< 2 Hou Olelesu 24 >

1 Youa: sie da lalelegele, ea ode fesu gidigili, Yuda hina bagade hamoi. E da Yelusaleme moilai bai bagade ganodini esala, ode 40 agoanega Yuda fi ouligilalu. Ea ame da Biasiba moilai uda galu, ea dio amo Sibia.
Joaṣi jẹ́ ọmọ ọdún méje nígbà tí ó jẹ ọba, ó sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún ogójì ọdún. Orúkọ ìyá rẹ̀ ni Sibia ti Beerṣeba.
2 Yihoida ea esalusu huluane amo ganodini, Youa: sie da Hina Gode hahawane ba: ma: ne hou hamonanusu. Bai gobele salasu dunu Yihoida da hou noga: idafa ema olelei.
Joaṣi ṣe ohun tí ó dára ní ojú Olúwa ní gbogbo àkókò Jehoiada àlùfáà.
3 Yihoiada da hina bagade Youa: sie idua aduna ilegei. Elama dunu manolali amola uda manolali da lalelegei.
Jehoiada yan ìyàwó méjì fún un, ó sì ní àwọn ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin.
4 Amogalu fa: no, Youa: sie da Debolo Diasu dodoa: musa: dawa: i.
Ní àkókò kan, Joaṣi pinnu láti tún ilé Olúwa ṣe.
5 Youa: sie da gobele salasu dunu amola Lifai fi dunu ili ema misa: ne sia: ne, ilia da Yuda moilai huluane amoga asili, muni amo Debolo Diasu dodoa: musa: lama: ne sia: i. E da ilima hedolo masa: ne sia: i. Be ilia hedolo hame asi.
Ó pe àwọn àlùfáà àti àwọn ará Lefi jọ, ó wí fún wọn pé, “Ẹ lọ sí àwọn ìlú Juda, kí ẹ sì gba owó ìtọ́sí láti ọwọ́ gbogbo Israẹli láti fi tún ilé Ọlọ́run yín ṣe.” Ṣùgbọ́n àwọn ará Lefi kò ṣe é lẹ́ẹ̀kan náà.
6 Amaiba: le, Youa: sie da ilia ouligisu dunu Yihoida ema misa: ne sia: ne, amola ema amane adole ba: i, “Na da Lifai dunuma, ilia da su lasu (da: gisi) amo Hina Gode ea hawa: hamosu dunu Mousese da Hina Gode Ea Abula Diasu ouligima: ne ilegei, amo Yuda amola Yelusaleme fima lama: ne masa: ne sia: i. Ilia hame lala asiba: le, di da abuliba: le amo hou hame ouligibala: ?”
Nítorí náà ọba pa á láṣẹ fún Jehoiada olórí àlùfáà ó sì wí fún un pé, “Kí ni ó dé tí o kò béèrè lọ́wọ́ àwọn ará Lefi láti mú wá láti Juda àti Jerusalẹmu, owó orí tí Mose ìránṣẹ́ Olúwa ti fi lélẹ̀ àti nípasẹ̀ àpéjọ gbogbo Israẹli fún àgọ́ ẹ̀rí?”
7 (Wadela: idafa uda A: dalaia ea fa: no bobogesu dunu da Debolo Diasu wadela: lesi. Ilia da hadigi liligi mogili amo ogogosu ‘gode’ Ba: ilema nodone sia: ne gadomusa: lai.)
Nísinsin yìí, àwọn ọmọkùnrin obìnrin búburú ni Ataliah ti fọ́ ilé Ọlọ́run, ó sì ti lo àwọn nǹkan ìyàsọ́tọ̀ fún àwọn Baali.
8 Amalalu, Yihoida da hamoma: ne sia: beba: le, Lifai fi dunu da gagili hamone, Debolo Diasu logo holeiga ligisi.
Nípasẹ̀ ọba, wọn ṣe àpótí wọ́n sì gbé e sí ìta, ní ẹnu-ọ̀nà ilé Olúwa.
9 Ilia Yelusaleme amola Yuda fi dunu huluanema, ilia da muni amo da Gode Ea hawa: hamosu dunu Mousese da bisili hafoga: i sogega lidili amola lama: ne ilegei, amo defele Hina Godema iamisa: ne sia: si.
A ṣe ìkéde ní Juda àti Jerusalẹmu wí pé wọ́n gbọdọ̀ mú wá fún Olúwa, owó orí tí Mose ìránṣẹ́ Olúwa ti béèrè lọ́wọ́ Israẹli ní aginjù.
10 Dunu amola ilia ouligisu dunu da amo hou hahawane ba: i. Ilia da ilia su (‘da: gisi’) muni gaguli misini, gagili nabalesi.
Gbogbo àwọn ìjòyè àti gbogbo àwọn ènìyàn sì yọ̀, wọ́n sì mú un wá, wọ́n ń jù ú sínú àpótí títí tí ó fi kún.
11 Eso huluane, Lifai dunu da amo gagili ouligisu dunuma gaguli asi. Ilia da amo gagili ganodini muni bagade ba: loba, hina bagade ea sia: dedesu dunu amola Gobele Salasu Hina dunu ea ilegei dunu, ela da misini, muni lidilalu, gagili ea sogebiga bu ligisisu. Amaiba: le, ilia da muni bagade gagadoi.
Nígbàkígbà tí a bá gbé àpótí wọlé láti ọwọ́ àwọn ará Lefi sí ọwọ́ àwọn ìjòyè ọba, tí wọ́n bá sì rí wí pe owó ńlá wà níbẹ̀ àwọn akọ̀wé ọba àti ìjòyè olórí àlùfáà yóò wá láti kó owó rẹ̀ kúrò, wọn yóò sì dá a padà sí ààyè rẹ̀. Wọ́n ṣe èyí déédé, wọ́n sì kó iye owó ńlá.
12 Amalalu, hina bagade amola Yihoiada da amo muni Debolo Diasu hawa: hamosu ouligisu dunu ilima iasu. Amo dunu ilia da diasu gagusu dunu, gele goudasu dunu amola gele dadamusu dunu, ilima iasu. Amola ilia da ifa gaga: i, amola gele gadelale sa: i, amo bu hahamoma: ne, amola eno hawa: hamoma: ne, amo dabe iasu.
Ọba àti Jehoiada fi fún àwọn ọkùnrin náà tí ó sì ń ṣiṣẹ́ nínú ilé Olúwa. Wọ́n fi owó gba ẹni tí ń fi òkúta mọ ilé àti àwọn gbẹ́nàgbẹ́nà láti kọ́ ilé Olúwa padà, àti àwọn òṣìṣẹ́ pẹ̀lú irin àti idẹ láti tún ilé Olúwa ṣe.
13 Ilia huluane gasa fili, hawa: hamone, Debolo Diasu da bu hahamoi dagoi ba: i. Debolo Diasu da ea musa: gasa bagade gagui hou bu ba: i.
Bẹ́ẹ̀ ni àwọn tí ó ń ṣiṣẹ́ náà, sì lọ síwájú àti síwájú ní ọwọ́ wọn, wọ́n sì tún mú ilé Ọlọ́run dúró sí ipò rẹ̀, wọ́n mú un le.
14 Debolo Diasu dodoa: su da hamoi dagoloba, muni dialu ilia da hina bagade amola Yihoiada elama i. Amo muniga ela da silifa ofodo, dalabede, gamali gesosu liligi, amola eno silifa o gouli liligi huluane, amo hahamomusa: ilegei. Yihoiada da esaloba, ilia da Debolo Diasuga gobele salasu hou gebewane hamonanu.
Nígbà tí wọ́n sì parí rẹ̀ tán, wọ́n mú owó ìyókù wá sí iwájú ọba àti Jehoiada, a sì fi ohun èlò fún ilé Olúwa, àní ohun èlò fún ìsìn àti fún ẹbọ pẹ̀lú ọpọ́n, àní ohun èlò wúrà àti fàdákà. Wọ́n sì ń rú ẹbọ sísun ní ilé Olúwa nígbà gbogbo ní gbogbo ọjọ́ Jehoiada.
15 E da da: idafa hamone, ode 130 agoane gidigiloba, e da bogoi.
Ṣùgbọ́n Jehoiada di arúgbó, ó sì kún fún ọjọ́, ó sì kú, ẹni àádóje ọdún ni nígbà tí ó kú.
16 E da Isala: ili dunu fi amola Debolo Diasu hou noga: le fidi amola Gode Ea hawa: hamosu noga: le hamoi. Amo dawa: le, ilia da ea da: i hodo amo hina bagade gele gelabo Da: ibidi Moilai bai bagadega, amo ganodini sali.
Wọ́n sì sin ín ní ìlú Dafidi pẹ̀lú àwọn ọba, nítorí tí ó ṣe rere ní Israẹli, àti sí Ọlọ́run àti sí ilé rẹ̀.
17 Be Yihoiada da bogoloba, amogalu Yuda ouligisu dunu da Youa: sie ilia fada: i sia: fa: no bobogemusa: fuligala: i.
Lẹ́yìn ikú Jehoiada, àwọn oníṣẹ́ Juda wá láti fi ìforíbalẹ̀ wọn hàn sí ọba. Ó sì fèsì sí wọn.
18 Amaiba: le, Yuda dunu da Debolo Diasu ganodini, ilia aowalalia Hina Godema nodone sia: ne gadosu hou fisiagale, ogogosu loboga hamoi ‘gode’ amola wadela: i uda ‘gode’ Asila agoai loboga hamoi liligi ilima muni nodone sia: ne gadosu hou hamosu. Ilia da amo wadela: i hou hamobeba: le, Hina Gode Ea ougi hou da Yuda amola Yelusaleme fi ilima doaga: i.
Wọ́n pa ilé Olúwa tì, Ọlọ́run baba a wọn. Wọ́n sì ń sin àwọn ère Aṣerah àti àwọn òrìṣà. Nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wọn yìí, ìbínú Ọlọ́run dé sórí Juda àti Jerusalẹmu.
19 Hina Gode da ilima balofede dunu, ili Ema sinidigima: ne sisasu ima: ne asunasi. Be ilia da amo sisasu hame nabi.
Bí ó ti wù kí ó rí, Olúwa rán àwọn wòlíì sí àwọn ènìyàn láti mú wọn padà sí ọ̀dọ̀ rẹ̀. Bí ó tilẹ̀ jẹ́ wí pé, wọ́n jẹ́rìí nípa wọn, wọn kì yóò gbọ́.
20 Amalalu, Hina Gode Ea A: silibu Hadigidafa da Segalaia (gobele salasu dunu Yihoiada egefe) amoga aligila sa: i. E da dunu huluane ilia midadi lelu, amane sia: i, “Hina Gode da amane sia: sa, ‘Dilia abuliba: le Hina Gode Ea hamoma: ne sia: i hame naba? Dilia da didili hame hamomu. Dilia da Hina Gode fisiagaiba: le, E amola da dili fisiagai dagoi.’”
Nígbà náà, Ẹ̀mí Ọlọ́run wá sórí Sekariah ọmọ Jehoiada wòlíì, ó dúró níwájú àwọn ènìyàn ó sì wí pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa wí: ‘Kí ni ó dé tí ẹ̀yin kò fi tẹ̀lé àṣẹ Olúwa? Ìwọ kì yóò ṣe rere. Nítorí tí ìwọ ti kọ Olúwa sílẹ̀, òun pẹ̀lú ti kọ̀ yín sílẹ̀.’”
21 Hina bagade Youa: sie da eno dunu gilisili, Segalaia fane legemusa: ilegei. Hina bagade da sia: beba: le, Yuda fi dunu da Hina Gode Ea Debolo Diasu gagoi ganodini, Segalaia igiga gala: le, medole legei dagoi.
Ṣùgbọ́n wọ́n dìtẹ̀ sí i, àti nípa àṣẹ ọba, wọ́n sọ ọ́ lókùúta pa nínú àgbàlá ààfin ilé Olúwa.
22 Youa: sie da Segalaia eda Yihoiada ema mae fisili noga: le hawa: hamoi amo gogolei. Amola ea sia: beba: le, ilia Segalaia medole legei. Segalaia da bogolaloba, e amane wele sia: i, “Hina Gode da dia hamobe ba: ma: mu amola dima se iasu imunu da defea!”
Ọba Joaṣi kò rántí inú rere tí Jehoiada baba Sakariah ti fihàn án ṣùgbọ́n, ó pa ọmọ rẹ̀, tí ó wí bí ó ti ń kú lọ pé, “Kí Olúwa kí ó rí èyí kí ó sì pè ọ́ sí ìṣirò.”
23 Amo ode dogoa, Silia dadi gagui wa: i da Yuda amola Yelusaleme fi doagala: i. Ilia da ouligisu dunu huluane medole legei amola liligi bagohamedafa susuguli, Dama: sagase moilai bai bagadega gaguli asi.
Ní òpin ọdún, àwọn ọmọ-ogun Aramu yàn láti dojúkọ Joaṣi; wọ́n gbógun ti Juda àti Jerusalẹmu, wọ́n sì pa gbogbo àwọn aṣáájú àwọn ènìyàn. Wọ́n rán gbogbo àwọn ìkógun sí ọba wọn ní Damasku.
24 Silia dadi gagui wa: i da fonobahadi fawane, be Hina Gode da ili fidibiba: le, ilia da Yuda fi dadi gagui wa: i bagadedafa amo hasali dagoi. Bai Yuda fi dunu da ilia aowalalia Hina Gode fisiagai dagoi. Hina bagade Youa: sie da agoane se iasu lai.
Bí ó ti wù kí ó rí, àwọn ọmọ-ogun Aramu ti wá pẹ̀lú àwọn ọkùnrin díẹ̀ Olúwa sì fi ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ-ogun lé wọn lọ́wọ́, nítorí tí Juda ti kọ Olúwa Ọlọ́run àwọn baba wọn sílẹ̀. Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì ṣe ìdájọ́ Joaṣi.
25 E da bagade fafa: ginisi ba: i. Amola ha lai dunu da ilia sogega bu ahoanoba, eagene ouligisu dunu aduna da ilegele, ea debea da: iya esala, e medole legei. Ela da gobele salasu dunu Yihoiada ea mano fasu dabe ima: ne e fane legei. Ilia da ea da: i hodo amo Da: ibidi Moilai bai bagadega ulidogone sali. Be hina bagade ilia bogoi gele gelabo ganodini hame sali.
Nígbà tí àwọn ará Aramu kúrò, wọ́n fi Joaṣi sílẹ̀ pẹ̀lú ọ̀pọ̀ ọgbẹ́. Àwọn oníṣẹ́ rẹ̀ dìtẹ̀ si fún pípa ọmọ Jehoiada àlùfáà, wọ́n sì pa á ní orí ibùsùn rẹ̀. Bẹ́ẹ̀ ó sì kú, a sì sin ín sínú ìlú ńlá ti Dafidi, ṣùgbọ́n kì í ṣe nínú àwọn ibojì àwọn ọba.
26 (Dunu amo da ilegele e medole legei, elea dio da Sa: iba: de amola Yihosaba: de. Sa: iba: de da A: mone fi uda ea dio amo Simia: de amo egefe galu, amola Yihosaba: de da Moua: be fi uda ea dio amo Similidi amo egefe galu.)
Àwọn tí ó dìtẹ̀ sì jẹ́ Sabadi, ọmọ Ṣimeati arábìnrin Ammoni àti Jehosabadi ọmọ Ṣimiriti arábìnrin Moabu.
27 Youa: sie egefelalia hou, amola balofede dunu ema gagabosu ba: la: lusu, amola ea Debolo Diasu dodoa: su hou, amo huluane da “Hina bagade buga Dedei ea Bai Olelesu Meloa” amo ganodini dedene legei. Youa: sie egefe A: masaia da e bagia Yuda hina bagade hamoi.
Àkọsílẹ̀ àwọn ọmọ rẹ̀, àwọn ọ̀pọ̀lọpọ̀ àsọtẹ́lẹ̀ nípa rẹ̀, àti àkọsílẹ̀ ti ìmúpadà sípò ilé Ọlọ́run ní a kọ sínú ìwé ìtumọ̀ ti àwọn ọba. Amasiah ọmọ rẹ̀ sì rọ́pò rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọba.

< 2 Hou Olelesu 24 >