< 2 Sa:miuele 5 >

1 Amalalu, Isala: ili fi huluane da Hibalone moilai bai bagadega Da: ibidima misini, ema amane sia: i, “Ninia da di defele maga: me amola hu afadafa fawane gala.
Gbogbo ẹ̀yà Israẹli sì tọ Dafidi wá ní Hebroni, wọ́n sì wí pé, “Ẹran-ara rẹ àti ẹ̀jẹ̀ rẹ ni àwa ń í ṣe.
2 Musaga, Solo da ninia hina bagade esaloba, di da Isala: ili dunu oule gegena ahoasu. Amola, Hina Gode da di Ea fi bisilua amola ouligisu hamoma: ne, ilegei dagoi.”
Àti nígbà àtijọ́, nígbà tí Saulu fi jẹ ọba lórí wa, ìwọ ni ẹni tí ó máa ń kó Israẹli jáde, ìwọ sì ni ó máa ń mú wọn bọ̀ wá ilé: Olúwa sì wí fún ọ pé, ‘Ìwọ yóò ṣe olùṣọ́ Israẹli àwọn ènìyàn mi, ìwọ yóò sì jẹ́ olórí fún Israẹli.’”
3 Amaiba: le, Isala: ili ouligisu dunu huluane da Hibalone moilai bai bagadega Da: ibidima misi. E amola ilia da gousa: su sema hamoi. Ilia da Da: ibidima susuligi sogagala: le, e Isala: ili hina bagade hamoma: ne ilegei.
Gbogbo àgbàgbà Israẹli sì tọ ọba wá ní Hebroni, Dafidi ọba sì bá wọn ṣe àdéhùn kan ní Hebroni, níwájú Olúwa: wọ́n sì fi òróró yan Dafidi ní ọba Israẹli.
4 Da: ibidi da lalelegele, ode30agoane gidigili esalu, hina bagade hawa: hamosu bai muni hamoi. E da ode 40 agoane Isala: ili fi ouligilalu.
Dafidi sì jẹ́ ẹni ọgbọ̀n ọdún nígbà tí ó jẹ ọba; ó sì jẹ ọba ní ogójì ọdún.
5 E da Hibalone moilai bai bagadega esalu, Yuda soge ode fesuale amola oubi gafeyale agoane ouligi. Amola e da Yelusaleme moilai bai bagade amoga esalu, ode33 agoane Isala: ili amola Yuda gilisili ouligisu.
Ó jẹ ọba ní Hebroni ní ọdún méje àti oṣù mẹ́fà lórí Juda, ó sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu ní ọdún mẹ́tàlélọ́gbọ̀n lórí gbogbo Israẹli àti Juda.
6 Hina Da: ibidi amola ea dunu da Yelusaleme moilai bai bagade doagala: musa: asi. Yebiusaide dunu da amogawi esalu. Ilia da Da: ibidi da ilima hasalimu da hamedei agoane dawa: i. Ilia da ema amane sia: i, “Di da ninia moilaiga doagala: le golili sa: imu da hamedeidafa. Si dofoi dunu amola gasuga: igi dunu da dia nini mae hasalima: ne gaga: mu da defele ba: mu.”
Àti ọba àti àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ sì lọ sí Jerusalẹmu sọ́dọ̀ àwọn ará Jebusi, àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà; àwọn tí ó sì ti wí fún Dafidi pé, “Bí kò ṣe pé ìwọ bá mú àwọn afọ́jú àti àwọn arọ kúrò, ìwọ kì yóò wọ ìhín wá.” Wọ́n sì wí pé, “Dafidi kì yóò lè wá síyìn-ín.”
7 (Be Da: ibidi da ilia gagili sali moilai amo Saione amoma gegenanu fedele lai. Fa: no ilia da amo moilai dio “Da: ibidi ea Moilai Bai Bagade” asuli.)
Ṣùgbọ́n Dafidi fi agbára gba ìlú odi Sioni: èyí náà ni í ṣe ìlú Dafidi.
8 Amo esoha, Da: ibidi da ea dunuma amane sia: i, “Dunu mogili amo da na defele Yebiusaide dunuma higabeba: le, ili fuga: musa: hanabela: ? Amai galea, amo hano osobaha golili ahoasu logo amoga heda: le, amo hahani si dofoi amola gasuga: igi dunu doagala: ma.” (Amaiba: le, dunu da wali agoane sia: sa, “Si dofoi amola gasuga: igi dunu da Hina Gode Ea diasu ganodini golili sa: imu hamedei gala.”)
Dafidi sọ lọ́jọ́ náà pé, “Ẹnikẹ́ni tí yóò kọlu àwọn ará Jebusi, jẹ́ kí ó gba ojú àgbàrá, kí o sí kọlu àwọn arọ, àti àwọn afọ́jú tí ọkàn Dafidi kórìíra.” Nítorí náà ni wọ́n ṣe wí pé, “Afọ́jú àti arọ wà níbẹ̀, kì yóò lè wọlé.”
9 Da: ibidi da gagili sali moilai doagala: le fefedei dagolalu, e da amo ganodini esalusu. E da amo moilai dio “Da: ibidi ea Moilai Bai Bagade” asuli. E da sogebi amo da agolo gusudili dialebe (amoga ilia da osobo dogone fa: su) amogai muni sisiga: le moilai bai bagade diasu gagui.
Dafidi sì jókòó ní ilé àwọn ọmọ-ogun tí ó ní odi, a sì ń pè é ní ìlú Dafidi. Dafidi mọ ògiri yí i ká láti Millo wá, ó sì kọ́ ilé nínú rẹ̀.
10 Ea gasa da heda: lalu. Bai Hina Gode Bagadedafa da e fidisu.
Dafidi sì ń pọ̀ sí i, Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun sì wà pẹ̀lú rẹ̀.
11 Daia soge hina bagade amo Haila: me, da Da: ibidima bidi lasu dunu asunasi. E da Da: ibidima dolo ifa bagohame i. Amola e da Da: ibidi fidima: ne, diasu gagusu dunu amola gelega diasu gagusu dunu ema asunasi.
Hiramu ọba Tire sì rán àwọn ìránṣẹ́ sí Dafidi, àti igi kedari, àti àwọn gbẹ́nàgbẹ́nà, àti àwọn tí ń gbẹ́ òkúta, wọ́n kọ́ ilé kan fún Dafidi.
12 Amaiba: le, Da: ibidi da amane dawa: i. Hina Gode da ema hina bagade hou hahamoi dagoi. Amola Hina Gode da Ea fi ilima asigiba: le, Da: ibidi e hina bagade hou amoga hasalima: ne amola bagade gagusu dunu fi esaloma: ne hamoi.
Dafidi sì kíyèsi i pé, Olúwa ti fi ìdí òun múlẹ̀ láti jẹ ọba lórí Israẹli, àti pé, ó gbé ìjọba rẹ̀ ga nítorí Israẹli àwọn ènìyàn rẹ̀.
13 Da: ibidi da Hibalone moilai bai bagade amo yolesili, Yelusaleme moilai bai bagadega fimusa: asi. Amogalu, e da gidisedagi uda enoenoia amola udadafa enoenoia lai. Amola e da dunu mano amola uda mano enoenoia lalelelegei.
Dafidi sì tún mú àwọn àlè àti aya sí i láti Jerusalẹmu wá, lẹ́yìn ìgbà tí ó ti Hebroni bọ̀, wọ́n sì bí ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin fún Dafidi.
14 E da Yelusaleme moilai bai bagadega esaloba, mano dedei goelali lalelelegei, ilia dio da Sia: miua, Sioubabe, Na: ida: ne, Soloumane, Ibaha, Elisiua, Nifege, Yafaia, Ilisiama, Ilaiada amola Ilifelede.
Èyí sì ni orúkọ àwọn tí a bí fún un ní Jerusalẹmu; Ṣammua, Ṣobabu, Natani àti Solomoni.
Àti Ibhari, àti Eliṣua, àti Nefegi, àti Jafia.
Àti Eliṣama, àti Eliada, àti Elifeleti.
17 Filisidini dunu da Da: ibidi Isala: ili hina bagade hamoi, amo sia: nabi. Amaiba: le, ilia dadi gagui wa: i da Da: ibidi suguli lamusa: muni ahoanu. Da: ibidi da amo hou nababeba: le, gagili sali sogebi amoga asi.
Ṣùgbọ́n nígbà tí àwọn Filistini gbọ́ pé, wọ́n ti fi Dafidi jẹ ọba lórí Israẹli, gbogbo àwọn Filistini sì gòkè wá láti wá Dafidi; Dafidi sì gbọ́, ó sì sọ̀kalẹ̀ lọ sí ìlú olódi.
18 Filisidini dunu da Lifa: ime Fago amoga misini gesowai.
Àwọn Filistini sì wá, wọ́n sì tẹ ara wọn ní àfonífojì Refaimu.
19 Da: ibidi da Hina Godema amane adole ba: i. “Na da Filisidini dunu doagala: ma: bela: ? Di da nama hasalasu hou ima: bela: ? Hina Gode da ema bu adole i, “Defea! Doagala: ma! Na da dia ili hasalima: ne hamomu.”
Dafidi sì béèrè lọ́dọ̀ Olúwa pé, “Kí èmi ó gòkè tọ àwọn Filistini bí? Ìwọ ó fi wọ́n lé mi lọ́wọ́ bí?” Olúwa sì wí fún Dafidi pé, “Gòkè lọ, nítorí pé dájúdájú èmi ó fi àwọn Filistini lé ọ lọ́wọ́.”
20 Amaiba: le, Da: ibidi da Ba: ile Bila: isimi sogega asili, Filisidini dunu hasali dagoi. E amane sia: i, “Hina Gode da hano heda: le fugagala: be amo defele, na ha lai ili hasali dagoi.” Amaiba: le, ilia da amo sogebi amoga dio “Ba: ile Bila: isimi” asuli. (Amo dawa: loma: ne da “Hasalasu dawa: hina”)
Dafidi sì dé Baali-Perasimu, Dafidi sì pa wọ́n níbẹ̀, ó sì wí pé, “Olúwa ti ya lu àwọn ọ̀tá mi níwájú mi, gẹ́gẹ́ bí omi ti ń ya.” Nítorí náà ni òun ṣe pe orúkọ ibẹ̀ náà ni Baali-Perasimu.
21 Filisidini dunu da hobea: iba: le, ilia da ilia loboga hamoi ogogosu ‘gode’ amo fisili, hobea: i. Da: ibidi amola ea dunu da amo gaguli asi.
Wọ́n sì fi òrìṣà wọn sílẹ̀ níbẹ̀, Dafidi àti àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ sì kó wọn.
22 Amalalu, Filisidini dunu da Lifa: ime Fagoga bu heda: le, amoga bu gesowale fi dagoi.
Àwọn Filistini sì tún gòkè wá, wọ́n sì tan ara wọn kalẹ̀ ní àfonífojì Refaimu.
23 Da: ibidi da bu Hina Godema adole ba: i. Amola Hina Gode da ema bu amane adole i, “Guiguda: amoga ili mae doagala: ma! Be na: iyadodili asili, `bolosa: me’ ifa labo aliligi amo gadenene sogebi amoga doagala: musa: momagema.
Dafidi sì béèrè lọ́dọ̀ Olúwa, òun sì wí pé, “Má ṣe gòkè lọ; ṣùgbọ́n bù wọ́n lẹ́yìn, kí o sì kọlù wọ́n níwájú àwọn igi Baka.
24 Di da ifa balu amoga mogodigisu emo goba gala: be nabasea, doagala: ma. Bai Na da dilima bisili, Filisidini dadi gagui wa: i amo hasalimusa: mogodigili hidadea asi ba: mu.”
Yóò sì ṣe, nígbà tí ìwọ bá gbọ́ ìró ẹsẹ̀ lórí àwọn igi Baka náà, nígbà náà ni ìwọ yóò sì yára, nítorí pé nígbà náà ni Olúwa yóò jáde lọ níwájú rẹ láti kọlù ogun àwọn Filistini.”
25 Da: ibidi da Hina Gode Ea hamoma: ne sia: i defele hamoi. E da Filisidini dunu amo Giba moilai bai bagadega muni sefasili, Gisa moilaiga sefasi dagoi.
Dafidi sì ṣe bẹ́ẹ̀, gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti pàṣẹ fún un; ó sì kọlu àwọn Filistini láti Geba títí dé Geseri.

< 2 Sa:miuele 5 >