mose ìránṣẹ́ Ọlọ́run dà sórí i wa, nítorí tí àwa ti sẹ̀ sí ọ.
12 Di da musa: Yelusaleme moilai bai bagadega hamomu sia: i, amo Di da hamoi dagoi. Di da Yelusaleme amoma se iasu. Amola amo se iasu da Dia se iasu amo moilai bai bagade eno osobo bagadega diala Di da ilima i, amo da bagadewane baligisu.
Ìwọ ti mú ọ̀rọ̀ tí o sọ sí wa sẹ àti lórí àwọn alákòóso wa, nípa mímú kí ibi ńlá bá wa, irú èyí tí kò tí ì ṣẹlẹ̀ rí lábẹ́ ọ̀run, bí ó ti ṣẹlẹ̀ sí Jerusalẹmu yìí.
13 Di da se iasu huluane Mousese ea sema buga ganodini dedei, amo huluane ninima iasu. Be amo mae dawa: le, ninia Di hahawane ba: ma: ne, Dia dafawane hou hame fa: no bobogesa amola ninia wadela: i hou hame yolesiagai.
Bí a ti kọ ọ́ sínú òfin Mose bẹ́ẹ̀ ni gbogbo ibi yìí ti dé bá wa, síbẹ̀ a kò bẹ̀bẹ̀ fún ojúrere Olúwa Ọlọ́run wa, nípa yíyí padà kí a kúrò nínú ẹ̀ṣẹ̀ wa kí a sì mọ òtítọ́ rẹ.
14 Ninia Hina Gode! Di da ninima se imunusa: dawa: i dagoi amola Dia da se iasu ninima i. Bai Di da eso huluane moloidafa hou fawane hamosa, amola ninia da Dia sia: hame nabi.
Olúwa kò jáfara láti mú ibi náà wá sórí wa, nítorí olódodo ni Olúwa Ọlọ́run wa nínú u gbogbo ohun tí ó ń ṣe; síbẹ̀ àwa kò ṣe ìgbọ́ràn sí i.
15 Ninia Hina Gode! Dia gasa bagade hou, di da dunu fifi asi gala ilima olelei dagoi. Dia fi dunu Idibidi sogega udigili hawa: hamonanu, amo Di da fadegale ga oule asi. Amo gasa hou, ninia da hame gogolei. Be ninia da wadela: le hamoi dagoi.
“Ní ìsinsin yìí, Olúwa Ọlọ́run wa, ẹni tí ó mú àwọn ènìyàn rẹ̀ jáde láti ilẹ̀ Ejibiti wá, pẹ̀lú ọwọ́ agbára, tí ó fún ara rẹ̀ ní orúkọ tí ó wà títí di òní, a ti ṣẹ̀, a sì ti ṣe búburú.
16 Di da musa: nini gaga: i dagoi. Amaiba: le, Di Yelusaleme amola ea fi ilima bu ougimusa: mae dawa: ma. Yelusaleme da Dia moilai bai bagadedafa amola Dia Hadigi Agolo gala. Na: iyado dunu fi huluane da wali Yelusaleme amo higale ba: sa. Bai nini amola ninia aowalalia da ledo bagade amola wadela: i hou bagade hamonanu.
Olúwa, ní ìbámu pẹ̀lú ìwà òdodo rẹ, yí ìbínú àti ìrunú rẹ padà kúrò ní Jerusalẹmu ìlú u rẹ, òkè mímọ́ rẹ. Ẹ̀ṣẹ̀ wa àti àìṣedéédéé àwọn baba wa ti mú Jerusalẹmu àti ènìyàn rẹ di ẹ̀gàn fún gbogbo àwọn tí ó yí wọn ká.
17 Hina Gode! Di na sia: ne gadosu amola na ha: giwane edegesu Dia nabima! Ninia Debolo mugului amo bu hahamoma. Dunu huluanedafa da Di da Godedafa amo dawa: ma: ne, Debolo bu hahamoma.
“Nísinsin yìí, Ọlọ́run wa, gbọ́ àdúrà àti ẹ̀bẹ̀ ìránṣẹ́ rẹ, nítorí i tìrẹ Olúwa, fi ojú àánú wo ibi mímọ́ rẹ tí ó ti dahoro.
18 Hina Gode! Ninia sia: nabima! Dia ninia hou ba: ma! Yelusalemega da Dia Dio asuli dagoi. Be amo ganodini, se nabasu amola da: i diosu amo fawane ba: sa. Ninia hou moloidafa hamobeba: le, Dima hame sia: ne gadosa. Bai ninia da moloidafa hou hamedafa hamosu. Be Di da asigi bagadedafa, amo dawa: beba: le, ninia Dima sia: ne gadosa.
Tẹ́ etí rẹ sílẹ̀, Ọlọ́run, kí o gbọ́; ya ojú rẹ sílẹ̀, kí o sì wo ìdahoro ìlú tí a ń fi orúkọ rẹ pè. Àwa kò gbé ẹ̀bẹ̀ wa kalẹ̀ níwájú u rẹ nítorí pé a jẹ́ olódodo, bí kò ṣe nítorí àánú ńlá rẹ.
19 Hina Gode! Ninia sia: nabima! Amola ninia wadela: i hou gogolema: ne olofoma. Dafawane! Mae aligima! Ninia edegesu nabima amola hedolodafa amo hahamoma. Amalalu, dunu huluane da Di da Godedafa, amo ilia da noga: le dawa: mu. Amo moilai bai bagade amola amo dunu fi huluane da Dia: fawane!”
Olúwa, fetísílẹ̀! Olúwa, dáríjì! Olúwa, gbọ́ kí o sì ṣe é! Nítorí i tìrẹ, Ọlọ́run mi, má ṣe pẹ́ títí, nítorí ìlú rẹ àti àwọn ènìyàn rẹ ń jẹ́ orúkọ mọ́ ọ lára.”
20 Na da mae fisili, sia: ne gadolalu. Na wadela: i hou amola na fi Isala: ili ilia wadela: i hou na da Godema olelelalu. Amola na Hina Gode amoma E da Ea hadigi Debolo Diasu amo bu hahamoma: ne, na da Ema ha: giwane edegelalu.
Bí mo ṣe ń sọ̀rọ̀, tí mo sì ń gba àdúrà, tí mo ń jẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ mi àti ẹ̀ṣẹ̀ àwọn Israẹli ènìyàn mi, tí mo sì ń mú ẹ̀bẹ̀ mi tọ Olúwa Ọlọ́run mi nítorí òkè mímọ́ rẹ.
21 Na sia: ne gadosa esaloba, a:igele dunu Ga: ibaliele (amo na da musa: simasi amo ganodini ba: i), e da hagili misini, na esalebe sogebi amoga doaga: i. E doaga: lalu, daeya gobele salasu hou hamomusa: agoane ba: i.
Bí mo ṣe ń gba àdúrà náà lọ́wọ́, Gabrieli ọkùnrin tí mo rí nínú ìran ìṣáájú, yára kánkán wá sí ọ̀dọ̀ mi ní àkókò ẹbọ àṣálẹ́.
22 E da nama amane sia: i “Da: niele! Na da dima amo musa: ba: la: lusu liligi di idi, amo dima noga: le olelemusa: dima misi.
Ó jẹ́ kí ó yé mi, ó sì wí fún mi pé, “Daniẹli, mo wá láti jẹ́ kí o mọ̀ kí o sì ní òye.
23 Di da muni Godema ha: giwane edegesu hemonanu, E da dima adole imunusa: dawa: i galu. E da dima bagade asigisa. Amaiba: le, na amo ba: la: lusu liligi ea bai dima olelela misi. Amaiba: le, noga: le nabima.
Bí o ṣe bẹ̀rẹ̀ sí nígbà àdúrà, a fún ọ ní ìdáhùn kan, èyí tí mo wá láti sọ fún ọ, nítorí ìwọ jẹ́ àyànfẹ́ gidigidi. Nítorí náà, gba ọ̀rọ̀ náà yẹ̀ wò kí ìran náà sì yé ọ:
24 Ode 70 amo fesuale agoane gidigisia (huluane da ode 490), amo ode idi Gode da ilegei dagoi. Ode 490 da gidigisia, Yelusaleme amola dia fi dunu da wadela: i hou amola ledo dialebe hame ba: mu. Wadela: i hou huluane da gogolema: ne olofoi dagoi ba: mu amola eso huluane moloidafa hou amola dafawane hou ba: mu. Amalalu, esala ba: i amola ba: la: lusu liligi huluane da dafawaneyale hamoi ba: mu, amola Gode Ea hadigi Debolo Diasu bu ilegele ligiagale doasi dagoi ba: mu.
“Àádọ́rin ọ̀sẹ̀ ni a pàṣẹ fún àwọn ènìyàn rẹ àti fún àwọn ìlú mímọ́ rẹ láti parí ìrékọjá, láti fi òpin sí ẹ̀ṣẹ̀, láti ṣe ètùtù sí ìwà búburú, láti mú òdodo títí ayé wá, láti ṣe èdìdì ìran àti wòlíì àti láti fi òróró yan Ibi Mímọ́ Jùlọ.
25 Amo huluane noga: le dawa: ma. Ilia da Yelusaleme amo bu gagumusa: sia: mu. Amalalu ode fesu amo fesuale agoane da gidigimu. Amoga gilisili, ode fesu gala 62 agoane amola da gidigimu (huluane da ode 483 da gidigimu). Ilia da Yelusaleme amo gasa bagade bu hiougimu amola ea logo amola gagoi gasa bagade gagumu. Be amo ode ganodini, ilia da se bagade nabimu. Be ode 483 da gidigisia, Gode Ea ilegei Hina Dunu (Mesaia) da doaga: i dagoi ba: mu.
“Nítorí náà, mọ èyí pé, láti ìgbà tí a ti gbé ọ̀rọ̀ náà jáde wí pé kí a tún Jerusalẹmu ṣe, kí a sì tún kọ́, títí dé ìgbà ọmọ-aládé, ẹni òróró náà, alákòóso wa yóò fi dé, ó jẹ́ ọ̀sẹ̀ méje àti ọ̀sẹ̀ méjìlélọ́gọ́ta, a ó sì tún ìgboro àti yàrá rẹ̀ mọ, ṣùgbọ́n ní àkókò wàhálà ni.
26 Amo ode huluane da gidigisia, Gode Ea ilegei Hina dunu da udigili medole legei dagoi ba: mu. Yelusaleme amola Debolo da ga fi dadi gagui gilisisu amola ilia hina bagade amoga mugululi, wadela: lesi dagoi ba: mu. Yelusaleme amola Debolo amo wadela: mu eso da hano bagade neda: i amo ea hou defele ba: mu. Be Gode da amo gegesu amola soge wadela: mu eso ilegei dagoi.
Lẹ́yìn ọ̀sẹ̀ méjìlélọ́gọ́ta, a ó ké Ẹni òróró náà kúrò, kò sì ní ní ohun kan. Àwọn ènìyàn ọmọ-aládé náà tí yóò wá ni yóò pa ìlú náà àti ibi mímọ́ run. Òpin yóò dé bí ìkún omi, ogun yóò máa jà títí dé òpin, a sì ti pàṣẹ ìdahoro.
27 Amo ga fi dadi gagui ilia hina da Isala: ili soge amo ouligisia, e da dunu bagohame ilima ode fesuale amoga gousa: su amola sema hamomu. Be ode osodayale gidigili amola oubi eno gafeyale da udusia, amo esoga, amo hina bagade da Godema gobele salasu amola hahawane iasu amo logo hedofamu. Amola, e da Wadela: idafa Liligi amo Debolo ea gadodafa sogebi amoga ligisimu. Amo liligi da amaiwane diala, amogainini Gode da amo ouligisu dunu wadela: lesimusa: ilegei eso doaga: mu,” Ga: ibaliele da amane sia: i.
Yóò sì fi ìdí i májẹ̀mú kan múlẹ̀ pẹ̀lú ọ̀pọ̀lọpọ̀ fún ọ̀sẹ̀ kan. Ní àárín ọ̀sẹ̀ ni yóò mú òpin bá ẹbọ àti ọrẹ ẹbọ. Àti lórí apá kan ni yóò dà ìríra tí ó mú ìdahoro wá, títí tí òpin tí a ti pàṣẹ lórí asọnidahoro yóò fi padà fi dé bá a.”

< Da:niele 9 >