< A:imose 7 >

1 Na da esala ba: i amo ganodini Ouligisudafa Hina Gode ba: i. Isala: ili hina bagade ea gisi da noi dagoi amola gisi da bu heda: lebe amo esoga Hina Gode da danuba: wa: i bagadedafa hamonanebe ba: i.
Èyí ni ohun tí Olúwa Olódùmarè fihàn mí: Ó pèsè ọwọ́ eṣú lẹ́yìn ìgbà tí a kórè ìpín ọba, ní ìgbà ti èso ẹ̀ẹ̀kejì ń jáde bọ̀.
2 Na esala ba: i amo ganodini, na da danuba: mola: ya: i liligi huluane soge ganodini amo na dagoi ba: i. Amalalu, na da amane sia: i, “Ouligisudafa Hina Gode! Dia fi ilia hou gogolema: ne olofoma! Ilia da habodane esaloma: bela: ! Ilia da fonobahadi amola gasa hame!”
Nígbà tí wọ́n jẹ koríko ilẹ̀ náà mọ́ féfé nígbà náà ni mo gbé ohùn mi sókè pé, “Olúwa Olódùmarè, mo bẹ̀ ọ́, dáríjì! Báwo ni Jakọbu yóò ha ṣe lè dìde? Òun kéré jọjọ!”
3 Hina Gode da Ea asigi dawa: su afadenene, amane sia: i, “Dia esala ba: i amo da dafawane hame ba: mu.”
Olúwa ronúpìwàdà nípa èyí. “Èyí kò ni ṣẹlẹ̀,” ni Olúwa wí.
4 Ouligisudafa Hina Gode da nama esala ba: su eno olelei. E da Ea fi dunu se dabe iasu ima: ne, lalu didilalu. Lalu da hano wayabo bagade osobo hagudu diala amo nei dagoi. Amalalu, lalu da osobo bagade amola amo nemusa: muni nenanu.
Èyí ni ohun ti Olúwa Olódùmarè fihàn mí: Olúwa Olódùmarè ń pè fún ìdájọ́ pẹ̀lú iná; ó jó ọ̀gbun ńlá rún, ó sì jẹ ilẹ̀ run.
5 Amalalu, na amane sia: i, “Hame mabu! Ouligisudafa Hina Gode mae! Dia fi da habodane esaloma: bela: ? Ilia da fonobahadi amola gasa hame!”
Nígbà náà ni mo gbé ohùn mi sókè pé, “Olúwa Olódùmarè jọ̀wọ́ má ṣe ṣe é! Báwo ni Jakọbu yóò ha ṣe lè dìde? Òun kéré jọjọ!”
6 Hina Gode da bu Ea asigi dawa: su afadenene, amane sia: i, “Amo amola da hame ba: mu.”
Olúwa ronúpìwàdà nípa èyí. “Èyí náà kò ní ṣẹlẹ̀,” ni Olúwa Olódùmarè wí.
7 Ouligisudafa Hina Gode da nama esala ba: su eno olelei. Amo ganodini na da Hina Gode dobea gagui (amo da ogoma efe ilegesu amoga defei) amo dafulili lelebe ba: i. Ea lobo ganodini, ogoma efe ilegesu dialebe ba: i.
Èyí ni ohun tí ó fihàn mí: Olúwa dúró ní ẹ̀gbẹ́ odi ti a fi okùn ìwọ̀n mọ́, ti òun ti okùn ìwọ̀n tí ó rún ni ọwọ́ rẹ̀.
8 E da nama amane adole ba: i, “A: imose! Di da adi ba: sala: ?” Na da bu adole i, “Na da ogoma efe ilegesu ba: sa!” Amalalu, E da nama amane sia: i, “Amoga Na da dima olelesa. Na fi dunu da dobea noga: le hame ilegele gagui defele esala. Na da ilima se dabe iasu ima: ne Na asigi dawa: su bu hame afadenemu.
Olúwa sì bi mi pé, “Amosi, kí ni ìwọ rí?” Mo dáhùn pé, “Okùn ìwọ̀n.” Nígbà náà ni Olúwa wí pé, “Wò ó, Èmí ń gbé okùn ìwọ̀n kalẹ̀ láàrín àwọn Israẹli ènìyàn mi; Èmi kì yóò sì tún kọjá lọ́dọ̀ wọn mọ́.
9 Aisage egaga fi ilia nodone sia: ne gadosu sogebi huluane da wadela: lesi dagoi ba: mu. Isala: ili soge hadigi sogebi huluane da wadela: lesi dagoi ba: mu. Na da hina bagade Yelouboua: me ea fi hina bagade hou huluane wadela: lesi dagomu.”
“Ibi gíga Isaaki wọ̀n-ọn-nì yóò sì di ahoro àti ibi mímọ Israẹli wọ̀n-ọn-nì yóò di ahoro. Èmi yóò sì fi idà dìde sí ilé Jeroboamu.”
10 A: masaia, Bedele gobele salasu dunu, da Yelouboua: me (Isala: ili hina bagade) ema sia: ne iasi amane, “A: imose da di wadela: ma: ne dunu huluane ilima hohonone sia: daha. Ea sia: da ninia soge fi huluane wadela: lesimu.
Nígbà náà Amasiah àlùfáà Beteli ránṣẹ́ sí Jeroboamu ọba Israẹli, wí pé: “Amosi ti dìde láti dìtẹ̀ sí ọ ni àárín gbùngbùn Israẹli. Ilẹ̀ kò sì le gba gbogbo ọ̀rọ̀ rẹ̀.
11 E da amane sia: daha, ‘Yelouboua: me da gegesu ganodini bogomu. Isala: ili fi dunu huluane da ilia sogega fadegale, ga soge amo ganodini mugululi asi dagoi ba: mu.’”
Nítorí èyí ni ohun ti Amosi ń sọ: “‘Jeroboamu yóò ti ipa idà kú, lóòtítọ́ Israẹli yóò lọ sí ìgbèkùn, jìnnà kúrò ní ilẹ̀ ìní wọn.’”
12 Amalalu, A:masaia da A: imosema amane sia: i, “Balofede dunu! Ouiya: ma! Eno hame! Di Yuda sogega buhagili, amogai dia sia: olelema. Ilia fawane da dia sia: beba: le, bidi imunu da defea.
Nígbà náà ni Amasiah sọ fún Amosi pé, “Lọ jáde, ìwọ aríran! Padà sí ilẹ̀ àwọn Juda. Kí o máa jẹun rẹ níbẹ̀, kí o sì máa sọtẹ́lẹ̀ rẹ̀ níbẹ̀.
13 Be Bedele moilai guiguda: ba: la: lusu sia: bu mae sia: ma. Bai amo sogebi da Isala: ili hina bagade ea nodone sia: ne gadosu sogebi amola Isala: ili fi ilia Debolo sogebi.”
Má ṣe sọtẹ́lẹ̀ mọ ni Beteli nítorí ibi mímọ́ ọba ni àti ibi tẹmpili ìjọba rẹ̀.”
14 A: imose da bu adole i, “Na da bidi lama: ne ba: la: lusu hou hame hamosa. Na da sibi ouligisu dunu amola figi ifa ouligisu dunu.
Amosi dá Amasiah lóhùn pé, “Èmi kì í ṣe wòlíì tàbí àwọn ọmọ wòlíì, ṣùgbọ́n mo jẹ́ olùṣọ́-àgùntàn, mo sì ń ṣe ìtọ́jú igi ọ̀pọ̀tọ́ sikamore.
15 Be Hina Gode da na sibi ouligisu hawa: hamosu fisili, ea fi Isala: ili dunuma fa: no misunu hou olelema: ne sia: i.
Ṣùgbọ́n Olúwa mu mi bí mo ti ń tọ́ agbo ẹran lẹ́yìn, ó sì wí fun mi pé, ‘Lọ sọtẹ́lẹ̀ fun àwọn Israẹli ènìyàn mi.’
16 Amaiba: le, wali Hina Gode Ea sia: nabima! Di da nama na da ba: la: lusu fisili, Isala: ili dunuma dadousa gagabosu sia: bu mae hamoma: ne sia: sa.
Nítorí náà nísinsin yìí, gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa. Ìwọ wí pé, “‘Má ṣe sọ àsọtẹ́lẹ̀ sí Israẹli, má sì ṣe wàásù sí ilé Isaaki.’
17 Amaiba: le, A:masaia, Hina Gode da dima amane sia: sa, ‘Dia uda da di fisili, udigili moilai bai bagade ganodini ea da: i dunuma udigili bidi lamu. Amola dia mano huluane gegesu ganodini medole legei dagoi ba: mu. Dia soge da fifili, eno dunuma i dagoi ba: mu. Amola disu da Gode Ea hou hame lalegagui ga soge amo ganodini bogomu. Amola Isala: ili dunu da dafawane ilia sogega fadegale, eno sogega mugululi asi dagoi ba: mu.”
“Nítorí náà, èyí ni ohun ti Olúwa wí: “‘Ìyàwó rẹ yóò di panṣágà ni ìlú, àwọn ọmọ ọkùnrin àti obìnrin rẹ yóò ti ipa idà ṣubú. A ó fi okùn wọn ilẹ̀ rẹ, a ó sì pín in àti ìwọ pẹ̀lú yóò kú ni ilẹ̀ àìmọ́. Israẹli yóò sì lọ sí ìgbèkùn, kúrò ní ilẹ̀ ìní wọn.’”

< A:imose 7 >