< 2 Sa:miuele 2 >

1 Amalu fa: no Da: ibidi da Hina Godema amane adole ba: i, “Na da asili, Yuda moilai afae ouligimu da defeala: ?” Hina Gode da bu adole i, “Ma! Ouligima!” Da: ibidi da bu adole ba: i, “Habola: ?” Hina Gode da bu adole i, “Hibalone!”
Lẹ́yìn àkókò yìí, Dafidi wádìí lọ́wọ́ Olúwa. Ó sì béèrè pé, “Ṣé èmi lè gòkè lọ sí ọ̀kan lára àwọn ìlú Juda?” Olúwa sì wí pé, “Gòkè lọ.” Dafidi sì béèrè pé, “Ní ibo ni kí èmi kí ó lọ?” Olúwa sì dá a lóhùn pé, “Sí Hebroni.”
2 Amaiba: le Da: ibidi da ea uda aduna Hibalone moilai bai bagadega oule asi. Ea iduala da Ahinoua: me (e da Yeseliele moilai bai bagadega fi uda) amola A: biga: ile (Na: iba: le ea didalo Gamele moilaiga misi.)
Nígbà náà ni Dafidi gòkè lọ síbẹ̀ pẹ̀lú ìyàwó rẹ̀ méjì Ahinoamu ará Jesreeli, àti Abigaili obìnrin opó Nabali ti Karmeli.
3 Amola e da ea dunu fi amola ilia sosogo fi huluane oule asili, amola ilia da Hibalone moilai bai bagade amo ganodini fifilai dagoi.
Dafidi sì mú àwọn ọkùnrin tí ó wà pẹ̀lú rẹ̀, olúkúlùkù pẹ̀lú ìdílé rẹ̀, wọ́n sì ń gbé ní Hebroni àti ìlú rẹ̀ mìíràn.
4
Nígbà náà àwọn ọkùnrin ará Juda wá sí Hebroni, níbẹ̀ ni wọ́n ti fi àmì òróró yan Dafidi gẹ́gẹ́ bí ọba lórí ilé Juda. Nígbà tí wọ́n sọ fún Dafidi pé, àwọn ọkùnrin ti Jabesi Gileadi ni ó sin òkú Saulu,
5 Amalu, Yuda dunu ilia Hibalone moilai bai bagadega misini doaga: le, Da: ibidi da Yuda dunu ilia hina bagade galebe ilia dawa: digima: ne susuligi unasili, e ilegei dagoi. Ya: ibese moilai bai bagade (Gilia: de soge amo ganodini gala) amo fifi lai dunu da Solo ea da: i hodo uligai dagoi. Da: ibidi da amo sia: be nababeba: le, sia: adola ahoasu dunu ilia amane sia: adola masa: ne asunasi dagoi, “Dilia da dilia hina bogoi ema nodone uligai dagoiba: le, Hina Gode da dilima hahawane dogolegele hamomu da defea.
Dafidi rán oníṣẹ́ sí àwọn ọkùnrin Jabesi Gileadi láti sọ fún wọn pé, “Olúwa bùkún un yín fún fífi inú rere yín hàn sí Saulu ọ̀gá yín nípa sí sin ín.
6 Amalu waha amola hobea Hina Gode da dilima mae fisili hahawane dogolegele hamomu da defea. Dilia da na noga: le fidibiba: le, na amola da dili noga: le fidimu.
Kí Olúwa kí ó fi inú rere àti òtítọ́ fún un yín, èmi náà yóò sì san oore yìí fún un yín, nítorí tí ẹ̀yin ti ṣe èyí.
7 Gasa fima! Amola hahawane galoma! Dilia hina bagade Solo da bogoi dagoi, amola Yuda dunu ilia da na amo hina bagade hawa: hamoma: ne ilegei dagoi.”
Ǹjẹ́ nísinsin yìí, ẹ mú ara yín le, kí ẹ sì ní ìgboyà, nítorí Saulu ọba yín ti kú, ilé Juda sì ti fi àmì òróró yàn mí ní ọba lórí wọn.”
8 Solo ea dadi gagui ilia bisilua A: bena (Ne egefe) amola Esiabousiede (Solo egefe), ela da gegesua hobeale, Yoda: ne hano degele, Ma: ihana: ime sogega asi.
Lákòókò yìí, Abneri ọmọ Neri olórí ogun Saulu ti mú Iṣboṣeti ọmọ Saulu, ó sì mú un kọjá sí Mahanaimu.
9 Amogai, A:bena da Esiabousiede ea hina bagade hawa: hamoma: ne ilegei, amalu Gilia: de soge huluane amola A: sie, Yeseliele, Ifala: ime, Bediamini, amola Isala: ili huluane ouligima: ne sia: i.
Ó sì fi jẹ ọba lórí Gileadi Aṣuri àti Jesreeli àti lórí Efraimu àti lórí Benjamini àti lórí gbogbo Israẹli.
10 Esiabousiede da lalelegele, ode 40 gidigili esalu, Isala: ili ouligisu hawa: hamosu lai. Amola e da Isala: ili soge ode aduna ouligi. Be Yuda fi da Da: ibidi ema fa: no bobogesu.
Iṣboṣeti ọmọ Saulu sì jẹ́ ọmọ ogójì ọdún nígbà tí ó jẹ ọba lórí Israẹli, ó sì jẹ ọba fún ọdún méjì. Ilé Juda sì ń tọ Dafidi lẹ́yìn.
11 Amola e da Hibalone moilai bai bagadega esala, Yuda ouligilalu, ode fesuale amola oubi gafeale gidigi.
Gbogbo àkókò tí Dafidi fi jẹ ọba ní Hebroni lórí ilé Juda sì jẹ́ ọdún méje àti oṣù mẹ́fà.
12 A: bena amola Esiabousiede ea baligia aligili eagene ouligisu dunu, ilia da amo Ma: ihana: ime soge amo ganodini asili, moilai bai bagade Gibione amoga asili, hano ulasu dogoi bega: doaga: i.
Abneri ọmọ Neri pẹ̀lú àwọn ọkùnrin ti Iṣboṣeti ọmọkùnrin Saulu kúrò ní Mahanaimu, wọ́n sì lọ sí Gibeoni.
13 Amoga ilia da Youa: be (ea ame da Seluaia) amola Da: ibidi ea eagene ouligisu dunu oda hano na: iyadodili fi dialebe ba: i.
Joabu ọmọ Seruiah pẹ̀lú àwọn ọkùnrin Dafidi jáde lọ láti lọ bá wọn ní adágún Gibeoni. Ẹgbẹ́ kan sì jókòó ní apá kan adágún, àti ẹgbẹ́ kejì ní apá kejì adágún.
14 A: bena da Youa: bema amane sia: i, “Dia fi goi mogili da ninia fi goi mogili ilima hedele gegemala: di.” Youa: be da bu adole i, “Defea!”
Nígbà náà, Abneri sọ fún Joabu pé, “Jẹ́ kí díẹ̀ nínú àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin yìí ó dìde láti bá ara wọn jà níwájú wa.” Joabu sì dáhùn pé, “Ó dára, jẹ́ kí wọ́n ṣe é.”
15 Amaiba: le, Esiabousiede ea Bediamini fi dunu fagoyale gala da Da: ibidi ea fi dunu fagoyale gala ilima gegei.
Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n dìde sókè, a sì kà wọ́n sí ọkùnrin méjìlá fún Benjamini àti Iṣboṣeti ọmọ Saulu àti méjìlá fún Dafidi.
16 Dunu afae afae da defele ilia ha lai dunu ilia dialumagia ili defele gaguli, ilia gobiheiga galu afoa sone, dunu huluane24agoane galu dafane bogoi ba: i. Amaiba: le, Gibione moilai bai bagade amo ganodini, amo soge dawa: loma: ne ilia da “Gegesu Gobihei Sogebi” sia: sa.
Nígbà náà olúkúlùkù ọkùnrin gbá ẹnìkejì rẹ̀ mú ní orí, ó sì fi idà gún ẹnìkejì rẹ̀ lẹ́gbẹ̀ẹ́, wọ́n sì ṣubú lulẹ̀ papọ̀. Bẹ́ẹ̀ ni ibẹ̀ ni Gibeoni ti à ń pè ni Helikatihu Hasurimu.
17 Amalalu, bagadedafa gegesu da mui. Amola Da: ibidi ea dunu da A: bena amola Isala: ili dunu hasali dagoi.
Ogun náà ní ọjọ́ náà gbóná. Àwọn ọmọkùnrin Dafidi sì ṣẹ́gun Abneri pẹ̀lú àwọn ọkùnrin Israẹli.
18 Selouaia ea mano udiana ilia da amogawi esalebe ba: i. Ilia dio da Youa: be, Abisia: i, amola A: sahele. A: sahele da sigua ohe ‘dia’ amo defele hehenasu dawa: i galu.
Àwọn ọmọkùnrin Seruiah mẹ́tẹ̀ẹ̀ta ni ó wà níbẹ̀: Joabu, Abiṣai àti Asaheli. Nísinsin yìí ẹsẹ̀ Asaheli sì fẹ́rẹ̀ bí ẹsẹ̀ èsúró tí ó wà ní pápá.
19 E da A: benama molo dounananu, doagala: musa: hehenaia bobogei.
Asaheli sì ń lépa Abneri, bí òun tí ń lọ kò sì yípadà sí ọ̀tún tàbí sí òsì láti máa tọ́ Abneri lẹ́yìn.
20 A: bena da beba: le amane sia: i, “A: sahele! Amo da dila: ?” “Ma!” e bu adole i.
Abneri bojú wo ẹ̀yìn rẹ̀, Ó sì béèrè pé, “Ṣé ìwọ Asaheli ni?” Ó dáhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ ni.”
21 A: bena da amane sia: i, “Na bobogebe go yolesima! Di dadi gagui ayeligi afae amoga se bobogele, ea gagui liligi lama.” Be A: sahele da mae yolesili ema fa: no bobogelalu.
Nígbà náà, Abneri sọ fún un pé, “Yípadà sí ọ̀tún tàbí òsì; mú ọ̀kan lára àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin kí o sì bọ́ ìhámọ́ra rẹ.” Ṣùgbọ́n Asaheli kọ̀ láti dẹ́kun lílépa rẹ̀.
22 A: bena da bu enowane A: sahelema amane sia: i, “Na bobogebe go yolesima! Abuliba: le di da na di fuga: ma: ne hamosala: ? Na da di fane legesea, dia ola Youa: be ea odagi na da habodane bu ba: ma: bela: ?”
Abneri tún kìlọ̀ fún Asaheli, “Dẹ́kun lílépa mi! Èéṣe tí èmi yóò fi lù ọ́ bolẹ̀? Báwo ni èmi yóò ti wo arákùnrin rẹ Joabu lójú?”
23 Be A: sahele da hame yolesi. Amaiba: le, A:bena da ea goge agei baligidu olele guma: noba, goge agei da A: sahele hagomoa sone badofale baligia, gadili asi ba: i. A: sahele da osoba gala: lasa: ili, bogoi dialebe ba: i. Amola dunu huluane amogai misini, ilia da e dialebe ba: loba, ili amogawi dufugili aliligi.
Ṣùgbọ́n ó sí kọ̀ láti padà, Abneri sì fi òdì ọ̀kọ̀ gún un lábẹ́ inú, ọ̀kọ̀ náà sì jáde ní ẹ̀yìn rẹ̀: òun sì ṣubú lulẹ̀ níbẹ̀, ó sì kú ní ibi kan náà; ó sí ṣe gbogbo ènìyàn tí ó dé ibi tí Asaheli gbé ṣubú si, tí ó sì kú, sì dúró jẹ́.
24 Be Youa: be amola Abisia: i da muni A: bena ema bobogei. Asili, eso daba guma: di ilia da A: ima agolo (amo da Gaia moilaiga gusudili diala. Gaia moilai da logo amo da Gibione hafoga: i sogega ahoasu bega: diala).
Joabu àti Abiṣai sì lépa Abneri: oòrùn sì wọ̀, wọ́n sì dé òkè ti Amima tí o wà níwájú Giah lọ́nà ijù Gibeoni.
25 Bediamini fi dunu da bu A: benama gale gilisi. Ilia da agolo da: iya lelu.
Àwọn ọmọ Benjamini sì kó ara wọn jọ wọ́n tẹ̀lé Abneri, wọ́n sì wá di ẹgbẹ́ kan, wọ́n sì dúró lórí òkè kan.
26 A: bena da Youa: bema amane wele sia: i, “Ninia abuliba: le mae fisili, eso huluane gegenanoma: bela: ? Amane hamosea, ninia da da: i diosu fawane ba: mu. Ninia da dilia fi dunu! Di da habogala dia fi dunu ilia nini sefasisu yolesima: ne sia: ma: bela: ?”
Abneri sì pe Joabu, ó sì bi í léèrè pé, “Idà yóò máa parun títí láéláé bí? Ǹjẹ́ ìwọ kò ì tí ì mọ̀ pé yóò korò níkẹyìn? Ǹjẹ́ yóò ha ti pẹ́ tó kí ìwọ tó sọ fún àwọn ènìyàn náà, kí wọ́n dẹ́kun láti máa lépa arákùnrin wọn.”
27 Youa: be da bu adole i, “Na da Esalebe Gode Ea Dioba: le amane ilegesa. Di da amane hame sia: i ganiaba, na da dilima gebewane bobogelalawane, aya hahabe fawane yolesila: loba.”
Joabu sì wí pé, “Bí Ọlọ́run ti ń bẹ, bí kò ṣe bí ìwọ ti wí, nítòótọ́ ní òwúrọ̀ ni àwọn ènìyàn náà ìbá padà lẹ́yìn arákùnrin wọn.”
28 Amalalu, Youa: be da ea dunu Isala: ili dunuma bobogesa yolesimu dawa: digima: ne, dalabede fulaboi. Amalalu, gegesu da fisi dagoi ba: i.
Joabu sì fọ́n ìpè, gbogbo ènìyàn sì dúró jẹ́ẹ́, wọn kò sì lépa Israẹli mọ́, bẹ́ẹ̀ ni wọn kò sì tún jà mọ́.
29 Amo gasia amogainini aya hahabe, A:bena amola ea dunu ilia da Yodane Fagoa gududili ahoanu, Yodane hano degele, esomogoadafa Ma: ihana: ime sogega doaga: i.
Abneri àti àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ sì fi gbogbo òru náà rìn ní pẹ̀tẹ́lẹ̀, wọ́n sì kọjá Jordani, wọ́n sì rìn ní gbogbo Bitironi, wọ́n sì wá sí Mahanaimu.
30 Youa: be da doagala: musa: bobogelalu fisiagaloba, e da ea dunu huluane gegedole, A:sahele amola dunu 19 eno esalebe hame ba: i.
Joabu sì dẹ́kun àti máa tọ Abneri lẹ́yìn: ó sì kó gbogbo àwọn ènìyàn náà jọ, ènìyàn mọ́kàndínlógún ni ó kú pẹ̀lú Asaheli nínú àwọn ìránṣẹ́ Dafidi.
31 Be Bediamini fi dunu (A: bena ea dunu) amo 360 agoane da Da: ibidi ea dunu amolalia fane legei dagoi ba: i.
Ṣùgbọ́n àwọn ìránṣẹ́ Dafidi sì pa nínú àwọn ènìyàn Benjamini: nínú àwọn ọmọkùnrin Abneri; òjìdínnírinwó ènìyàn.
32 Youa: be amola ea dunu da A: sahele ea bogoi da: i hodo lale, ea sosogo fi uli gelaba Bedeleheme moilaiga amo ganodini sali. Amalalu, ilia da amo gasi ganodini mogodigili, lafiadala, hadigibi galu Hibalone moilai bai bagadega doaga: i.
Wọ́n si gbé Asaheli wọ́n sì sin ín sínú ibojì baba rẹ̀ tí ó wà ní Bẹtilẹhẹmu. Joabu àti àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ fi gbogbo òru náà rìn, ilẹ̀ sì mọ́ wọn sí Hebroni.

< 2 Sa:miuele 2 >