< 2 Sa:miuele 9 >

1 Eso afaega, Da: ibidi da amane adole ba: i, “Solo ea sosogo fi dunu afae da esalabala? Amai galea, na da Yonada: nema asigiba: le, ema asigi hou olelemu hanai gala.”
Dafidi sì béèrè pé, ọ̀kan nínú àwọn ẹni tí ń ṣe ìdílé Saulu kù síbẹ̀ bí? Kí èmi lè ṣe oore fún un nítorí Jonatani.
2 Solo ea sosogo fi hawa: hamosu dunu afae amo ea dio Siba da esalebe ba: i. Ilia da e Da: ibidima masa: ne sia: i. Da: ibidi da ema amane adole ba: i, “Di da Sibala: ?” E bu adole i, “Ma! Hina noga: idafa! Na da dia hawa: hamosu dunu!”
Ìránṣẹ́ kan sì ti wà ní ìdílé Saulu, orúkọ rẹ̀ sí ń jẹ́ Ṣiba, wọ́n sì pè é wá sọ́dọ̀ Dafidi, ọba sì béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé, “Ìwọ ni Ṣiba bí?” Ó sì dáhùn wí pé, “Ìránṣẹ́ rẹ ni.”
3 Hina bagade Da: ibidi da ema amane adole ba: i, “Solo ea sosogo fi dunu afae esalabala? Na da na Godema ilegei defele, agoai dunuma asigi hou olelemusa: dawa: lala.” Siba da bu adole i, “Yonada: ne egefe afadafa fawane da esala. E da gasuga: igi gala.”
Ọba sì wí pé, “Kò ha sí ọ̀kan nínú ìdílé Saulu síbẹ̀, kí èmi ṣe oore Ọlọ́run fún un?” Ṣiba sì wí fún ọba pé, “Jonatani ní ọmọ kan síbẹ̀ tó ya arọ.”
4 Da: ibidi da adole ba: i, “E da habidili esalabala?” Siba da adole i, “E da Loudiba sogega, Ma: ige (A: miele egefe) amo ea diasua esala.”
Ọba sì wí fún un pé, “Níbo ni ó gbé wà?” Ṣiba sì wí fún ọba pé, “Wò ó, òun wà ní ilé Makiri, ọmọ Ammieli, ní Lo-Debari.”
5 Amaiba: le, Da: ibidi da Mifibousiede ema misa: ne sia: si.
Dafidi ọba sì ránṣẹ́, ó sì mú un láti ilé Makiri ọmọ Ammieli láti Lo-Debari wá.
6 Mifibousiede (Yonada: ne egefe amola Solo ea aowa) da doaga: loba, e da Da: ibidima nodoma: ne, e midadi begudui. Da: ibidi da amane sia: i, “Mifibousiede!” E bu adole i, “Hina noga: idafa! Na da dia hawa: hamosu dunu!”
Mefiboṣeti ọmọ Jonatani ọmọ Saulu sì tọ Dafidi wá, ó sì wólẹ̀ níwájú rẹ̀, ó sì bú ọlá fún un. Dafidi sì wí pé, “Mefiboṣeti!” Òun sì dáhùn wí pé, “Wò ó, ìránṣẹ́ rẹ!”
7 Da: ibidi da amane sia: i, “Mae beda: ma! Na da dia ada Yonada: ne dawa: beba: le, dima asigiwane hamomu. Na da soge huluane amo dia aowa ea gagui, amo dima bu imunu. Amola di da eso huluane na diasuga ha: i manu da defea.”
Dafidi sì wí fún un pé, “Má ṣe bẹ̀rù, nítorí pé nítòótọ́ èmi ó ṣe oore fún ọ nítorí Jonatani baba rẹ, èmi ó sì tún fi gbogbo ilé Saulu baba rẹ fún ọ, ìwọ ó sì máa bá mi jẹun nígbà gbogbo ní ibi oúnjẹ mi.”
8 Mifibousiede da bu beguduli, amane sia: i, “Hina noga: idafa! Na hou da wa: me bogoi amo ilia hou hame baligisa. Nama da noga: i hou agoai da hame hamomu galu.”
Mefiboṣeti sì tẹríba, ó sì wí pé, “Kí ni ìránṣẹ́ rẹ jásí, tí ìwọ ó fi máa wo òkú ajá bí èmi.”
9 Amalalu, Da: ibidi da Solo ea hawa: hamosu dunu, Siba, amo ema misa: ne wele sia: ne, ema amane sia: i, “Na da dia hina ea aowa amo Mifibousiede, ema liligi huluane amo Solo amola ea sosogo ilia musa: gagui liligi, amo ema bu imunu.
Ọba sì pe Ṣiba ìránṣẹ́ Saulu, ó sì wí fún un pé, “Gbogbo nǹkan tí í ṣe ti Saulu, àti gbogbo èyí tí í ṣe ti ìdílé rẹ̀ ni èmi fi fún ọmọ olúwa rẹ.
10 Di amola diagofelali amola dia hawa: hamosu dunu da Solo ea sosogo fi ilima ha: i manu ima: ne, ea soge amoga ha: i manu bugimu amola dadamini gaguli misa. Be Mifibousiede e fawane da eso hulu nina: ha: i nasu fafai amogai nasu hamomu.” (Siba egefelali da15agoane ba: i, amola ea hawa: hamosu dunu da 20 agoane esalu).
Ìwọ, àti àwọn ọmọ rẹ, àti àwọn ìránṣẹ́ rẹ ni yóò sì máa ro ilẹ̀ náà fún un, ìwọ ni yóò sì máa mú ìkórè wá, ọmọ olúwa rẹ yóò sì máa rí oúnjẹ jẹ, ṣùgbọ́n Mefiboṣeti ọmọ olúwa rẹ yóò sì máa bá mi jẹun nígbà gbogbo ní ibi oúnjẹ mi.” (Ṣiba sì ní ọmọ mẹ́ẹ̀ẹ́dógún àti ogún ìránṣẹ́kùnrin.)
11 Siba da bu adole i, “Hina noga: idafa! Na da dia hamoma: ne sia: i huluane amo defele hamomu!” Amaiba: le, Mifibousiede da hina bagade egefelali defele, Da: ibidi ea ha: i nasu fafai amoga fili, ha: i nasu.
Ṣiba sì wí fún ọba pé, “Gẹ́gẹ́ bí gbogbo èyí tí olúwa mi ọba ti pàṣẹ fún ìránṣẹ́ rẹ, bẹ́ẹ̀ náà ni ìránṣẹ́ rẹ ó ṣe.” Ọba sì wí pé, “Ní ti Mefiboṣeti, yóò máa jẹun ní ibi oúnjẹ mi, gẹ́gẹ́ bí ọ̀kan nínú àwọn ọmọ ọba.”
12 Mifibousiede da goi mano ea dio Maiga esalu. Siba ea sosogo huluane da Mifibousiede ea hawa: hamosu lai.
Mefiboṣeti sì ní ọmọ kékeré kan, orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Mika. Gbogbo àwọn tí ń gbé ní ilé Ṣiba ni ó sì ń ṣe ìránṣẹ́ fún Mefiboṣeti.
13 Amalalu, Mifibousiede (ea emo aduna da gasuga: igi galu) e da Yelusaleme moilai bai bagadega esalu. E da ea ha: i manu huluane amo hina bagade ea ha: i nasu fafai amoga nasu.
Mefiboṣeti sì ń gbé ní Jerusalẹmu, òun a sì máa jẹun nígbà gbogbo ní ibi oúnjẹ ọba; òun sì yarọ ní ẹsẹ̀ rẹ̀ méjèèjì.

< 2 Sa:miuele 9 >