< Asunasi Dunu Ilia Hou 28 >
1 Ninia bega: hahawane doaga: i. Amalalu, ninia da amo oga ea dio da Moloda nabi.
Nígbà tí gbogbo wa sì yọ tan ni àwa tó mọ̀ pé, Mẹlita ni a ń pè erékùṣù náà.
2 Amo soge fi dunudafa da ninima asigi hamoi. Gibu da muni dabeba: le, ninia anegagi nabi. Be ilia lalu didilalu, nini huluane bagadewane fidisu.
Kì í ṣe oore díẹ̀ ni àwọn aláìgbédè náà ṣe fún wa. Nítorí ti wọ́n dáná, wọ́n sì gbà gbogbo wa sí ọ̀dọ̀ nítorí òjò ń rọ nígbà náà, àti nítorí òtútù.
3 Bolo da lalu ifa gilisili, laluga ligisilaloba, medosu sania da gia: i nababeba: le, amo lalu ifaga gadili misini, Bolo ea lobo gasonaloba besega gagui.
Nígbà tí Paulu sì ṣa ìdí ìṣẹ́pẹ́ igi jọ, ti ó sì kó o sínú iná, paramọ́lẹ̀ kan ti inú oru-iná jáde, ó di mọ́ ọn ní ọwọ́.
4 Dunudafa ilia da sania amo Bolo ea loboga gagulalebe ba: beba: le, gilisili amane sia: dasu, “Amabela: ? Amo dunu da fasu dunu. Be e da fo amola hano gafului, amoga hame bogoi. Be wali Osobo Bagade Ouligisu Hou da e medole legemusa: dawa: lala!”
Bí àwọn aláìgbédè náà sì ti rí ẹranko olóró náà tí ó dì mọ́ ọn lọ́wọ́, wọ́n bá ara wọn sọ pé, “Dájúdájú apànìyàn ni ọkùnrin yìí, ẹni ti ó yọ nínú Òkun tan, ṣùgbọ́n tí ẹ̀san kò sì jẹ́ kí ó wà láààyè.”
5 Be Bolo da ea lobo fofoga: beba: le, sania da laluma sa: i. Amola Bolo da hame oloi.
Òun sì gbọn ẹranko náà sínú iná ohunkóhun kan kò sì ṣe é.
6 Ilia da e da hedolowane fofale, dafane, bogomu, amo ba: musa: ouesalu. Be sedagawane ouesalu, hou hisu da hame doaga: beba: le, ilia asigi dawa: su afadenene, amane sia: i, “E da ‘gode’ agoane!”
Ṣùgbọ́n wọn ń wòye ìgbà tí yóò wù, tàbí tí yóò sì ṣubú lulẹ̀ láti kú lójijì; nígbà tí wọ́n wò títí, tí wọn kò sì rí nǹkan kan kí ó ṣe é, wọ́n pa èrò wọn dà pé, òrìṣà kan ni ọkùnrin yìí.
7 Amo sogebi gadenene, oga ouligisu dunu, ea dio amo Babaliase, e da ifabi gagui galu. E da nini hahawane yosia: le, ninima eso udiana agoane aowai.
Ní agbègbè ibẹ̀ ni ilé ọkùnrin ọlọ́lá erékùṣù náà wà, orúkọ ẹni tí a ń pè ní Pubiliu; ẹni tí ó ti ipa inú rere gbà wá sí ọ̀dọ̀ fún ọjọ́ mẹ́ta.
8 Babaliase eda da asugi amola hagomo se oloiba: le, diaheda: su da: iya esalu. Bolo da ea diasu ganodini golili sa: ili, Godema sia: ne gadole, ea lobo ema ligisili, e uhinisi dagoi.
Ó sì ṣe, baba Pubiliu dùbúlẹ̀ àìsàn ibà àti ìgbẹ́-ọ̀rìn; ẹni tí Paulu wọlé tọ̀ lọ, tí ó sì gbàdúrà fún, nígbà tí ó sì fi ọwọ́ lé e, ó sì mú un láradá.
9 Amo sia: nababeba: le, oloi dunu huluane amo oga ganodini esalu da Boloma misini, uhi dagoi ba: i.
Nígbà tí èyí sì ṣetán, àwọn ìyókù tí ó ni ààrùn ni erékùṣù náà tọ̀ ọ́ wá, ó sì mú wọn láradá.
10 Ilia da ninima liligi bagohame i. Ninia amo soge fisimusa: dawa: beba: le, ninia dusagai ganodini ilia ha: i manu amola liligi huluane, ninia ahoabe ouligima: ne defele ligisi.
Wọ́n sì bu ọlá púpọ̀ fún wa; nígbà tí a ń lọ, wọ́n sì fún wa ní ohun púpọ̀ tí a nílò ní ọ̀nà àjò wa.
11 Oubi udiana aligili, ninia da dusagai (amo da A: legesa: nadalia moilaiga misini, anegagi oubi ganodini Moloda oga amoga ouesalu. Dusagai ea dio amo da “‘gode’ Aduna Eso Afadafa Lalelegei.”) amo ganodini fila heda: le, yolesili asi.
Lẹ́yìn oṣù mẹ́ta, a wọ ọkọ̀ ojú omi kan èyí tí ó lo àkókò òtútù ní erékùṣù náà. Ó jẹ́ ọkọ̀ ojú omi ti Alekisandiria, èyí tí àmì rẹ̀ jẹ́ tí òrìṣà ìbejì ti Kasitoru òun Polukisu.
12 Asili, ninia da Silagiusi moilai bai bagadega doaga: le, eso udiana ouesalu.
Nígbà tí a sì gúnlẹ̀ ní Sirakusi, a gbé ibẹ̀ fún ọjọ́ mẹ́ta.
13 Yolesili asili, ninia Lidiame moilai bai bagadega doaga: i. Golale hahabe, fo da ga (south) mabe ba: beba: le, eso adunaga asili, Biudioli moilaiga doaga: i.
Láti ibẹ̀ nígbà tí a lọ yíká; a dé Regiomu: nígbà tí ó sì di ọjọ́ kejì, afẹ́fẹ́ gúúsù bẹ̀rẹ̀ sí ní fẹ́, ní ọjọ́ kejì rẹ̀ a sì dé Puteoli.
14 Amo moilaiga, ninia da eno Yesu Ea hou lalegagui dunu ba: i. Ilia da ninima sia: beba: le, nini da ili amola hi afadafa sigi esalu. Yolesili asili, ninia Louma moilai bai bagadega doaga: i.
A sì rí àwọn arákùnrin kan níbẹ̀, tí wọ́n sì bẹ̀ wá láti bá wọn gbé fún ọjọ́ méje: bẹ́ẹ̀ ni a sì lọ sí ìhà Romu.
15 Louma moilai bai bagadega, Yesu Ea hou lalegagui dunu da ninia doaga: be nababeba: le, Louma yolesili, mogili da A: biase Bidi Lama: ne diasu amola Ga Misi Dunu Diasu Udiana moilaiga nini yosia: la misi. Bolo da amo dunu ba: beba: le, Godema nodoi. Ea dogo da bagadewane denesi dagoi.
Àwọn arákùnrin ibẹ̀ gbúròó pé a ń bọ̀, wọ́n sì rìnrìn àjò títí wọ́n fi dé Apii Foroni àti sí ilé èrò mẹ́ta láti pàdé wa: nígbà tí Paulu sì rí wọn, ó dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run, ó sì mú ọkàn le.
16 Ninia Louma moilaiga doaga: loba, Louma gamane dunu da sia: beba: le, Bolo da hisu diasu ganodini esalu. Dadi gagui dunu afadafa fawane da e sosodo aligisu.
Nígbà tí a sì dé Romu, olórí àwọn ọmọ-ogun fi àwọn òǹdè lé olórí ẹ̀ṣọ́ lọ́wọ́, ṣùgbọ́n wọ́n gba Paulu láààyè láti máa dágbé fún ara rẹ̀ pẹ̀lú ọmọ-ogun tí ó ń ṣọ́ ọ.
17 Eso udiana aligili, Bolo da Yu ouligisu dunu amo soge ganodini esalu, amo fofada: musa: misa: ne sia: i. Ilia da gilisibiba: le, e da ilima amane sia: i, “Na fi Isala: ili dunu! Na da ninia sema amo ninia aowalali olelei liligi, amo na da hamedafa wadela: lesi. Be Yelusaleme Yu fi dunu ilia hanaiba: le, Louma gamane dunu da na se dabe iasu diasu ganodini sali.
Lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́ta, Paulu pe àwọn olórí Júù jọ. Nígbà tí wọ́n sì péjọ, ó wí fún wọn pé, “Ẹ̀yin ara, bí ó ti ṣe pé èmi kò ṣe ohun kan lòdì sí àwọn ènìyàn, tàbí sí àṣà àwọn baba wa, síbẹ̀ wọ́n fi mí lé àwọn ara Romu lọ́wọ́ ní òǹdè láti Jerusalẹmu wá.
18 Louma gamane dunu ilia da nama fofada: nanu, na hou ganodini se imunusa: fofada: mu liligi hame ba: beba: le, na se dabe iasu diasu logo doasimusa: dawa: i galu.
Nígbà tí wọ́n sì wádìí ọ̀ràn mi, wọ́n fẹ́ jọ̀wọ́ mi lọ́wọ́ lọ, nítorí tí wọn kò rí ẹ̀sùn kan tí ó tọ́ sí ikú pẹ̀lú mi.
19 Be Yu dunu da na se dabe iasu diasu logo doasimu higa: iba: le, ougiwane bu fofada: i. Amaiba: le, na da Louma gamane ouligisudafa fofada: mu, amo logo fawane ba: i. Be na da na fi dunu ilima diwaneya udidimu hamedei galebe.
Ṣùgbọ́n nígbà tí àwọn Júù sọ̀rọ̀ lòdì sí i, èyí sún mí láti fi ọ̀ràn náà lọ Kesari, kì í ṣe pe mo ní ẹ̀sùn kan láti fi kan àwọn ènìyàn mi.
20 Amaiba: le, na da dili ba: mu amola dilima sia: sa: imusa: , dawa: i galu. Na da Dunu amo E hobea misunu Isala: ili dunu ilia da dafawane hamoma: beyale dawa: lusu, amo Ea hou dafawaneyale dawa: beba: le, na da amo sia: inega la: gi dagoi!”
Ǹjẹ́ nítorí ọ̀ràn yìí ni mo ṣe ránṣẹ́ pè yín, láti rí yín àti láti bá yín sọ̀rọ̀ nítorí pé, nítorí ìrètí Israẹli ni a ṣe fi ẹ̀wọ̀n yìí dè mí.”
21 Yu ouligisu dunu ilia da Boloma bu adole i, “Yudia soge fi dunu ilia da dia hou olelema: ne, ninima meloa hamedafa dedei. Amola ninia fi dunu da amo sogega misini, di da wadela: le hamoi, amo da hame sia: i.
Wọ́n sì wí fún un pé, “Àwa kò rí ìwé gbà láti Judea nítorí rẹ, bẹ́ẹ̀ ni ẹnìkan nínú àwọn arákùnrin tí ó ti ibẹ̀ wá kò ròyìn, tàbí kí ó sọ̀rọ̀ ibi kan sí ọ.
22 Be dunu huluane da dia gilisisu (Yesu Ea fa: no bobogesu fi) ilima halalewane sia: beba: le, ninia dia hou nabimu hanai gala!”
Ṣùgbọ́n àwa ń fẹ́ gbọ́ lẹ́nu rẹ ohun tí ìwọ rò nítorí bí ó ṣe ti ẹgbẹ́ ìlànà yìí ní, àwa mọ̀ pé, níbi gbogbo ni a ń sọ̀rọ̀ lòdì sí i.”
23 Amaiba: le ilia amola Bolo da fofada: mu eso ilegele, amo esoga dunu bagohame da Bolo ea esalebe diasuga misi. Hahabe muni olelesa asili, amoganini gasi, e da Gode Ea Hinadafa Hou ilima olelei. Ilia da Yesu Ea hou dafawaneyale dawa: ma: ne, e da Mousese ea Sema amola balofede dunu ilia dedei, amo ilima olelei.
Àwọn fi ẹnu kò lórí ọjọ́ tí wọn yóò ṣe ìpàdé pẹ̀lú Paulu, ọ̀pọ̀lọpọ̀ wọn ni ó tọ̀ ọ́ wa ni ilé àgbàwọ̀ rẹ̀; àwọn ẹni tí òun sọ àsọyé ọ̀rọ̀ ìjọba Ọlọ́run fún, ó ń yí wọn padà nípa ti Jesu láti inú òfin Mose àti àwọn wòlíì, láti òwúrọ̀ títí ó fi di àṣálẹ́.
24 Mogili da ea sia: nababeba: le, dafawaneyale dawa: i galu. Be eno da higabeba: le, dafawaneyale hame dawa: i.
Àwọn ẹlòmíràn gba ohun tí ó wí gbọ́, bẹ́ẹ̀ ni àwọn ẹlòmíràn kò sì gbà á gbọ́.
25 Amaiba: le, ilia fisili asili, mogisu sia: gilisili sia: dasu. Be Bolo da hidadea sia: afadafa fawane sia: i galu, amane, “Dafawane! Gode Ea A: silibu Hadigidafa Gala da ninia aowalalima Aisaia ea lafidili dafawane sia: i.
Nígbà tí ohùn wọn kò ṣọ̀kan láàrín ara wọn, wọ́n túká, lẹ́yìn ìgbà tí Paulu sọ̀rọ̀ kan pé, “Ẹ̀mí Mímọ́ sọ òtítọ́ fún àwọn baba yín nígbà tí ó sọ láti ẹnu wòlíì Isaiah wí pé:
26 E amane sia: i, ‘Masa! Amo dunuma agoane sia: ma. Dilia da gega nabalumu be hamedafa dawa: mu. Dilia da siga hogoi helelalumu be hame ba: mu.
“‘Tọ àwọn ènìyàn wọ̀nyí lọ, kí ó sì wí pé, “Ní gbígbọ́ ẹ̀yin yóò gbọ́, kì yóò sì yé e yín; à ti ní rí rí ẹ̀yin yóò rí, ẹ̀yin kì yóò sí wòye.”
27 Bai amo dunu ilia asigi dawa: su da igi agoai gala. Ilia ge ilisu ga: i dagoi. Ilia si ilisu da dofoi dagoi. Agoane hame hamoi ganiaba, ilia si da ba: la: loba, ilia ge da nabana: noba, ilia asigi dawa: su da dawa: la: loba, amola ilia da Nama sinidigili, Na da ili uhinisila: loba, Gode da sia: sa.’
Nítorí ti àyà àwọn ènìyàn yìí yigbì, etí wọn sì wúwo láti fi gbọ́, ojú wọn ni wọn sì ti di. Nítorí kí wọn má ba à fi ojú wọn rí, kí wọn kí ó má ba à fi etí wọn gbọ́, àti kí wọn má ba à fi ọkàn wọn mọ̀, kí wọn kí ó má ba à yípadà, àti kí èmi má ba à mú wọn láradá.’
28 Bolo da sia: dagomusa: amane sia: i, “Dilia noga: le dawa: ma! Gode da Ea Sia: Ida: iwane gala amo osobo bagade dunuma gaga: su sia: , Dienadaile dunuma iasi dagoi. Dienadaile dunu da nabimu!”
“Ǹjẹ́ kí ẹ̀yin mọ́ èyí pé, a rán ìgbàlà Ọlọ́run sí àwọn kèfèrí wọ́n ó sì gbọ́!”
29 Bolo da amo sia: sia: beba: le, Yu dunu da gilisili sia: ga gegenanu, yolesili asi.
30 Amalalu, ode aduna amoga Bolo da amo diasu ganodini esalu. Amogawi esaloma: ne, e da bidi i. Amola dunu huluane amo da ema gousa: musa: mabeba: le, e da hahawane yosia: su.
Paulu sì gbé ilé àgbàwọ̀ rẹ̀ lọ́dún méjì gbáko, ó sì ń gbà gbogbo àwọn tí ó wọlé tọ̀ ọ́ wá.
31 E da mae beda: iwane, Gode Ea Hinadafa Hou amola Hina Gode Yesu Gelesu Ea hou gasawane amola halegalewane olelelalu. Sia: Ama Dagoi
Ó ń wàásù ìjọba Ọlọ́run, ó ń fi ìgboyà kọ́ni ní àwọn ohun tí i ṣe ti Jesu Kristi Olúwa, ẹnìkan kò si dá a lẹ́kun.