< 2 Hina 10 >

1 Musa: Isala: ili hina bagade A: iha: be egaga fi misi dunu 70 agoane da Samelia ganodini esalebe ba: i. Yihiu da meloa dedene, amaiwane amo defele eno mogili hahamone, Samelia asigilai dunu amola moilai ouligisu dunu amola A: iha: be egaga fi misi dunu ilia ouligisu dunu, amo huluanema iasi. E dedei da amane dedei,
Nísinsin yìí, Ahabu ṣì ní àádọ́rin ọmọkùnrin ní ìdílé rẹ̀ ní Samaria. Bẹ́ẹ̀ ni, Jehu kọ lẹ́tà, ó sì fi wọ́n ránṣẹ́ sí Samaria: sí àwọn oníṣẹ́ Jesreeli, sí àwọn àgbàgbà àti sí àwọn olùtọ́jú àwọn ọmọ Ahabu. Ó wí pé,
2 “Dilia da hina bagade A: iha: be egaga fifi misi dunu amo ouligisa. Dilia da ‘sa: liode’ amola hosi amola gegesu liligi gagui gala. Amaiba: le, amo meloa dedei da dilima doaga: sea,
“Ní kété tí lẹ́tà bá ti dé ọ̀dọ̀ rẹ̀, níwọ̀n ìgbà tí àwọn ọmọ ọ̀gá rẹ wà pẹ̀lú rẹ, ìwọ sì ní àwọn kẹ̀kẹ́ àti àwọn ẹṣin, ìlú olódi kan pẹ̀lú ohun ìjà,
3 dilia hedolowane baligili dawa: su hina bagade egaga fi dunu afae, dilia hina bagade hamoma: ne ilegema. Amasea, e gaga: ma: ne, ninima gegema!”
yan èyí tí ó dára àti èyí tí ó níye jùlọ nínú àwọn ọmọkùnrin ọ̀gá à rẹ, kí o sì gbé e lé orí ìtẹ́ baba a rẹ̀. Nígbà náà, kí o sì jà fún ilé ọ̀gá à rẹ.”
4 Samelia ouligisu dunu da bagadewane beda: gia: i. Ilia da amane sia: i, “Ninia da habodane Yihuma ha lale, gegema: bela: ? Hina bagade Youla: me amola hina bagade A: ihasaia da e hasalasimu hamedei ba: i.”
Ṣùgbọ́n ẹ̀rù bà wọ́n, wọ́n sì wí pé, “Tí ọba méjì kò bá le kojú ìjà sí i, báwo ni a ṣẹ le è ṣe é?”
5 Amaiba: le, hina bagade diasu ouligisu dunu amola moilai ouligisu dunu amola asigilai dunu amola A: iha: be egaga fi dunu ilia ouligisu dunu, ilia da Yihuma amane sia: si, “Ninia da dia hawa: hamosu dunu esala. Ninia da dia sia: be liligi defele hamomusa: momagele esala. Be ninia da hina bagade hame ilegemu. Dia adi hou da noga: i di dawa: sea, amo hamoma!”
Bẹ́ẹ̀ ẹni tí ń ṣe olórí ilé, ẹni tí ń ṣe olórí ìlú ńlá, àwọn àgbàgbà àti àwọn olùtọ́jú náà rán iṣẹ́ yìí sí Jehu, pé, “Ìránṣẹ́ rẹ ni àwa jẹ́ pẹ̀lú, àwa yóò ṣe ohunkóhun tí o bá sọ. Àwa kì yóò yan ẹnikẹ́ni gẹ́gẹ́ bí ọba; ìwọ ṣe ohunkóhun tí o rò pé ó dára jù lójú rẹ.”
6 Yihiu da ilima meloa eno dedene iasi, “Dilia da namagai galea, amola na hamoma: ne sia: i amo hamomusa: momagele esalea, hina bagade A: iha: be egaga fi dunu huluane ilia dialuma amo aya wewaba, Yeseliele moilai bai bagadega nama gaguli misa: !” (Samelia asigilai dunu, ilia da hina bagade A: iha: be egaga fifi misi dunu ouligisu. Asigilai dunu da ili bugili ianu.)
Nígbà náà ni Jehu kọ lẹ́tà kejì sí wọn, wí pé, “Tí ìwọ bá wà ní ìhà tèmi, tí o sì pa ọ̀rọ̀ mi mọ́, mú orí àwọn ọmọkùnrin ọ̀gá à rẹ wá sí ọ̀dọ̀ mi ní Jesreeli ní ìwòyí ọ̀la.” Nísinsin yìí, àwọn ọmọ-aládé àádọ́rin ọkùnrin, ń bẹ pẹ̀lú àwọn ènìyàn ńlá ìlú náà tí ń tọ́ wọn.
7 Yihiu ea meloa dedei da ilima doaga: loba, Samelia moilai bai bagade ouligisu dunu, ilia da A: iha: be egaga fi dunu 70 agoane huluane medole lelegele, ilia dialuma damuni fasili, daba ganodini salawene, Yeseliele moilai bai bagadega Yihuma iasi.
Nígbà tí ìwé náà dé ọ̀dọ̀ wọn, àwọn ọkùnrin wọ̀nyí mú gbogbo àwọn ọmọ ọba tí gbogbo wọ́n jẹ́ àádọ́rin wọ́n sì pa gbogbo wọn. Wọ́n gbé orí wọn sí inú apẹ̀rẹ̀, wọ́n fi ránṣẹ́ sí Jehu ní Jesreeli.
8 Ilia da Yihuma, A:iha: be egaga fi dunu ilia dialuma da gaguli misi dagoi adobeba: le, e da amo dialuma gasa huluane mogili aduna ligiagale moilai gagoi logo holei gadenene ligisi, dialeawane hahabe hadigima: ne sia: i.
Nígbà tí ìránṣẹ́ náà dé, ó sọ fún Jehu, “Wọ́n ti gbé orí àwọn ọmọ ọba náà wá.” Nígbà náà Jehu pàṣẹ, “Ẹ tò wọ́n ní òkìtì méjì ní àtiwọ ẹnu ibodè ìlú ńlá títí di òwúrọ̀.”
9 Golale hahabe, e da logo holeiga asili, amoga gilisi dunu ilima amane sia: i, “Ni fawane da hina bagade medole legema: ne wamo ilegele, amola e dafawane medole legei. Dilia hame! Be amo dunu amo nowa da medole legebela: ?
Ní òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, Jehu jáde lọ. Ó dúró níwájú gbogbo àwọn ènìyàn, ó sì wí pé, “Ẹ̀yin jẹ́ aláìjẹ̀bi. Èmi ni mo dìtẹ̀ sí ọ̀gá mi, tí mo sì pa á, ṣùgbọ́n ta ni ó pa gbogbo àwọn wọ̀nyí?
10 Hina Gode da Ea balofede dunu Ilaisiamadili, hou huluane amo da A: iha: be egaga fima misunu hou, olelei dagoi. Amola ilia huluane da medole legeiba: le, amo hou da dafawane doaga: i dagoi dawa: ma!”
Nígbà yìí, kò sí ọ̀rọ̀ kan tí Olúwa ti sọ sí ilé Ahabu tí yóò kùnà. Olúwa ti ṣe ohun tí ó ṣèlérí nípasẹ̀ ìránṣẹ́ rẹ̀ Elijah.”
11 Amalalu, Yihiu da A: iha: be egaga sosogo fi huluane Yeseliele ganodini esala, amola ea eagene ouligisu dunu amola ea dogolegei amola ea gobele salasu dunu, ili huluanedafa, ea medole legei. Dunu afae esalebe da hamedafa ba: i.
Bẹ́ẹ̀ ni Jehu pa gbogbo ẹni tí ó kù Jesreeli ní ilé Ahabu, pẹ̀lúpẹ̀lú gbogbo àwọn ọkùnrin ìjòyè rẹ̀, àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ tímọ́tímọ́ àti àwọn àlùfáà rẹ̀, láì ku ẹni tí ó yọ nínú ewu fún un.
12 Yihiu da Yeseliele fisili, Samelia amoma doaga: musa: asi. Logoga ahoanoba, e da sogebi ea dio amo “Sibi Ouligisu Fisisu” amoga,
Jehu jáde lọ, ó sì lọ sí ọ̀kánkán Samaria. Ní Beti-Ekedi tí àwọn olùṣọ́-àgùntàn.
13 e da hina bagade A: ihasaia bogoi, amo ea sosogo fi oda ba: i. E da ilima amane adole ba: i, “Dili da nowala: ?” Ilia da bu adole i, “Nini da A: ihasaia ea sosogo fi dunu. Ninia da hina bagade uda Yesebele ea manolali amola hina bagade sosogo fi eno Yeselielega esala, ilima asigi sia: saimusa: masunu.”
Jehu pàdé díẹ̀ lára àwọn ìbátan Ahasiah ọba Juda, ó sì béèrè, “Ta ni ẹ̀yin ń ṣe?” Wọ́n wí pé, “Àwa jẹ́ ìbátan Ahasiah, àwa sì ti wá láti kí ìdílé ọba àti ti màmá ayaba.”
14 Yihiu da ea dunuma amane hamoma: ne sia: i, “Ili mae medole, gagulaligima!” Ilia da ili huluane gagulaligili, Yihiu da uli dogoi amogai dialu, amo gadenene ili huluane medole legei. Ilia idi da 42 agoane, amola dunu afae esalebe hame ba: i.
“Mú wọn láààyè!” ó pàṣẹ. Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n mú wọn láààyè, wọ́n sì pa wọ́n ní ẹ̀bá kọ̀nga Beti-Ekedi, ọkùnrin méjìlélógójì. Kò sì fi ẹnìkan sílẹ̀ láìkù.
15 Yihiu da bu logoga ahoanoba, Yonada: be (Liga: be egefe) yosia: i. Yihiu da ema hahawane sia: ne, amane sia: i, “Ania asigi dawa: su da defele diala. Di da na fuli gala: ma: bela: ?” Yonada: be da bu adole i, “Ma! Na da dimagai dialumu!” Yihiu da bu adole i, “Defea! Amaiba: le, gousa: la: di!” Ela da gousa: lu, Yihiu da Yonada: be ‘sa: liode’ da: iya fila heda: ma: ne, lobolele gadoi.
Nígbà tí a sì jáde níbẹ̀, ó rí Jehonadabu ọmọ Rekabu ń bọ̀ wá pàdé rẹ̀, ó sì súre fún un, ó sì wí fún pé, “Ọkàn rẹ ha ṣe déédé bí ọkàn mi ti rí sí ọkàn rẹ?” Jehonadabu dáhùn wí pé, “Èmi wà.” Jehu wí pé, “Bí ó bá jẹ́ bẹ́ẹ̀, fún mi ní ọwọ́ ọ̀ rẹ.” Bẹ́ẹ̀ ni ó ṣe pẹ̀lú, Jehu sì fà á lọ́wọ́ sókè sọ́dọ̀ rẹ̀ nínú kẹ̀kẹ́.
16 Yihiu da amane sia: i, “Ani ahoa: di! Di da na Hina Godema fawane fa: no bobogesu hou ba: mu!” Elea da ‘sa: liode’ da: iya fila heda: le, Samelia moilai bai bagadega doaga: le,
Jehu wí pé, “Wá pẹ̀lú mi, kí o sì rí ìtara mi fún Olúwa.” Nígbà náà ó jẹ́ kí ó gun kẹ̀kẹ́ rẹ̀.
17 Yihiu da A: iha: be ea sosogo huluanedafa medole legei. E da dunu afae esaloma: ne hame yolesi. Amo hou Hina Gode da Ilaisiama olelei, amo defele doaga: i dagoi ba: i.
Nígbà tí Jehu wá sí Samaria, ó pa gbogbo àwọn tí a fi kalẹ̀ ní ìdílé Ahabu; ó pa wọ́n run, gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ Olúwa tí a sọ sí Elijah.
18 Yihiu da Samelia fi dunu huluane gilisima: ne sia: ne, ilima amane sia: i, “Hina bagade A: iha: be da Ba: ilema fonobahadi hawa: hamonanu. Be na da Ba: ilema asigiba: le, baligiliwane ema hawa: hamomu.
Nígbà náà, Jehu kó gbogbo àwọn ènìyàn jọ, ó sì wí fún wọn pé, “Ahabu sin Baali díẹ̀; ṣùgbọ́n Jehu yóò sìn ín púpọ̀.
19 Dilia Ba: ile ea balofede dunu amola ema nodone sia: ne gadosu dunu amola ea gobele salasu dunu huluanedafa guiguda: gilisima: ne sia: ma. Afae mae yolesima. Na da Ba: ilema gobele salasu bagadedafa hamomu. Amola nowa da hame masea, ninia da amo dunu medole legemu.” (Yihiu da ogogoi. E da Ba: ilema nodone sia: ne gadosu dunu huluane medole legemusa: ilegeiba: le, ili gilisima: ne sia: i)
Nísinsin yìí, ẹ pe gbogbo àwọn wòlíì Baali jọ fún mi, gbogbo àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ àti gbogbo àlùfáà rẹ̀, má ṣe jẹ́ kí ọ̀kan kí ó kù, nítorí èmí yóò rú ẹbọ ńlá sí Baali. Ẹnikẹ́ni tí ó bá kọ̀ láti wá, kò ní wà láààyè mọ́.” Ṣùgbọ́n Jehu fi ẹ̀tàn ṣe é, kí ó lè pa àwọn òjíṣẹ́ Baali run.
20 Amalalu, Yihiu da amane hamoma: ne sia: i, “Ba: ilema nodoma: ne, nodone sia: ne gadomusa: eso bagadedafa ilegema!” Ilia da amo eso ilegei.
Jehu wí pé, “ẹ pe àpéjọ ní ìwòyí ọ̀la fún Baali.” Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n kéde rẹ.
21 Amalu, Yihiu da Isala: ili soge huluane ganodini dunu huluane da amo nodone sia: ne gadosu amoga misa: ne sia: si. Ba: ilema nodone sia: ne gadosu dunu huluanedafa da misi. Ilia huluane da Ba: ile ea debolo diasu ganodini golili sa: ili, debolo diasu da nabaidafa ba: i.
Nígbà náà, Jehu rán ọ̀rọ̀ káàkiri Israẹli, gbogbo àwọn òjíṣẹ́ Baali sì wá: kò sí ẹnìkan tí ó dúró lẹ́yìn. Wọ́n kún ilé tí a kọ́ fún òrìṣà títí tí ó fi kún láti ìkangun èkínní títí dé èkejì.
22 Amalalu, Yihiu da Ba: ile gobele salasu dunu amo da sema abula ouligi, amo sema abula lale, nodone sia: ne gadosu dunu iligili ima: ne sia: i.
Jehu sì sọ fún olùṣọ́ pé, “Kí ó mú aṣọ ìgúnwà wá fún gbogbo àwọn òjíṣẹ́ Baali.” Bẹ́ẹ̀ ni ó mú aṣọ ìgúnwà jáde wá fún wọn.
23 Amalalu, Yihiu hisu da Yonada: be (Liga: be egefe) oule, debolo diasu ganodini golili sa: ili, dunu amo ganodini gilisi dialu ilima amane sia: i, “Gilisisu ganodini hogoma! Ba: ilema nodone sia: ne gadosu dunu fawane esaloma: ne sia: ma. Hina Godema nodone sia: ne gadosu dunu da goegai mae esaloma: ne sia: ma.”
Nígbà náà, Jehu àti Jehonadabu ọmọ Rekabu lọ sí inú ilé tí a kọ́ fún òrìṣà Baali. Jehu sì wí fún àwọn òjíṣẹ́ Baali pé, “Wò ó yíká, kí o sì rí i pé kò sí ìránṣẹ́ Olúwa kankan pẹ̀lú yín níbí—kìkì òjíṣẹ́ Baali.”
24 Amalalu, e amola Yonada: be da Ba: ilema gobele salimusa: golili sa: i. E da musa: dunu 80 agoane debolo gadili hamega leloma: ne ilegele, ilima amane sia: i, “Dilia amo dunu huluane fane legema. Nowa da dunu afae esaloma: ne yolesisia, e da dabele, medole legei dagoi ba: mu!”
Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n wọ inú ilé lọ láti lọ rú ẹbọ àti ẹbọ sísun. Nísinsin yìí Jehu ti rán ọgọ́rin ọkùnrin sí ìta pẹ̀lú ìkìlọ̀ yìí: “Tí ẹnikẹ́ni nínú yín bá jẹ́ kí ẹnikẹ́ni nínú àwọn ọkùnrin tí mo ń gbé sí ọwọ́ yín ó sálọ, yóò jẹ́ ẹ̀mí yín fún ẹ̀mí rẹ.”
25 Yihiu da gobele salasu liligi ianu, sosodo aligisu dunu amola dadi gagui wa: i ouligisu dunu ilima amane sia: i, “Ganodini golili sa: ili, dunu huluanedafa medole legema! Afae da maedafa hobeama: ma!” Ilia da gegesu gobihei duga: le gadole, ganodini golili sa: ili, Ba: ilema nodone sia: ne gadosu dunu huluanedafa medole lelegele, ilia da: i hodo moiya gadili hiougili sasali.
Ní kété tí Jehu ti parí ṣíṣe ẹbọ sísun, ó pàṣẹ fún àwọn olùṣọ́ àti àwọn ìjòyè: “Wọlé lọ, kí o sì pa wọ́n, má ṣe jẹ́ kí ẹnikẹ́ni kí ó sálọ.” Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n gé wọn lulẹ̀ pẹ̀lú idà. Àwọn olùṣọ́ àti ìjòyè ju ara wọn síta, wọ́n sì wọ inú ojúbọ ti ilé tí a kọ́ fún òrìṣà Baali.
26 Ilia da duni bugi ifa (amo da sema galu) amogai diala, amo gadili gaguli asili, laluga ulagili sali.
Wọ́n gbé òkúta bíbọ náà jáde láti inú ilé tí a kọ́ fún òrìṣà Baali, wọ́n sì jó o.
27 Ilia da amaiwane sema ifa duni bugi amola debolo diasu amo wadela: lesi. Ilia da debolo ea hou afadenene bu iga giasu diasu hamoi. Amola amo da wali amaiwane diala. (Amo da eso dedei amoga amaiwane diala)
Wọ́n fọ́ òkúta bíbọ ti Baali náà túútúú, wọ́n sì ya ilé òrìṣà Baali bolẹ̀. Àwọn ènìyàn sì ń lò ó fún ilé ìgbẹ́ títí di ọjọ́ òní.
28 Yihiu da amanewane Isala: ili soge ganodini, Ba: ilema nodone sia: ne gadosu hou gugunufinisi dagoi.
Bẹ́ẹ̀ ni Jehu pa sí sin Baali run ní Israẹli.
29 Be e da hina bagade Yelouboua: me (amo da gouliga hamoi bulamagau gawali mano aduna Bedele moilai amola Da: ne moilai ligisiba: le, Isala: ili dunu fi wadela: le hamoma: ne oule asi) Yihiu da ea hou defele hamoi.
Bí ó ti wù kí ó rí, Jehu kò yípadà kúrò nínú ẹ̀ṣẹ̀ Jeroboamu ọmọ Nebati, tí ó ṣokùnfà Israẹli láti dá—ti sí sin ẹgbọrọ màlúù wúrà ní Beteli àti Dani.
30 Hina Gode da Yihuma amane sia: i, “Di da Na hamoma: ne hanai huluane A: iha: be egaga fima hamoi dagoi. Amaiba: le, Na da dima dafawane ilegele sia: sa. Digaga fifi misi biyadu amo, ilia da Isala: ili hina bagade hamomu.”
Olúwa sì sọ fún Jehu pé, “Nítorí ìwọ ti ṣe dáradára ní ṣíṣe èyí tí ó tọ́ ní ojú mi, tí o sì ti ṣe sí ilé Ahabu gẹ́gẹ́ bí gbogbo èyí tí ó wà ní ọkàn mi, àwọn ọmọ ọ̀ rẹ yóò jókòó lórí ìtẹ́ Israẹli títí dé ìran kẹrin.”
31 Be Yihiu da dafawanedafa nabasu hou hame hamoi. E da Isala: ili Hina Gode Ea Sema amo noga: le hame hamoi. Be amomane e da Yelouboua: me (amo da Isala: ili fi dunu wadela: le hamoma: ne, oule asi) amo ea hou defele hamoi.
Síbẹ̀ Jehu kò ṣe pẹ̀lẹ́ láti pa òfin Olúwa, Ọlọ́run Israẹli mọ́ pẹ̀lú tọkàntọkàn. Òun kò yípadà kúrò nínú ẹ̀ṣẹ̀ Jeroboamu èyí tí ó ṣokùnfà Israẹli láti dá.
32 Amogalu Hina Gode da muni Isala: ili soge fonoboma: ne hamoi. Silia hina bagade Ha: sa: iele da Isala: ili soge amo da Yodane Hano gusudili diala, ga (south) asili, Aloua moilai (Anone Hano bega: diala) amo huluane hasali. Amo soge ganodini, Gilia: de amola Ba: isia: ne soge dialebe ba: i. Amola amo ganodini, Ga: de fi amola Liubene fi amola Gusu Ma: na: se fi, ilia da amo soge ganodini esalebe ba: i.
Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì, Olúwa ti bẹ̀rẹ̀ sí ní dín iye Israẹli kù. Hasaeli fi agbára jẹ ọba lórí àwọn ọmọ Israẹli ní gbogbo agbègbè wọn.
Ìlà-oòrùn ti Jordani ni gbogbo ilẹ̀ ti Gileadi (ẹ̀kún ilẹ̀ ti ará Gadi, Reubeni, àti Manase) láti Aroeri, tí ó wà létí kòtò Arnoni láti ìhà Gileadi sí Baṣani.
34 Yihiu ea hou eno huluane, amola ea nimi gesa: i hou da “Isala: ili hina bagade Ilia Hamonanu Meloa” amo ganodini dedene legei.
Fún ti òmíràn ti iṣẹ́ ìjọba Jehu, gbogbo ohun tí ó ṣe, gbogbo àṣeyọrí rẹ̀, ṣé a kò kọ wọ́n sí inú ìwé ìtàn ayé àwọn ọba Israẹli?
35 Yihiu da bogole, Samelia moilai bai bagadega uli dogone sali. Egefe Yihouaha: se, da e bagia Isala: ili hina bagade hamoi.
Jehu sinmi pẹ̀lú baba a rẹ̀, a sì sin ín sí Samaria Jehoahasi ọmọ rẹ̀ sì rọ́pò rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọba.
36 Yihiu da Samelia moilai bai bagadega esala, ode 28 agoanega Isala: ili fi ouligilalu.
Àkókò tí Jehu fi jẹ ọba lórí Israẹli ní Samaria jẹ́ ọdún méjìdínlọ́gbọ̀n.

< 2 Hina 10 >