< 2 Hina 11 >

1 Hina bagade A: ihasaia ea ame A: dalaia da egefe da medole legei nababeba: le, e da hina bagade ea sosogo fi dunu huluane medole legema: ne sia: si.
Nígbà tí Ataliah ìyá Ahasiah rí i wí pé ọmọ rẹ̀ ti kú, ó tẹ̀síwájú láti pa gbogbo ìdílé ọba náà run.
2 A: ihasaia egefe Youa: se e fawane da hame medole legei ba: i. Ilia da e amola eno sosogo fi dunu fane legemusa: misini, ea awa Yihosiba (hina bagade Yihoula: me ea idiwi amola A: ihasaia ea dalusi) e da Youa: se gei. E da Youa: se amola ea ouligisu uda amo dia ahoasu sesei Debolo ganodini amoga oule asili, amola A: dalaia ea mae ba: ma: ne, ela wamolegei. Amalalu, ilia da Youa: se hame medole legei.
Ṣùgbọ́n Jehoṣeba ọmọbìnrin ọba Jehoramu àti arábìnrin Ahasiah, mú Joaṣi ọmọ Ahasiah, ó sì jí i lọ kúrò láàrín àwọn ọmọ-aládébìnrin ti ọba náà, tí ó kù díẹ̀ kí a pa. Ó gbé òhun àti olùtọ́jú rẹ̀ sínú ìyẹ̀wù láti fi pamọ́ kúrò fún Ataliah; bẹ́ẹ̀ ni a kò pa á.
3 Yihosiba da ode gafeyale agoanega Youa: se ouligi. A: dalaia da Yuda fi ouligilaloba, Youa: se da Debolo diasu ganodini wamoaligili esalebe ba: i, amola Yihosiba da e ouligi.
Ó wà ní ìpamọ́ pẹ̀lú olùtọ́jú ní ilé tí a kọ́ fún Olúwa fún ọdún mẹ́fà nígbà tí Ataliah fi jẹ ọba lórí ilẹ̀ náà.
4 Be ode fesuga, gobele salasu dunu Yihoida da hina bagade uda ea da: igene sosodo aligisu dunu amola hina bagade diasu sosodo aligisu dunu ilia hina dunu, ilima Debolo diasua misa: ne sia: i. Amogawi, e da sia: beba: le, ilia da ea hamomu liligi amo fidima: ne dafawane ilegele sia: i. E da hina bagade A: ihasaia egefe Youa: se wamo esalu, amo ilima olei.
Ní ọdún keje, Jehoiada ránṣẹ́ ó sí mú àwọn olórí lórí ọ̀rọ̀ọ̀rún, pẹ̀lú àwọn balógun àti àwọn olùṣọ́, ó sì mú wọn wá sí ọ̀dọ̀ rẹ̀ nínú ilé tí a kọ́ fún Olúwa. Ó ṣe májẹ̀mú pẹ̀lú wọn, ó sì fi wọ́n sí abẹ́ ìbúra nínú ilé tí a kọ́ fún Olúwa. Níbẹ̀ ni ó fi ọmọkùnrin ọba hàn wọ́n.
5
Ó pàṣẹ fún wọn, wí pé, “Ìwọ tí ó wà nínú àwọn ẹgbẹ́ mẹ́tẹ̀ẹ̀ta tí ó ń lọ fún iṣẹ́ ìsìn ní ọjọ́ ìsinmi—ìdámẹ́ta yín fún ṣíṣọ́ ààfin ọba.
6 E da ilima amane hamoma: ne sia: i, “Dilia da Sa: bade eso hawa: hamomusa: masea, mogi udiana amoga eno da hina bagade uda ea diasu sosodo aligima: ne sia: ma! Mogi udiana amoga, eno da Se Logo Ga: suga sosodo aligima: ne sia: ma! Amola mogi udiana amoga, eno da logo ga: su sosodo aligisu dunu ilia baligia sosodo aligima: ne sia: ma!
Ìdámẹ́ta ní ẹnu ìlẹ̀kùn huri, àti ìdámẹ́ta ní ẹnu ìlẹ̀kùn ní ẹ̀yìn olùṣọ́, tí ó yípadà ní ṣíṣọ́ ilé tí a kọ́,
7 Be sosodo aligisu dunu gilisisu aduna amo da Sa: bade esoga helefisia, ilia da hina bagade Youa: se gemusa: , Debolo diasu sosodo aligima: ne sia: ma!
àti ẹ̀yin tí ó wà ní ẹgbẹ́ kejì yòókù tí kì í lọ ibi iṣẹ́ ìsìn ní ọjọ́ ìsinmi gbogbo ni kí ó ṣọ́ ilé tí a kọ́ fún Olúwa fún ọba.
8 Dilia da gegesu gobihei duga: le gadolewane, hina bagade Youa: se noga: le gema: mu! E da habidili ahoasea, dili e sigi masa. Nowa da dilima gadenena masea, medole legema!”
Ẹ mú ibùjókòó yín yí ọba ká, olúkúlùkù ọkùnrin pẹ̀lú ohun ìjà rẹ̀ ní ọwọ́ rẹ̀. Ẹnikẹ́ni tí ó bá súnmọ́ ọgbà yìí gbọdọ̀ kú. Ẹ dúró súnmọ́ ọba ní ibikíbi tí ó bá lọ.”
9 Ouligisu dunu ilia da Yihoida ea hamoma: ne sia: i defele hamoi. Ilia da ilia dunu, gilisisu amo da Sa: bade esoga helefi amola gilisisu amo da Sa: bade esoga hawa: hamonanu, amo huluane Yihoidama oule asi.
Olórí àwọn ọ̀rọ̀ọ̀rún ṣe gẹ́gẹ́ bí Jehoiada àlùfáà ti pa á láṣẹ. Olúkúlùkù mú àwọn ọkùnrin rẹ̀ àwọn tí ó ń lọ sí iṣẹ́ ìsìn ní ọjọ́ ìsinmi àti àwọn tí wọ́n wá sí ọ̀dọ̀ Jehoiada àlùfáà.
10 Yihoida da musa: hina bagade Da: ibidi ea goge agei amola ludasa: besa: le gaga: su liligi huluane Debolo diasu ganodini modaligi, amo lale, ouligisu dunu ilima i.
Nígbà náà, ó fún àwọn olórí ní àwọn ọ̀kọ̀ àti àwọn àpáta tí ó ti jẹ́ ti ọba Dafidi tí ó sì wà nínú ilé tí a kọ́ fún Olúwa.
11 Amola e da dunu ilia gegesu gobihei duga: le gadole, amo hina bagade Youa: se gemusa: , Debolo diasu midadi sisiga: le dadalema: ne asunasi.
Àwọn olùṣọ́, olúkúlùkù pẹ̀lú ohun ìjà rẹ̀ ní ọwọ́ rẹ̀, wọ́n sì dúró ṣinṣin yìí ọba ká—lẹ́bàá pẹpẹ àti ilé ìhà gúúsù sí ìhà àríwá ilé tí a kọ́ fun Olúwa náà.
12 Amalalu, Yihoida da Youa: se amo gadili oule asili, hina bagade habuga ea dialuma da: iya figisili, meloa amo ganodini da hina bagade ilia sema dedei ema i. Amalalu, e da Youa: se ea dialuma da: iya susuligi sogagala: le, e Yuda hina bagade hamoma: ne ilegei. Dunu huluane da lobo fane, amane wele sia: i, “Hina bagade da sedagili esalumu da defea!”
Jehoiada mú ọmọkùnrin ọba jáde, ó sì gbé adé náà lé e: ó fún un ní ẹ̀dà májẹ̀mú, wọ́n sì kéde ọba rẹ̀. Wọ́n fi àmì òróró yàn án, àwọn ènìyàn pa àtẹ́wọ́, wọ́n sì kígbe, “Kí ẹ̀mí ọba kí ó gùn.”
13 Hina bagade uda A: dalaia da sosodo aligisu dunu amola gilisi dialu dunu ilia nodosa gugulubi amo nababeba: le, e da hehenaia Debolo diasuga doaga: loba, dunu bagohame amogawi gilisi dialebe ba: i.
Nígbà tí Ataliah gbọ́ ariwo tí àwọn olùṣọ́ àti àwọn ènìyàn ń pa, ó lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn ènìyàn nínú ilé tí a kọ́ fún Olúwa.
14 Amogawi, e da hina bagade gaheabolo, Yuda fi ilia hou defele, golasu ifa bagade Debolo Diasu logo holeiga dialu, amo dafulili lelebe ba: i. Ouligisu dunu huluane amola dalabede dusu dunu ilia da e sisiga: le lelefulu. Amola dunu huluane da hahawane wele sia: nanebe amola dalabede fulabolalebe ba: i. A: dalaia da bagadewane da: i dioiba: le, ea abula gadelale, ha: giwane amane wele sia: i, “Hohonosu! Hohonosu da doaga: i dagoi.”
Ó wò ó, níbẹ̀ ni ọba, tí ó dúró lẹ́bàá òpó, gẹ́gẹ́ bí àṣà ti rí. Àwọn balógun àti àwọn afùnpè wà ní ẹ̀bá ọba, gbogbo àwọn ènìyàn ilé náà sì ń yọ̀, wọ́n sì ń fun ìpè pẹ̀lú. Nígbà náà Ataliah fa aṣọ ìgúnwà rẹ̀ ya. Ó sì kégbe pé, “Ọ̀tẹ̀! Ọ̀tẹ̀!”
15 Yihoida da A: dalaia amo Debolo diasu sogebi ganodini medole legei ba: mu higa: i galu. Amaiba: le e da dadi gagui wa: i ouligisu dunu ilima amane hamoma: ne sia: i, “A: dalaia amo sosodo aligisu dunu ilia dadalei dogoa amoga gadili oule masa. Nowa da e gemusa: hamosea, amo medole legema!”
Jehoiada àlùfáà pàṣẹ fún olórí ọ̀rọ̀ọ̀rún, ta ni ó wà ní ìkáwọ́ ọ̀wọ́ ogun: “Mú u jáde láàrín àwọn ẹgbẹ́ ogun yìí kí o sì fi sí ipa idà ẹnikẹ́ni tí ó bá tẹ̀lé.” Nítorí àlùfáà ti sọ, “A kò gbọdọ̀ pa á nínú ilé tí a kọ́ fún Olúwa.”
16 Ilia da A: dalaia gagulaligili, hina bagade diasuga gaguli oule asili, Hosi Logo Ga: sua amogai, e medole legei dagoi.
Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n fi agbára mú un bí ó ti dé ibi tí àwọn ẹṣin tí ń wọ ilẹ̀ ààfin ọba àti níbẹ̀ ni a ti pa á.
17 Gobele salasu dunu Yihoida da amane hamoma: ne sia: beba: le, hina bagade Youa: se amola Yuda fi dunu da Hina Godema ilia da Ea fidafa fawane esaloma: ne, dafawane ilegele sia: su hamoi. Amola Yihoida da sia: beba: le, Yuda fi dunu da, ilia hina bagade noga: le fuli gala: ma: ne, dafawane ilegele sia: su.
Nígbà náà ni Jehoiada dá májẹ̀mú láàrín Olúwa àti ọba àti àwọn ènìyàn tí yóò jẹ́ ènìyàn Olúwa. Ó dá májẹ̀mú láàrín ọba àti àwọn ènìyàn pẹ̀lú.
18 Amalalu, dunu huluane da ogogosu ‘gode’ Ba: ile ea debolo diasuga asili, amo mugululi, wadela: lesi. Ilia da oloda amola loboga hamoi ‘gode’ agoaila huluane gugunufinisi. Amola ilia da oloda amo ilia midadi, Ba: ile gobele salasu dunu Ma: da: ne, medole legei dagoi. Yihoida da sosodo aligisu dunu Debolo Diasu ouligima: ne asunasi.
Gbogbo àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà lọ sí ilé tí a kọ́ fún òrìṣà Baali wọ́n sì ya á bolẹ̀. Wọ́n fọ́ àwọn pẹpẹ àti òrìṣà sí wẹ́wẹ́. Wọ́n sì pa Mattani àlùfáà Baali níwájú àwọn pẹpẹ. Nígbà náà, Jehoiada àlùfáà náà sì yan àwọn olùṣọ́ sí ilé tí a kọ́ fún Olúwa.
19 Amalalu, e amola dadi gagui wa: i ouligisu dunu amola hina bagade da: i sosodo aligisu dunu, ilia da hina bagade amo Debolo diasu fisili, hina bagade diasuga oule asi. Dunu huluane da ili bobogei. Youa: se da Sosodo Aligisu Logo Ga: su amoga hina bagade diasu golili sa: ili, hina bagade fisu amoga fila heda: i.
Ó mú pẹ̀lú u rẹ̀ àwọn olórí ọ̀rọ̀ọ̀rún àti gbogbo balógun àti àwọn olùṣọ́ àti gbogbo àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà àti lápapọ̀, wọ́n mú ọba sọ̀kalẹ̀ wá láti ilé tí a kọ́ fún Olúwa. Wọ́n sì wọ inú ààfin lọ, wọ́n sì wọlé nípa ìlẹ̀kùn ti àwọn olùṣọ́. Ọba sì mú ààyè rẹ̀ ní orí ìtẹ́ ọba.
20 Dunu huluane da hahawane bagade ba: i. Moilai fi da ouiya: i dialebe ba: i. Bai A: dalaia da hina bagade diasu ganodini fane legei ba: i.
Gbogbo àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà sì yọ̀, ìlú náà sì dákẹ́ jẹ́ẹ́. Nítorí a pa Ataliah pẹ̀lú idà náà ní ààfin ọba.
21 Youa: se da lalelegele, ode fesuale esalu, e da muni Yuda hina bagade hamoi.
Joaṣi jẹ́ ọmọ ọdún méje nígbà tí ó bẹ̀rẹ̀ ìjọba rẹ̀.

< 2 Hina 11 >