< 2 Hina 8 >

1 Ilaisia da musa: Siunemega esalu uda (amo ea mano bogoi e da uhinisi) ema, Hina Gode da ha: i bagade Isala: ili sogega iasimu amo olelei. E da amane sia: i, “Amo ha: i bagade da ode fesuale agoane dialumu. Di amola dia sosogo fi amo Isala: ili soge fisili, asili, eno sogega esalumusa: masa.”
Nísinsin yìí, Eliṣa wí fún obìnrin náà tí ọmọ rẹ̀ ọkùnrin jí padà sáyé pé, “Jáde lọ pẹ̀lú ìdílé rẹ kí o sì lọ dúró fún ìgbà díẹ̀ ní ibikíbi tí o bá le dúró sí, nítorí Olúwa ti pàṣẹ ìyàn ní ìlú tí yóò lò tó ọdún méje.”
2 Siuneme uda da ea hamoma: ne sia: i nababeba: le, e da ea sosogo fi amo Filisidini fi ilia sogega oule asili, amogawi ode fesuale esalu.
Obìnrin náà tẹ̀síwájú gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ ènìyàn Ọlọ́run ti sọ. Òun àti ìdílé rẹ̀ sí lọ, wọ́n sì ṣe àtìpó ní ilẹ̀ àwọn ará Filistini fún ọdún méje.
3 Ha: i bagade ode fesuale gidigibiba: le, e da Isala: ili sogega buhagili, hina bagadema asili, e da ea diasu amola soge, amo hima bu ima: ne adole ba: i.
Ní ẹ̀yìn ọdún méje ó sì padà wá láti ilẹ̀ àwọn ará Filistini ó sì lọ sí ọ̀dọ̀ ọba láti lọ bẹ̀ ẹ́ fún ilé àti ilẹ̀ rẹ̀.
4 E da Isala: ili hina bagadema doaga: loba, e amola Ilaisia ea hawa: hamosu dunu Gihaisai ela gilisili sia: dalebe ba: i. Hina bagade da Ilaisia ea musa: hame ba: i gasa bagade hou amo dawa: mu hanai.
Ọba sì ń sọ̀rọ̀ sí Gehasi, ìránṣẹ́ ènìyàn Ọlọ́run pé, “Sọ fún mi nípa gbogbo ohun ńlá tí Eliṣa ti ṣe.”
5 Gihaisai da hina bagadema, Ilaisia ea bogoi dunu bu esaloma: ne hamoi sia: adodoloba, Siuneme uda da misini, hina bagadema ea adole ba: su adole ba: i. Gihaisai da hina bagadema amane sia: i, “Hina bagade! Uda amo ea hou na dima olelei amola egefe amo bogoi amola Ilaisia da bu uhinisi, ela da goea!”
Bí Gehasi ti ń sọ bí tí Eliṣa ṣe jí òkú di alààyè, obìnrin náà tí ọmọ rẹ̀ ọkùnrin tí Eliṣa ti dá padà sí ayé wá láti bẹ ọba fún ilé àti ilẹ̀ rẹ̀. Gehasi sì wí pé, “Obìnrin náà nìyìí olúwa mi ọba, ọmọkùnrin rẹ náà nìyí tí Eliṣa ti jí dìde sí ayé.”
6 Isala: ili hina bagade da Siuneme udama adole ba: beba: le, uda da Gihaisai ea sia: be da dafawane sia: i. Amaiba: le, hina bagade da eagene ouligisu dunu afae amo ema misa: ne sia: ne, e da Siuneme udama ea musa: gagui huluane, amola ha: i manu ea sogega bugi, amola e soge enoga esaloba ode fesuale amoga ea lai defei, amo huluane hima bu ima: ne sia: i.
Ọba béèrè lọ́wọ́ obìnrin náà nípa rẹ̀, ó sì sọ fún un. Ó sì yan ìjòyè kan fún ún fún ọ̀rọ̀ rẹ̀ ó sì wí fún un pé, “Ẹ fún un padà gbogbo ohun tí ó bá jẹ́ tirẹ̀, àti pẹ̀lú gbogbo èrè ilé rẹ̀ fún ún láti ọjọ́ tí ó ti kúrò ní ìlú títí di àsìkò yìí.”
7 Silia hina bagade Beneha: ida: de da Dama: sagase moilai bai bagade ganodini oloi dialu. Amogalu, Ilaisia da Dama: saga: se moilaiga asi. Beneha: ida: de da Ilaisia amogai esala sia: be nababeba: le,
Eliṣa lọ sí Damasku, Beni-Hadadi ọba Siria ń ṣe àìsàn. Nígbà tí wọ́n sọ fún ọba pé, “Ènìyàn Ọlọ́run ti wá láti gbogbo ọ̀nà òkè síbí,”
8 e da ea eagene ouligisu dunu Ha: sa: iele, ema amane sia: i, “Di balofede dunuma hahawane iasu iasili, ema amane adole ba: ma, ‘Di Hina Godema adole ba: ma, amo hina bagade ea oloi da uhima: bela: le?”
ọba sì wí fún Hasaeli pé, “Mú ọrẹ lọ́wọ́ rẹ, sì lọ pàdé ènìyàn Ọlọ́run. Kí o sì béèrè Olúwa láti ọ̀dọ̀ rẹ̀, béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé ṣé èmi yóò sàn nínú àìsàn yìí?”
9 Amaiba: le, Ha: sa: iele da Dama: saga: sega masusa: liligi noga: idafa ga: mele40agoane amo da: iya ligisili, Ilaisiama asi. Ha: sa: iele da Ilaisia gousa: le, ema amane sia: i, “Dia hawa: hamosu dunu hina bagade Beneha: ida: de da dima amane adole ba: ma: ne, na asunasi, ‘Na oloi da uhima: bela: o hame uhima: bela: ?’”
Hasaeli lọ láti pàdé Eliṣa, ó mú lọ pẹ̀lú rẹ̀ ẹ̀bùn gẹ́gẹ́ bí ogójì ẹrù ìbákasẹ tí gbogbo ìní tí ó dára jù fún wíwò ti Damasku, ó sì wọlé lọ ó sì dúró níwájú rẹ̀, ó sì wí pé, “Ọmọ rẹ Beni-Hadadi ọba Siria rán mi láti béèrè pé, ‘Ṣé èmi yóò sàn nínú àìsàn mi yìí?’”
10 Ilaisia da bu adole i, “Hina Gode da nama amane olelei, ‘e da bogomu’. Be di ema asili, e da uhimu, ema amane adoma!”
Eliṣa da á lóhùn pé, “Lọ kí o lọ sọ fún un pé, ‘Ìwo ìbá sàn nítòótọ́’; ṣùgbọ́n Olúwa ti fihàn mí pé nítòótọ́ òun yóò kùú.”
11 Amalalu, Ilaisia da Ha: sa: ielema fofogadigili nani sosodoaligili, Ha: sa: iele da beda: i. Hedolowane, Ilaisia da doleledane di.
Ó sì ranjú mọ́ ọn pẹ̀lú àtẹjúmọ́ gidigidi títí tí ojú fi ti Hasaeli. Nígbà náà ènìyàn Ọlọ́run bẹ̀rẹ̀ sí ní sọkún.
12 Ha: sa: iele da ema adole ba: i, “Hina! Di da abuliba: le disala: ?” Ilaisia da bu adole i, “Bai na da gugunufinisisu hou amo di da Isala: ili fi dunuma hamomu, amo dawa: Di da ilia gagili sali moilai laluga ulagimu. Amola ilia ayeligi noga: idafa huluane medole lelegemu, amola ilia mano huluane fufuga: le lelegemu. Amola ilia uda abula agui huluane oda hihidamu.”
“Kí ni ó dé tí olúwa mi fi ń sọkún?” Hasaeli béèrè. “Nítorí pé èmi mọ ibi tí ìwọ yóò ṣe sí Israẹli,” ó sì dáhùn pé, “Ìwọ yóò fi iná si odi agbára wọn, ìwọ yóò, pa àwọn ọ̀dọ́ ọmọkùnrin wọn pẹ̀lú idà, ìwọ yóò kọlù àwọn ọmọ wẹ́wẹ́ wọn, ìwọ ó sì fọ́ wọn túútúú, ìwọ o sì la inú àwọn aboyún wọn.”
13 Ha: sa: iele da bu adole ba: i, “Na da habodane agoane gasa bagade hou hamoma: bela: ? Na da hamedei dunu fawane!” Ilaisia da bu adole i, “Hina Gode da nama amane olelei. Di da Silia hina bagade hamomu.”
Hasaeli sì wí pé. “Báwo ni ìránṣẹ́ rẹ, ajá lásán làsàn yóò ṣe ṣe irú nǹkan ńlá bẹ́ẹ̀?” “Olúwa ti fihàn mí pé ìwọ ni yóò jẹ ọba Siria,” Eliṣa dá a lóhùn.
14 Ha: sa: iele da Beneha: ida: dema buhagi. Beneha: ida: de da ema amane adole ba: i, “Ilaisia da adi sia: bela: ?” Ha: sa: iele da bu adole i, “E da di uhimu sia: i.”
Nígbà náà Hasaeli fi Eliṣa sílẹ̀ ó sì padà sí ọ̀dọ̀ ọ̀gá rẹ̀. Nígbà tí Beni-Hadadi béèrè, “Kí ni ohun tí Eliṣa sọ fún ọ?” Hasaeli dá a lóhùn, “Ó sọ fún mi wí pé ìwọ yóò sàn nítòótọ́.”
15 Be aya amoga, Ha: sa: iele da abula sosone diasu lale, hano gele, hina bagade ea midofoga: le gagulaligili, medole legei dagoi. Amola Ha: sa: iele da Beneha: ida: de bagia, Silia hina bagade hamoi.
Ṣùgbọ́n ní ọjọ́ kejì ó mú aṣọ tí ó nípọn, ó sì kì í bọ inú omi ó sì tẹ̀ ẹ́ sí ojú ọba, bẹ́ẹ̀ ni ó sì kú. Nígbà náà Hasaeli sì rọ́pò rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọba.
16 Isala: ili hina bagade Youla: me (A: iha: be egefe) amo da ode biyale ouligilalu, Yihoula: me (Yihosiafa: de egefe) da Yuda hina bagade hamoi.
Ní ọdún karùn-ún ti Joramu ọmọ Ahabu ọba Israẹli, nígbà tí Jehoṣafati jẹ́ ọba Juda, Jehoramu ọmọ Jehoṣafati bẹ̀rẹ̀ ìjọba rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọba Juda.
17 Amo esoha e da lalelegele, ode 32 agoane esalu. E da Yelusaleme moilai bai bagadega esala, ode godoaneagoane Yuda soge ouligilalu.
Ó jẹ́ ẹni ọdún méjìlélọ́gbọ̀n nígbà tí ó di ọba. Ó sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún ọdún mẹ́jọ.
18 Ea uda da A: iha: be ea idiwi. Amola Yihoula: me da A: iha: be ea sosogo fi amola Isala: ili hina bagade ilia hou defele, wadela: le bagade hamoi. E da Hina Godema wadela: le hamoi.
Ó sì rìn ní ọ̀nà ọba Israẹli, gẹ́gẹ́ bí ilé Ahabu ti lọ, nítorí ó fẹ́ ọmọbìnrin Ahabu ó sì ṣe ohun búburú níwájú Olúwa.
19 Be Hina Gode da Yuda fi gugunufinisimu higa: i. Bai E da musa: Da: ibidi amola egaga sosogo fi da mae fisili, Yuda fi ouligilaloma: ne ilegele sia: i dagoi.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, nítorí ti ìránṣẹ́ rẹ̀ Dafidi. Olúwa kò fẹ́ pa Juda run, ó ti ṣèlérí láti ṣètọ́jú ìmọ́lẹ̀ fún Dafidi àti àwọn ilé rẹ̀ títí láéláé.
20 Yihoula: me da Yuda fi ouligilalebe, Idome fi dunu da Yudama odoga: ne, ilisu ilia fi ouligi.
Ní àkókò Jehoramu, Edomu ṣọ̀tẹ̀ sí Juda, wọ́n sì gbé ọba tiwọn kalẹ̀.
21 Amaiba: le, Yihoula: me amola ea ‘sa: liode’ fila heda: i dadi gagui dunu da Sa: ie moilaiga gegemusa: asi. Amogawi, Idome dadi gagui wa: i da Yihoula: me ea dadi gagui wa: i amo eale disi. Yihoula: me amola ea ‘sa: liode’ ouligisu dunu da eale disi amomane fili, hobeale asi. Yuda dadi gagui dunu huluane da afogogole, afae afae hi diasua buhagi.
Bẹ́ẹ̀ ni Jehoramu lọ sí Sairi pẹ̀lú gbogbo kẹ̀kẹ́ rẹ̀. Àwọn ará Edomu sì yí i ká àti kẹ̀kẹ́ àwọn olórí wọn, ṣùgbọ́n ó dìde dúró ní òru; àwọn ogun rẹ̀ síbẹ̀síbẹ̀, sá padà lọ ilé.
22 Amoganini, Idome fi da ilisu ouligisu. Amola Yihoula: me ea ouligilalu, Libina moilai bai bagade fi da ema odoga: i.
Títí ó fi di òní, Edomu wà nínú ọ̀tẹ̀ lórí Juda, Libina ṣọ̀tẹ̀ ní àkókò kan náà.
23 Yihoula: me ea hou eno huluane da “Yuda hina bagade ilia Hamonanu Meloa” amo ganodini dedene legei.
Gẹ́gẹ́ bí fún iṣẹ́ mìíràn ti ìjọba Jehoramu, àti gbogbo ohun tí ó ṣe, ṣé a kò ha kọ wọ́n sínú ìwé ọ̀rọ̀ ọjọ́ àwọn ọba Juda?
24 Yihoula: me da bogoi amola hina bagade ilia bogoi uli dogosu sogebi Da: ibidi Moilai Bai Bagade ganodini uli dogonesi. Egefe A: ihasaia da e bagia Yuda hina bagade hamoi.
Jehoramu sì sùn pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀ a sì sin ín pẹ̀lú wọn ní ìlú Dafidi, Ahasiah ọmọ rẹ̀ sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
25 Isala: ili hina bagade Youla: me (A: iha: be egefe) da ode fagoyale Isala: ili ouligilalu, A:ihasaia (Yihoula: me egefe) da Yuda fi ilia hina bagade hamoi.
Ní ọdún méjìlá Joramu ọmọkùnrin Ahabu ọba Israẹli, Ahasiah ọmọkùnrin Jehoramu ọba Juda bẹ̀rẹ̀ ìjọba rẹ̀.
26 E da lalelegele ode22 agoane esalu, Yuda hina bagade hamoi. E da Yelusaleme moilai bai bagadega esala, ode afae fawane Yuda fi ouligilalu. Ea: me da A: dalaia (Isala: ili hina bagade A: iha: be ea idiwi amola Isala: ili hina bagade Omeli amo ea aowa).
Ahasiah jẹ́ ẹni ọdún méjìlélógún nígbà tí ó di ọba. Ó sì jẹ ọba ní ọdún kan ní Jerusalẹmu. Orúkọ ìyá rẹ̀ a sì máa jẹ́ Ataliah, ọmọbìnrin Omri ọba Israẹli.
27 A: ihasaia ea ame da hina bagade A: iha: be ea idiwiba: le, e da A: iha: be ea sosogo fi defele, Hina Godema wadela: le hamoi.
Nígbà tí ó rin ọ̀nà ilé Ahabu ó sì ṣe búburú níwájú Olúwa, gẹ́gẹ́ bí ilé Ahabu ti ṣe, nítorí ó tan nípa ìgbéyàwó sí ìdílé Ahabu.
28 Yuda hina bagade A: ihasaia amola Isala: ili hina bagade Youla: me ela da gilisili, Silia hina bagade Ha: sa: ielema gegei. Ilia dadi gagui wa: i da La: imode moilai bai bagade, Gilia: de soge ganodini, amogai migagadenene gegei. Youla: me da amogai gegenana, gala: i ba: i.
Ahasiah sì lọ pẹ̀lú Joramu ọmọ Ahabu lọ sí ogun lórí Hasaeli ọba Aramu ní Ramoti Gileadi. Àwọn ará Siria ṣẹ́ Joramu lẹ́sẹ̀.
29 E da e gala: i fa: gi bahoma: ne, Yeseliele moilai bai bagadega buhagi. Amola A: ihasaia da amoga e ba: la asi.
Bẹ́ẹ̀ ni ọba Joramu padà sí Jesreeli láti wo ọgbẹ́ rẹ̀ sàn tí ará Siria ti jẹ ní yà lórí rẹ̀ ní Ramoti ní ojú ogun rẹ̀ pẹ̀lú Hasaeli ọba Aramu. Nígbà náà Ahasiah ọmọ Jehoramu ọba Juda sọ̀kalẹ̀ lọ sí Jesreeli láti lọ wo Joramu ọmọ Ahabu nítorí tí ó fi ara pa.

< 2 Hina 8 >