< 2 Hina 9 >

1 Amogaluwane, balofede dunu Ilaisia da ayeligi balofede dunu afae wele guda: le, ema amane sia: i, “Di da momagele, La: imode moilai bai bagade, Gilia: de soge ganodini, amoga masa. Amo osoboga hamoi ofodo olife susuligi di nabai, amo gaguli masa.
Wòlíì Eliṣa fi àṣẹ pe ọkùnrin kan láti ẹgbẹ́ àwọn wòlíì, ó sì wí fún un pé, “Ki agbádá rẹ sínú ọ̀já àmùrè rẹ, gba ṣágo kékeré òróró yìí pẹ̀lú rẹ, kí o sì lọ sí Ramoti Gileadi.
2 Di da amoga doaga: sea, Yihiu (Yihosiafa: de egefe amola Nimisa: i ea aowa) hogoma. Dunu ili asi amo esafulia, efa oule, enoga hame heda: su sesei amoga oule heda: ma.
Nígbà tí o bá dé bẹ̀, wá Jehu ọmọ Jehoṣafati, ọmọ Nimṣi kiri. Lọ sí ọ̀dọ̀ ọ rẹ̀, mú un kúrò lọ́dọ̀ àwọn ẹlẹgbẹ́ ẹ rẹ̀, kí o sì mú un wọ inú yàrá lọ́hùn ún lọ.
3 Amogai, di da olife susuligi, Yihiu ea dialuma da: iya sogagala: le, amane sia: ma, ‘Hina Gode da amane sia: sa, Na da di Na fi Isala: ili ilia hina bagade ilegesa.’ Amasea, amo sogebi hedolowane fisili masa.”
Nígbà náà, mú ṣágo kékeré yìí, kí o sì da òróró náà lé e lórí, kí o sì wí pé, ‘Èyí ni ohun tí Olúwa wí, “Èmi fi àmì òróró yàn ọ́ ní ọba lórí Israẹli.”’ Nígbà náà, ṣí ìlẹ̀kùn, kí o sì sáré, má ṣe jáfara!”
4 Amaiba: le, ayeligi balofede dunu da La: imode moilai bai bagadega asi.
Bẹ́ẹ̀ ni ọ̀dọ́mọkùnrin náà, wòlíì náà lọ sí Ramoti Gileadi.
5 Amogai, e da dadi gagui wa: i ouligisu dunu, ilia da sia: sia: sa: imusa: gilisibi ba: i. E amane sia: i, “Hina! Na da dima sia: sia: mu gala!” Yihiu da amane adole ba: i, “Di da niniga afae nowama sia: mu gala?” E bu adole i, “Hina! Dimafa sia: mu gala.”
Nígbà tí ó dé, ó rí àwọn olórí ẹgbẹ́ ọmọ-ogun tí wọ́n jókòó papọ̀. “Èmi ní iṣẹ́ fún ọ, olórí,” Ó wí. “Sí ta ni nínú wa?” Jehu béèrè. Òun sì wí pé, “Sí ọ, balógun,” Ó dáhùn.
6 Amalalu, ele galu diasu ganodini golili sa: ili, amola ayeligi balofede dunu da Yihiu ea dialuma da: iya olife susuligi sogagala: le, ema amane sia: i, “Isala: ili fi ilia Hina Gode da amane sia: sa, ‘Na da di Na fi Isala: ili ilia hina bagade ilegesa.
Jehu dìde sókè, ó sì wọ inú ilé lọ. Nígbà náà, wòlíì náà da òróró náà sórí Jehu; ó sì wí pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli wí: ‘Èmi fi àmì òróró yàn ọ́ ní ọba lórí àwọn ènìyàn Olúwa Israẹli.
7 Di da dia hina (Isala: ili hina bagade, A:iha: be ea egefe) amo medole legema. Bai Na da Yesebele, e da Na balofede dunu amola Na eno hawa: hamosu dunu medole lelegeiba: le, Na da ema se dabe imunu.
Kí ìwọ kí ó pa ilé Ahabu ọ̀gá à rẹ̀ run, Èmi yóò sì gbẹ̀san ẹ̀jẹ̀ gbogbo àwọn ìránṣẹ́ mi wòlíì àti gbogbo ẹ̀jẹ̀ àwọn ìránṣẹ́ Olúwa tí a ta sílẹ̀ látọwọ́ ọ Jesebeli.
8 A: iha: be ea sosogo fi amola egaga fi huluane da bogosu ba: mu. Na da ea sosogo fi dunumusu huluanedafa, goi amola da: i hamoi amo huluane ebelelesimu.
Gbogbo ilé Ahabu yóò ṣègbé. Èmi yóò gé e kúrò láti orí Ahabu gbogbo ọ̀dọ́mọkùnrin tí ó gbẹ̀yìn ni Israẹli, ẹrú tàbí òmìnira.
9 Na da Isala: ili fi hina bagade Yelouboua: me amola Isala: ili hina bagade Ba: iasia ela sosogo fima hamoi defele, A:iha: be ea sosogo fima hamomu.
Èmi yóò ṣe ilé Ahabu gẹ́gẹ́ bí ilé Jeroboamu ọmọ Nebati àti ilé Baaṣa ọmọ Ahijah.
10 Yesebele ea da: i hodo da mae dogone sanawene, Yeseliele sogega wa: mega na dagoi ba: mu,’” Amo sia: nanu, ayeligi balofede dunu da sesei yolesili, hobea: i.
Fún Jesebeli, ajá ni yóò jẹ ẹ́ ní oko Jesreeli, kò sì sí ẹni tí yóò sin òkú rẹ̀.’” Nígbà náà ó ṣí ìlẹ̀kùn, ó sì sálọ.
11 Yihiu da ea na: iyado dadi gagui ouligisu dunu ilima bu asili, ilia da ema amane adole ba: i, “Liligi huluane da defeala: ? Amo gagaoui dunu da dima adi hamosala: ?” Yihiu da bu adole i, “Ea hamomusa: hanai amo dilia dawa:”
Nígbà tí Jehu jáde lọ bá àwọn ọgbà ìjòyè e rẹ̀, ọ̀kan nínú wọn sì bi í pé, “Ṣé gbogbo nǹkan dára?” Kí ni ó dé tí aṣiwèrè fi tọ̀ ọ́ wá, “Ìwọ mọ ọkùnrin náà àti irú nǹkan tí ó ń sọ,” Jehu fèsì.
12 Ilia amane sia: i, “Hae! Ninia hame dawa: Ea sia: i amo ninima adole ima!” Yihiu da amane sia: i, “E da nama amane sia: i, ‘Hina Gode da amane ilegesa, Na da di Isala: ili ilia hina bagade hamoma: ne susuligi sogagala: le ilegesa!’”
“Ìyẹn kì í ṣe òótọ́!” Wọ́n wí. “Sọ fún wa.” Jehu wí, “Èyí ni ohun tí ó sọ fún mi: ‘Èyí ni ohun tí Olúwa wí, “Èmi fi àmì òróró yàn ọ́ ní ọba lórí Israẹli.”’”
13 Hedolodafa, Yihiu ea na: iyado dadi gagui ouligisu dunu, ilia da ilia abula fa: gu da: iya gado, Yihiu amo da: iya aligima: ne, fa: sisili, dalabede fulabole, amola ha: giwane amane wele sisia: i, “Yihiu da hina bagade hamoi dagoi.”
Wọ́n ṣe gírí, wọ́n sì mú agbádá a wọn, wọ́n sì tàn wọ́n sí abẹ́ rẹ̀ ní orí àtẹ̀gùn. Nígbà náà, wọ́n fọn ìpè, wọ́n sì kígbe, “Jehu jẹ ọba!”
14 Amalalu, Yihiu da Isala: ili hina bagade Youla: me amo fane legemusa: , hohonosu wamo sia: hamoi. Hina bagade Youla: me da La: imode sogega, Silia hina bagade Ha: sa: ilelema gegenana gala: i. Amo bahoma: ne, e da Yeseliele moilai bai bagadega asili, esalu. Amaiba: le, Yihiu da ea na: iyado dadi gagui ouligisu dunuma amane sia: i, “Dilia da namagai galea, dunu mogili da La: imode fisili, Yeseliele fima sisane sia: sa: besa: le, logo huluane noga: le sosodo aligima.”
Bẹ́ẹ̀ ni Jehu ọmọ Jehoṣafati, ọmọ Nimṣi, dìtẹ̀ sí Joramu. (Nísinsin yìí Joramu àti gbogbo Israẹli ti ń dáàbò bo Ramoti Gileadi nítorí Hasaeli ọba Aramu.
ṣùgbọ́n ọba Joramu ti padà sí Jesreeli láti lọ sàn nínú ọgbẹ́ tí àwọn ará Aramu ti dá sí i lára nínú ogun pẹ̀lú ọba Hasaeli ti Aramu.) Jehu wí pé, “Tí èyí bá jẹ́ ọ̀nà tí ò ń rò, má ṣe jẹ́ kí ẹnìkankan kí ó yọ jáde nínú ìlú ńlá láti lọ sọ ìròyìn náà ní Jesreeli.”
16 Amalalu, Yihiu da ea ‘sa: liode’ da: iya fila heda: le, Yeseliele moilai bai bagadega doaga: musa: asi. Youla: me e gala: i da hame bahoi, amola Yuda hina bagade A: ihasaia da ema ba: la misini, amogawi esalebe ba: i.
Nígbà náà Jehu wọ inú kẹ̀kẹ́ rẹ̀, ó sì gùn ún lọ sí Jesreeli, nítorí Joramu ń sinmi níbẹ̀ àti Ahasiah ọba Juda sì sọ̀kalẹ̀ láti wá wò Joramu.
17 Sosodo ouligisu dunu afae, Yeseliele gagagula heda: i diasu gadodili esala, da Yihiu amola ea dunu manebe ba: i. E da amane wele sia: i, “Na ba: loba dunu da hosi da: iya fili heda: fia: lebe ba: sa.” Youla: me da bu adole i, “Amo ilia da ha lai dunuyale o ninimagai dunuyale, amo ba: ma: ne, hosiga fila heda: i dunu asunasima.”
Nígbà tí olùṣọ́ kan tí ó dúró ní ilé ìṣọ́ ní Jesreeli, rí ọ̀wọ́ ogun Jehu tí wọ́n ń súnmọ́ tòsí, ó pè jáde, “Mo rí àwọn ọ̀wọ́ ogun tí ó ń bọ̀.” “Mú ọkùnrin ẹlẹ́ṣin kan,” Joramu pa á láṣẹ. “Rán an lọ sí ọ̀dọ̀ wọn kí o sì béèrè pé, ‘Ṣé ẹ̀yin wá pẹ̀lú àlàáfíà?’”
18 Sia: adole ahoasu dunu da hosi da: iya fila heda: le asili, Yihuma doaga: le, ema amane sia: i, “Hina bagade da di da ninimagai o ninima ha lai dunuyale dawa: musa: , amo adole ba: ma: ne na asunasi.” Yihiu da bu adole i, “Amo da dia liligi hame. Na baligia aligili, nama fa: no bobogema!” Sosodo ouligisu dunu gagagula heda: i diasu gadodili esalu, da adola ahoasu dunu da Yihiu ea gilisisu doaga: le, bu hame maha, amane sia: legei.
Ọkùnrin ẹlẹ́ṣin náà, lọ láti lọ bá Jehu ó sì wí pé, “Èyí ni ohun tí ọba wí: ‘Ṣé ìwọ wá pẹ̀lú àlàáfíà?’” “Kí ni ìwọ ní ṣe pẹ̀lú àlàáfíà?” Jehu sì dáhùn. “Bọ́ sí ẹ̀yìn mi.” Olùṣọ́ náà sì wí fún un pé, “Ìránṣẹ́ náà ti dé ọ̀dọ̀ wọn, ṣùgbọ́n kò tún padà wá mọ́.”
19 Youla: me da sia: adola ahoasu dunu eno asunasili, e da Yihuma musa: adole ba: i defele, adole ba: i. Amola Yihiu da bu amane sia: i, “Amo da dia liligi hame. Na baligia aligili, nama fa: no bobogema!”
Bẹ́ẹ̀ ni, ọba rán ọkùnrin ẹlẹ́ṣin kejì. Nígbà náà ó wá sí ọ̀dọ̀ wọn, ó wí pé, “Èyí ni ohun tí ọba sọ: “Ṣé ìwọ wá pẹ̀lú àlàáfíà?” Jehu dáhùn, “Dúró sí ẹ̀yìn mi.”
20 Sosodo ouligisu dunu da enowane sia: adola ahoasu da Yihiu ea gilisisu doaga: le, hame buhagi, amo sia: legei. Amola e eno amane sia: i, “Gilisisu bisili ahoabe dunu da ea ‘sa: liode’ fila heda: le amo dadousa dunu agoane ha: gi ahoa. E da Yihiu ea hou defele hamosa.”
Olùṣọ́ náà sì fi sùn. “Ó ti dé ọ̀dọ̀ wọn, ṣùgbọ́n kò tún padà wá mọ́ pẹ̀lú. Wíwá rẹ̀ sì dàbí ti Jehu ọmọ Nimṣi, ó ń wa kẹ̀kẹ́ bí ti aṣiwèrè.”
21 Isala: ili hina bagade Youla: me da amane hamoma: ne sia: i, “Na ‘sa: liode’ momagema!” Ilia da amane hamoi. Youla: me amola Yuda hina bagade A: ihasaia, ela da elela: ‘sa: liode’ da: iya fila heda: le, Yihuma doaga: musa: , gadili asi. Ilia da sogebi amo musa: Na: ibode gagui, amoga Yihuma doaga: i.
“Fi ìwọ̀ kọ́ kẹ̀kẹ́ ogun mi.” Joramu pa á láṣẹ. Àti nígbà tí a fi kọ́, Joramu ọba Israẹli àti Ahasiah ọba Juda, gun kẹ̀kẹ́ lọ, olúkúlùkù nínú kẹ̀kẹ́ ogun tirẹ̀, láti lọ bá Jehu. Wọ́n bá a pàdé ní ibi oko tí ó ti jẹ́ ti Naboti ará Jesreeli.
22 Youla: me da ema amane adole ba: i, “Di da olofoiwane manabela: ?” Yihiu da bu adole i, “Olofosu hamomu da hamedei. Bai wamuni dawa: su hou amola ogogole loboga hamoi ‘gode’ma nodone sia: ne gadosu hou amo dia ame Yesebele ea bai muni hamoi, amo huluane dialebe ba: sa.”
Nígbà tí Joramu rí Jehu, ó béèrè pé, “Ṣé ìwọ wá pẹ̀lú àlàáfíà, Jehu?” “Báwo ni àlàáfíà yóò ṣe wà,” Jehu dáhùn, “Ní ìwọ̀n ìgbà tí gbogbo ìbọ̀rìṣà àti iṣẹ́ àjẹ́ ti màmá rẹ Jesebeli di púpọ̀?”
23 Youla: me da ha: giwane wele sia: i, “A: ihasaia! Hohonosu hou da doaga: i dagoi!” E da ea ‘sa: liode’ delegima: ne hosi efega hiougia guda: i.
Joramu yí ọwọ́ rẹ̀ padà, ó sì sálọ, ó sì ń pe Ahasiah, “Ọ̀tẹ̀ dé, Ahasiah!”
24 Yihiu da ea gasa defele oulali dili, souga gala: i. Sou da asili, Youla: me ea baligia ludili, ea dogo badofai. Youla: me da ea ‘sa: liode’ ganodini, gala: la sa: ili, bogoi dagoi.
Nígbà náà, Jehu fa ọrun rẹ̀, ó sì yin Joramu láàrín èjìká méjèèjì. Ọfà náà sì wọ inú ọkàn rẹ̀, ó sì ṣubú lulẹ̀ láti orí kẹ̀kẹ́ rẹ̀.
25 Yihiu da ea fidisu dunu Bidigama amane sia: i, “Ea da: i hodo lale, Na: ibode ea musa: gagui sogega galagama! Di bu dawa: ma! Musa: ania da hosi da: iya fila heda: le, hina bagade Youla: me ea ada A: iha: be ea baligia ahoanoba, Hina Gode da A: iha: bema amane sia: i,
Jehu sọ fún Bidikari, balógun kẹ̀kẹ́ ẹ rẹ̀ pé, “Gbé e sókè kí ó sì jù ú sí orí oko tí ó jẹ́ ti Naboti ará Jesreeli. Rántí bí èmi àti ìwọ ti ń gun kẹ̀kẹ́ papọ̀ lẹ́yìn Ahabu baba à rẹ nígbà tí Olúwa sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa rẹ̀,
26 ‘Na da aya Na: ibode amola egefelali medole legei ba: i. Amola Na da amane dafawane hamoma: ne ilegele sia: sa, Na da ilia medole legei sogebi amoga, dima se dabe imunu.’” Yihiu da ea fidisu dunuma eno amane sia: i, “Amaiba: le, Youla: me ea da: i hodo lale, Hina Gode Ea ilegei sia: dafawane hamoma: ne, Na: ibode ea musa: gagui sogebi amoga galagama.”
‘Ní àná, mo rí ẹ̀jẹ̀ Naboti pẹ̀lú ẹ̀jẹ̀ ọmọ rẹ̀ ọkùnrin, ni Olúwa wí.’ Ǹjẹ́ nítorí náà, ẹ gbé e sókè, kí o sì jù ú sí orí ilẹ̀ oko náà ní ìbámu pẹ̀lú ọ̀rọ̀ Olúwa.”
27 Yuda hina bagade A: ihasaia da amo hou ba: beba: le, e da ea ‘sa: liode’ ganodini, Bede Ha: iga: nega doaga: musa: hobea: i. Yihiu da e baligia se bobogei. Yihiu da ea dunuma amane sia: i, “E amolawane medole legema!” A: ihasaia da ea ‘sa: liode’ ganodini, logo amo da Ge moilai (Ibia: me moilai gadenene) amoga asili, Yihiu ea dunu da e gala: i. Be e da bu asili, Migidou moilai bai bagadega doaga: le, bogoi.
Nígbà tí Ahasiah ọba, Juda rí ohun tí ó ti ṣẹlẹ̀, ó sálọ sójú ọ̀nà sí Beti-Haggani. Jehu sì lépa rẹ̀, ó ń kígbe, “Pa á pẹ̀lú!” Wọ́n ṣá a ní ọgbẹ́ nínú kẹ̀kẹ́ ẹ rẹ̀ ní ọ̀nà lọ sí Guri lẹ́bàá a Ibleamu, ṣùgbọ́n ó sálọ sí Megido, ó sì kú síbẹ̀.
28 A: ihasaia ea eagene ouligisu dunu da ea bogoi da: i hodo lale, ‘sa: liode’ da: iya ligisili, Yelusaleme moilai bai bagadega gaguli asili, hina bagade bogoi uli dogosu sogebi, Da: ibidi Moilai Bai Bagade ganodini, uli dogone sali.
Ìránṣẹ́ rẹ̀ sì gbé e pẹ̀lú kẹ̀kẹ́ lọ sí Jerusalẹmu, ó sì sin ín pẹ̀lú, baba a rẹ̀ nínú ibojì rẹ̀ ní ìlú ńlá ti Dafidi.
29 Isala: ili hina bagade Youla: me (A: iha: be egefe) amo ea ouligibi ode gidayale ganodini, A:ihasaia da Yuda hina bagade hamoi.
(Ní ọdún kọkànlá ti Joramu ọmọ Ahabu, Ahasiah ti di ọba Juda.)
30 Yihiu da Yeseliele moilai bai bagadega doaga: i. Yesebele da hou doaga: i nababeba: le, ea si widasilale, ea dialuma hinabo nina: hahamone, fo misa: ne agenesidili lela, logoa gudu ba: le gudui.
Nígbà náà Jehu lọ sí Jesreeli. Nígbà tí Jesebeli gbọ́ nípa rẹ̀, ó kun ojú u rẹ̀, ó to irun rẹ̀, ó sì wò jáde láti ojú fèrèsé.
31 Yihiu da moilai logo holeiga golili manoba, Yesebele da amane wele sia: i, “Di Similai! Fane legesu dunu di! Abuliba: le guiguda: misi?”
Bí Jehu ti wọ ẹnu ìlẹ̀kùn, ó béèrè, “Ṣé ìwọ wá ní àlàáfíà, Simri, ìwọ olùpa ọ̀gá à rẹ?”
32 Yihiu da ba: le gadole, amane wele sia: i, “Namagai da nowala: ?” Hina bagade diasu ouligisu dunu aduna o udiana da fo misa: ne agenesidili ema gudu ba: le gudui.
Ó gbójú sókè láti wo fèrèsé, ó sì pè jáde, “Ta ni ó wà ní ẹ̀gbẹ́ mi? Ta ni?” Ìwẹ̀fà méjì tàbí mẹ́ta bojú wò ó nílẹ̀.
33 Yihiu da ilima amane sia: i, “Amo uda galaguduma!” Ilia da Yesebele amo ouga: ne galagudui. Ea maga: me da dobea fei damana, amola hosi damana siagagala: i. Yihiu da ea ‘sa: liode’ da: iya fila heda: le amo uda ososa: gi.
Jehu sọ wí pé, “Gbé e jù sílẹ̀!” Wọ́n sì jù ú sílẹ̀. Díẹ̀ nínú ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ sì fọ́n sí ara ògiri àti àwọn ẹṣin bí wọ́n ti tẹ̀ ẹ́ mọ́lẹ̀ lábẹ́ ẹsẹ̀ wọn.
34 Amalalu, Yihiu da hina bagade diasuga golili sa: ili, ha: i mai. Amogalu fawane, e da amane sia: i, “Amo gagabui aligi uda, uli dogone sanasima. Bai e da hina bagade idiwi.”
Jehu wọ inú ilé lọ, ó jẹ, ó sì mu. “Tọ́jú obìnrin yẹn tí a fi bú,” Ó wí, “Kí o sì sin ín, nítorí ọmọbìnrin ọba ni ó jẹ́.”
35 Be dunu da e uli dogomusa: asili, ea dialuma gasa amola ea lobo gasa amola emo gasa amo fawane diafulubi ba: i.
Ṣùgbọ́n nígbà tí wọ́n jáde lọ láti lọ sin ín, wọn kò rí nǹkan kan àyàfi agbárí i rẹ̀, ẹsẹ̀ rẹ̀ méjèèjì àti ọwọ́ rẹ̀ méjèèjì.
36 Ilia da amo Yihuma sia: legebeba: le, e da amane sia: i, “Hina Gode da ea hawa: hamosu dunu Ilaidiamadili sia: i defele, amo hou da doaga: i. Hina Gode da amane sia: i, ‘Yesebele ea da: i hodo da Yeseliele soge ganodini, wa: mega mai dagoi ba: mu.
Wọ́n padà lọ sọ fún Jehu, ẹni tí ó wí pé, “Èyí ni ọ̀rọ̀ Olúwa tí ó sọ nípasẹ̀ ìránṣẹ́ rẹ̀ Elijah ará Tiṣibi wí pé, ‘Ní orí oko Jesreeli ni àwọn ajá yóò ti jẹ ẹran-ara Jesebeli.
37 Ea da: i hodo oda dialebe da iga safasi agoai ba: mu. Amasea, dunu afae da amo da Yesebele ea da: i hodo hamedafa dawa: mu,’”
Òkú Jesebeli yóò dàbí ohun ẹ̀gbin ní orí oko Jesreeli, dé bi pé, ẹnikẹ́ni kì yóò lè sọ pé, “Jesebeli ni èyí.”’”

< 2 Hina 9 >