< 2 Sa:miuele 3 >

1 Isala: ili dunu mogili da Da: ibidi ea fi fuligala: su. Mogili da Solo egaga fi fuligala: su. Amaiba: le, gegesu da bagade heda: i. Da: ibidima fuligala: su fi ilia gasa da heda: lalu, be ea ha lai ilia gasa da gududafa sa: i.
Ogun náà sì pẹ́ títí láàrín ìdílé Saulu àti ìdílé Dafidi: agbára Dafidi sì ń pọ̀ sí i, ṣùgbọ́n ìdílé Saulu ń rẹ̀yìn sí i.
2 Da: ibidi egefelali gafeyale gala da Hibalone moilai bai bagade amo ganodini lalelelegei. Magobo mano da A: manone (ea: me da Yeseliele uda amo ea dio amo Ahinoua: me).
Dafidi sì bí ọmọkùnrin ní Hebroni: Amnoni ni àkọ́bí rẹ̀ tí Ahinoamu ará Jesreeli bí fún un.
3 Amo baligia da Gilia: be (ea: me da Gamele uda, Na: iba: le ea didalo, ea dio amo A: biga: ile). Amo baligia da A: basalome (ea: me da Gisie hina bagade Da: lama: i ea idiwi, amo Ma: iaga).
Èkejì rẹ̀ sì ni Kileabu, tí Abigaili aya Nabali ará Karmeli bí fún un; ẹ̀kẹta sì ni Absalomu ọmọ tí Maaka ọmọbìnrin Talmai ọba Geṣuri bí fún un.
4 Amo baligia da Adounaidia (ea: me da Ha: gide). Amo baligia da Siefada: ia (ea: me da Abaida: le).
Ẹ̀kẹrin sì ni Adonijah ọmọ Haggiti; àti ẹ̀karùnún ni Ṣefatia ọmọ Abitali;
5 Ufidafa da Idilia: me (ea: me da Egela). Amo dunu mano huluane da Hibalone moilai bai bagadegamusu lalelelegei galu.
Ẹ̀kẹfà sì ni Itreamu, tí Egla aya Dafidi bí fún un. Wọ̀nyí ni a bí fún Dafidi ni Hebroni.
6 Da: ibidima fuligala: su dunu amola Solo ea sosogo fi fuligala: su dunu ele gegenanu. A: bena da Solo ea sosogo fi fuligala: su fi amo ganodini gasawane heda: lebe ba: i.
Ó sì ṣe, nígbà tí ogun wà láàrín ìdílé Saulu àti ìdílé Dafidi, Abneri sì dì alágbára ní ìdílé Saulu.
7 Eso afaega, Esiabousiede (Solo egefe) e da A: bena da Solo ea gidisedagi uda Lisiba (A: ia ea mano) amola gilisili golaiba: le, diwaneya udidi.
Saulu ti ní àlè kan, orúkọ rẹ̀ sì ń jẹ́ Rispa, ọmọbìnrin Aiah: Iṣboṣeti sì bi Abneri léèrè pé, “Èéṣe tí ìwọ fi wọlé tọ àlè baba mi lọ.”
8 Amoga, A:bena da ougi bagade ba: i. E amane sia: i, “Di da dawa: loba na da Soloma baligi fa: ma: bela: ? Di da dawa: loba na da Yuda dunu ilia hawa: hamobe hamosala: ? Na da muni amogainini dia ada Solo amola yolalali amola ea sama huluane, ili fawane fuligala: su. Amola Da: ibidi da dili mae hasalima: ne, na da hamosu. Be wali di da ogogole na da udama doaga: i sia: sa.
Abneri sì bínú gidigidi nítorí ọ̀rọ̀ wọ̀nyí ti Iṣboṣeti sọ fún un, ó sì wí pé, “Èmi jẹ́ bí orí ajá ti Juda bí? Di òní yìí ni mo ṣàánú fún ìdílé Saulu baba rẹ, àti fún àwọn arákùnrin rẹ̀, àti fún àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀, tí èmi kò sì fi ọ́ lé Dafidi lọ́wọ́, ìwọ sì kà ẹ̀ṣẹ̀ sí mí lọ́rùn nítorí obìnrin yìí lónìí?
9
Bẹ́ẹ̀ ni kí Ọlọ́run ó ṣe Abneri, àti jù bẹ́ẹ̀ lọ pẹ̀lú, bí Olúwa ti búra fún Dafidi, bí èmi kò ní ṣe bẹ́ẹ̀ fún un.
10 Hina Gode da Da: ibidima, E da Isala: ili hina bagade hou Solo amola egaga fi amoga fadegale, Da: ibidi da Isala: ili amola Yuda soge huluanedafa ouligima: ne hina bagade hamomu ilegei. Wali, na da amo hou dafawanedafa ba: ma: ne hame hamosea, Gode da na fane legemu da defea.”
Láti mú ìjọba náà kúrò ní ìdílé Saulu, àti láti gbé ìtẹ́ Dafidi kalẹ̀ lórí Israẹli, àti lórí Juda, láti Dani títí ó fi dé Beerṣeba.”
11 Esiabousiede da A: benaba: le bagadewane beda: i. E da bu adole imunu hamedei ba: i.
Òun kò sì lè dá Abneri lóhùn kan nítorí tí ó bẹ̀rù rẹ̀.
12 Amogalu, Da: ibidi da Hibalone moilai bai bagadega esalu. A: bena da ema adola ahoasu dunu ema amane sia: na masa: ne asunasi, “Nowa da ninia soge ouligima: bela: ? Nama gousa: su hamoma. Amasea, Isala: ili dunu huluane di fuligala: ma: ne, na da di fidimu.”
Abneri sì rán àwọn oníṣẹ́ sí Dafidi nítorí rẹ̀ wí pé, “Ti ta ni ilẹ̀ náà ń ṣe? Bá mi ṣe àdéhùn, èmi yóò si kó gbogbo Israẹli tọ̀ ọ́ wá.”
13 Da: ibidi da bu adole i, “Defea! Dia liligi afae fawane hamosea, na da ani gousa: su hamomu. Di da na ba: la masea, Solo idiwi Maiga: le, amo nama oule misa.”
Òun sì wí pé, “Ó dára, èmi ó bá ọ ṣe àdéhùn, ṣùgbọ́n ohun kan ni èmi ó béèrè lọ́wọ́ rẹ, èyí ni pé, ìwọ kì yóò rí ojú mi, àfi bí ìwọ bá kọ́ mú Mikali ọmọbìnrin Saulu wá, nígbà tí ìwọ bá wá, láti rí ojú mi.”
14 Amola Da: ibidi da sia: adola ahoasu dunu Esiabousiede ema amane sia: ma: ne sia: si, “Na uda Maiga: le nama bu ima. Na da Filisidini dunu 100 ilia ewa gadofo amo uda lama: ne dabe i galu.”
Dafidi sì rán àwọn ìránṣẹ́ sí Iṣboṣeti ọmọ Saulu pé, “Fi Mikali obìnrin mi lé mi lọ́wọ́, ẹni tí èmi ti fi ọgọ́rùn-ún awọ iwájú orí àwọn Filistini fẹ́.”
15 Amaiba: le, Esiabousiede da Maiga: le amo ea egoa Ba: ladiele (La: ise egefe) amo ea lai amo sugui.
Iṣboṣeti sì ránṣẹ́, ó sì gbà á lọ́wọ́ ọkùnrin tí a ń pè ní Paltieli ọmọ Laiṣi.
16 Ba: ladiele da diginiwane Maiga: lema fa: no bobogele, Bahiulimi moilaiga doaga: i. Amalalu, A:bena da ema amane sia: i, “Di diasua buhagima!” Amanobamone, e da buhagi.
Ọkọ rẹ̀ sì ń bà a lọ, ó ń rìn, ó sì ń sọkún lẹ́yìn rẹ̀ títí ó fi dé Bahurimu Abneri sì wí fún un pé, “Padà sẹ́yìn!” Òun sì padà.
17 A: bena da Isala: ili ouligisu dunu ilima asili, amane sia: i, “Dilia da eso bagohame amoga Da: ibidi dilia hina bagade hamoma: ne hananusu.
Abneri sì bá àwọn àgbàgbà Israẹli sọ̀rọ̀ pé, “Ẹ̀yin ti ń ṣe àfẹ́rí Dafidi ní ìgbà àtijọ́, láti jẹ ọba lórí yín.
18 Wali, amo hamoma! Hina Gode Ea sia: i bu dawa: ma! E amane sia: i, `Na da na hawa: hamosu dunu Da: ibidi amo ea loboga, Na fi Isala: ili dunu amo Filisidini dunu amola ilia ha lai dunu huluane ili mae hasalima: ne gaga: mu.’”
Ǹjẹ́ ẹ ṣe, nítorí tí Olúwa ti sọ fún Dafidi pé, ‘Láti ọwọ́ Dafidi ìránṣẹ́ mi lé mi ó gba Israẹli ènìyàn mi là kúrò lọ́wọ́ àwọn Filistini àti lọ́wọ́ gbogbo àwọn ọ̀tá a wọn.’”
19 Amola A: bena da amanewane Bediamini fi dunuma sia: i. Amalalu, e da Hibalone amoga asili, e da Bediamini amola Isala: ili dunu ilia hamomu sia: i, amo Da: ibidima olelei.
Abneri sì sọ̀rọ̀ létí Benjamini: Abneri sì lọ sọ létí Dafidi ní Hebroni, gbogbo èyí tí ó dára lójú Israẹli, àti lójú gbogbo ilé Benjamini.
20 A: bena amola ea dunu 20 agoane da Hibalone moilai bai bagadega Da: ibidima misi. Da: ibidi ili aowama: ne lolo nasu hamoi.
Abneri sì tọ Dafidi wá ní Hebroni, ogún ọmọkùnrin sì lọ pẹ̀lú rẹ̀ Dafidi sì ṣe àsè fún Abneri àti fún àwọn ọmọkùnrin tí ó wà pẹ̀lú rẹ̀.
21 A: bena da Da: ibidima amane adole i, “Hina noga: idafa! Na da wali asili, Isala: ili dunu huluane di fuligala: ma: ne hamomu. Amasea, ilia huluane da di hina bagade hamoma: ne sia: mu. Amola dia hanai defele, di da Isala: ili soge huluanedafa ouligima: mu.” Da: ibidi da A: bena da se hamedafa nabima: ne, gaga: su sia: ilegei.
Abneri sì wí fún Dafidi pé, “Èmi ó dìde, èmi ó sì lọ, èmi ó sì kó gbogbo Israẹli jọ sọ́dọ̀ ọba olúwa mi, wọn ó sì bá a ṣe àdéhùn, ìwọ ó sì jẹ ọba gbogbo wọn bí ọkàn rẹ ti ń fẹ́.” Dafidi sì rán Abneri lọ; òun sì lọ ní àlàáfíà.
22 Amalu fa: no, Youa: be amola Da: ibidi ea ouligisu dunu eno da ha wa: i asili, liligi lai bagadedafa gagaguli buhagi. Be ilia da A: bena Hibalone amoga esalebe hame ba: i. Bai Da: ibidi da A: benama e da se hamedafa nabima: ne, gaga: su sia: ilegele, hi diasua masa: ne asunasi.
Sì wò ó, àwọn ìránṣẹ́ Dafidi àti Joabu sì ti ibi ìlépa ẹgbẹ́ ogun kan bọ̀, wọ́n sì mú ìkógun púpọ̀ bọ̀; ṣùgbọ́n Abneri kò sí lọ́dọ̀ Dafidi ní Hebroni; nítorí tí òun ti rán an lọ, òun sì ti lọ ní àlàáfíà.
23 Youa: be amola ea dunu da doaga: le nabagaloba, A:bena da Da: ibidima misini amola Da: ibidi da e se mae nabima: ne ilegelalu hi diasua masa: ne asunasi, amo ilia nabi.
Nígbà tí Joabu àti gbogbo ogun tí ó pẹ̀lú rẹ̀ sì dé, wọ́n sì sọ fún Joabu pé Abneri, ọmọ Neri ti tọ ọba wá, òun sì ti rán an lọ, ó sì ti lọ ní àlàáfíà.
24 Amaiba: le, Youa: be da hina bagade ema asili amane sia: i, “Di da adi hamobela: ? A: bena da dima misi. Dia abuliba: le e udigili masa: ne logo doasibala: ?
Joabu sì tọ ọba wá, ó sì sọ pé, “Kí ni ìwọ ṣe yìí? Wò ó, Abneri tọ̀ ọ́ wá; èéha ti ṣe tí ìwọ sì fi rán an lọ? Òun sì ti lọ.
25 E da dima ogogomusa: misi. Amola dia hamobe amola ahoabe huluane abedemusa: misi. Di da ea hou dawa: !”
Ìwọ mọ Abneri ọmọ Neri, pé ó wá láti tàn ọ́ jẹ ni, àti láti mọ ìjáde lọ rẹ, àti wíwọlé rẹ́ àti láti mọ gbogbo èyí tí ìwọ ń ṣe.”
26 Youa: be da Da: ibidi yolesilalu, sia: adola ahoasu dunu, amo A: bena bu misa: ne sia: ma: ne asunasi. Ilia da A: bena amo Sila si hano esalebe ba: loba, e bu oule misi. Be Da: ibidi da amo hou hame dawa: i galu.
Nígbà tí Joabu sì jáde kúrò lọ́dọ̀ Dafidi, ó sì rán àwọn ìránṣẹ́ láti lépa Abneri, wọ́n sì pè é padà láti ibi kànga Sira, Dafidi kò sì mọ̀.
27 A: bena da Hibalone logo holeiga doaga: loba, Youa: be da logo bega: ema ogogole wamo sia: sia: musia: ne oule aliagale, e gobiheiga hagomo sone legei. Amola A: bena da medole legei dagoi ba: i. Bai e da Youa: be eya A: sahele fane legei.
Abneri sì padà sí Hebroni, Joabu sì bá a tẹ̀ láàrín ojú ọ̀nà láti bá a sọ̀rọ̀ ní àlàáfíà, ó sì gún un níbẹ̀ lábẹ́ inú, ó sì kú, nítorí ẹ̀jẹ̀ Asaheli arákùnrin rẹ̀.
28 Da: ibidi da amane hamoi sia: nababeba: le, e da amane sia: i, “Hina Gode da dawa: ! Na amola na baligia aligi dunu huluane, ninia da A: bena e hamedafa fane legei.
Lẹ́yìn ìgbà tí Dafidi sì gbọ́ ọ, ó sì wí pé, “Èmi àti ìjọba mi sì jẹ́ aláìlẹ́bi níwájú Olúwa títí láé, ní ti ẹ̀jẹ̀ Abneri ọmọ Neri,
29 Gode da Youa: be amola ea sosogo fi huluane ilima amo hou ea dabe se iasu ilima imunu da defea. Egaga fifi misunu amo ganodini, dunu afae da gadofo olo bagade o wadela: i uda lasu olo bagade o dunu da gasa hameba: le uda ea hawa: fawane hamomu dawa: o dunu da gegesu ganodini fane legei o dunu da ha: i bagade, agoaiwane dunu ba: mu da defea. Gode da Youa: be fi ilima amane se dabe imunu da defea.”
jẹ́ kí ó wà ní orí Joabu, àti ní orí gbogbo ìdílé baba rẹ̀; kí a má sì fẹ́ ẹni ó tí ní ààrùn ìsun, tàbí adẹ́tẹ̀, tàbí ẹni tí ń tẹ ọ̀pá, tàbí ẹni tí a ó fi idà pa, tàbí ẹni tí ó ṣe aláìní oúnjẹ kù ní ilé Joabu.”
30 Youa: be amola eaeya Abisia: i da amanewane A: bena dabe i. Bai e da ela eya A: sahele amo Gibione gegesu ganodini fane legei.
(Joabu àti Abiṣai arákùnrin rẹ̀ sì pa Abneri, nítorí pé òun ti pa Asaheli arákùnrin wọn ní Gibeoni ní ogun.)
31 Amalalu, Da: ibidi da Youa: be amola ea dunu ilia da abula gagadelale, amola abula wadela: i ebobolesi sasalili, A:benaha fofagini didigia: ma: ne sia: i. Bogoi uli dogomusa: gilisisu amoga, hina bagade Da: ibidi da bogoi doufa da: iya gisa ahoabe amoga fa: no bobogei.
Dafidi sì wí fún Joabu àti fún gbogbo ènìyàn tí ń bẹ lọ́dọ̀ rẹ̀ pé, “Ẹ fa aṣọ yín ya, kí ẹ̀yin sì mú aṣọ ọ̀fọ̀, kí ẹ̀yin sì sọkún níwájú Abneri.” Dafidi ọba tìkára rẹ̀ sì tẹ̀lé pósí rẹ̀.
32 Ilia da A: bena amo Hibalone moilai bai bagadega uli dogoi. Da: ibidi amola dunu huluane da uli dogoi bega: didigia: sa esafulu.
Wọ́n sì sin Abneri ní Hebroni, ọba sì gbé ohùn rẹ̀ sókè, ó sì sọkún ní ibojì Abneri; gbogbo àwọn ènìyàn náà sì sọkún.
33 Da: ibidi da A: benaha asigili fofagi gesami amane hea: i, “A: bena da abuliba: le gagaoui dunuga bogosu defele bagobela: ?
Ọba sì sọkún lórí Abneri, ó sì wí pé, “Ǹjẹ́ Abneri ó yẹ kí ó kú bí aṣiwèrè?
34 Ea lobo da hame la: gi ba: i. Ea emo da hame la: gi ba: i. E da dunu amo wadela: i hamosu dunuga medole legei, amo defele bogoi.” Amalalu, dunu huluane eha da bu didiga: i.
A kò sá à dè ọ́ lọ́wọ́, bẹ́ẹ̀ ni a kò kan ẹsẹ̀ rẹ ní àbà. Gẹ́gẹ́ bí ènìyàn tí ń ṣubú níwájú àwọn ìkà ènìyàn, bẹ́ẹ̀ ni ìwọ ṣubú.” Gbogbo àwọn ènìyàn náà sì tún sọkún lórí rẹ̀.
35 Amo esoha, dunu da gebewane Da: ibidi e ha: i moma: ne sia: i. Be e da dafawane amane ilegele sia: i, “Na da wali eso amoga ha: i nasea, Gode da na fane legemu da defea.”
Nígbà tí gbogbo ènìyàn sì wá láti gba Dafidi ní ìyànjú kí ó jẹun, nígbà tí ọjọ́ sì ń bẹ, Dafidi sì búra wí pé, “Bẹ́ẹ̀ ni kí Ọlọ́run ó ṣe sí mi àti jù bẹ́ẹ̀ lọ, bí èmi yóò bá tọ́ oúnjẹ wò, tàbí nǹkan mìíràn títí oòrùn yóò fi wọ̀!”
36 Ilia da amo hou ba: lalu, hahawane ba: i. Dafawane! Ilia da hina bagade Da: ibidi ea hamobe huluane hahawane ba: i.
Gbogbo àwọn ènìyàn sì kíyèsi i, ó sì dára lójú wọn, gbogbo èyí tí ọba ṣe sì dára lójú gbogbo àwọn ènìyàn náà.
37 Da: ibidi ea fi dunu huluane, amola Isala: ili fi dunu huluane da hina bagade da A: bena fane legei amo hamedafa fidi, amo noga: le dawa: i galu.
Gbogbo àwọn ènìyàn náà àti gbogbo Israẹli sì mọ̀ lọ́jọ́ náà pé, kì í ṣe ìfẹ́ ọba láti pa Abneri ọmọ Neri.
38 Hina bagade da ea eagene ouligisu dunuma amane sia: i, “Dilia! Noga: le dawa: ma! Wali eso, Isala: ili soge ouligisu dunu bagade da bogoi dagoi.
Ọba sì wí fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ pé, “Ẹ̀yin kò mọ̀ pé olórí àti ẹni ńlá kan ni ó ṣubú lónìí ní Israẹli.
39 Gode da na hina bagade hamoma: ne ilegei dagoi. Be wali eso na da gasa hamedene gogaya: i ba: sa. Selouaia egefelali da baligili bidi hamobeba: le, na higasa. Hina Gode da ilia wadela: i hamoi defele, se dabe ilima imunu da defea.”
Èmi sì ṣe aláìlágbára lónìí, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé a fi èmi jẹ ọba; àwọn ọkùnrin wọ̀nyí ọmọ Seruiah sì le jù mí lọ: Olúwa ni yóò san án fún ẹni tí ó ṣe ibi gẹ́gẹ́ bí ìwà búburú rẹ̀!”

< 2 Sa:miuele 3 >