< 2 Hou Olelesu 12 >

1 Lihouboua: me da gasa fili, ea ouligisu hou didili lalegagui dagoloba, e amola ea fi dunu da hedolowane, Hina Gode Ea Sema yolesiagai.
Lẹ́yìn ìgbà tí a fi ìjọba Rehoboamu múlẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọba, tí ó sì ti di alágbára, òun àti gbogbo Israẹli, pẹ̀lú rẹ̀ ni wọ́n pa òfin Olúwa tì.
2 Ilia da Hina Godema baligi fa: iba: le, Lihouboua: me ea ouligibi ode bi amoga, ilia da se iasu ba: i. Idibidi hina bagade Siaisia: ge da Yelusaleme doagala: i.
Nítorí tí wọn kò ṣọ òtítọ́ sí Olúwa. Ṣiṣaki ọba Ejibiti dojúkọ Jerusalẹmu ní ọdún karùn-ún ti ọba Rehoboamu.
3 Siaisia: ge ea dadi gagui wa: i da sa: liode 1,200 agoane, hosiga fila heda: i dadi gagui dunu 60,000 agoane amola dadi gagui dunu eno idimu hame gala. Ea dadi gagui dunu mogili da Libia, Sagimi amola Idioubia sogega misi.
Pẹ̀lú ẹgbàá mẹ́fà kẹ̀kẹ́ àti ọ̀kẹ́ mẹ́ta àwọn ọkùnrin ẹlẹ́ṣin àti àìníye ọ̀wọ́ ogun ti Libia, Sukki àti Kuṣi, tí ó wà pẹ̀lú rẹ̀ láti Ejibiti.
4 E da Yuda gagili sali moilai bai bagade huluane susuguli, mogodigili ahoana, Yelusalemega doaga: i.
Ó fi agbára mú àwọn ìlú ààbò ti Juda, pẹ̀lú wá sí Jerusalẹmu bí ó ti jìnnà tó.
5 Balofede dunu Siema: ia da hina bagade Lihouboua: me amola Yuda ouligisu dunu (ili huluane da Siaisia: gema beda: iba: le, Yelusaleme ganodini gilisili esalebe ba: i) ilima asili, amane sia: i, “Hina Gode da dilima amane sia: ne iaha, ‘Dilia da Na fisiagaiba: le, Na da Siaisia: ge amo ea dili hasalima: ne, fisiagai dagoi.’”
Nígbà náà, wòlíì Ṣemaiah wá sí ọ̀dọ̀ Rehoboamu àti sí ọ̀dọ̀ àwọn olórí Juda tí wọ́n ti péjọ ní Jerusalẹmu nítorí ìbẹ̀rù Ṣiṣaki, ó sì wí fún wọn pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa wí: ìwọ ti pa mí tì; nítorí náà èmi náà ti pa yín tì sí ọ̀dọ̀ Ṣiṣaki.”
6 Lihouboua: me amola Yuda ouligisu dunu da ilia wadela: i hou gogosiane fofada: i. Ilia amane sia: i, “Dafawane! Hina Gode Ea wali hamobe da moloidafa.”
Àwọn olórí Israẹli àti ọba rẹ̀ ará wọn sílẹ̀, wọ́n sì wí pé, “Olódodo ni Olúwa.”
7 Hina Gode da amo ba: beba: le, bu Siema: iama amane sia: i, “Ilia da ilia wadela: i hou gogosiane fofada: iba: le, Na da ili hame gugunufinisimu. Be Siaisia: ge da ili doagala: sea, ilia da gugunufinisidafa hame ba: mu. Na ougidafa hou da Yelusalemema hame doaga: mu.
Nígbà tí Olúwa rí i pé, wọ́n ti rẹ̀ ara wọn sílẹ̀ ọ̀rọ̀ Olúwa yí tọ Ṣemaiah lọ pé, “Níwọ́n ìgbà tí wọ́n ti rẹ ara wọn sílẹ̀, Èmi kì yóò pa wọ́n ṣùgbọ́n, yóò fún wọn ní ìtúsílẹ̀ tó bá yá. Ìbínú mi kì yóò dà sórí Jerusalẹmu ní ipasẹ̀ Ṣiṣaki.
8 Be Siaisia: ge da ili hasalimu. Nama hawa: hamosu hou amola osobo bagade ouligisu dunuma hawa: hamosu hou da hisu. Amo ilia da dawa: mu.”
Bí ó ti wù kí ó rí, wọn yóò sìn ní abẹ́ rẹ̀, kí wọn kí ó lè mọ̀ ìyàtọ̀ láàrín sí sìn mí àti sí sin àwọn ọba ilẹ̀ mìíràn.”
9 Hina bagade Siaisia: ge da Yelusalemega misini, e da Debolo Diasua amola hina bagade diasua, noga: i liligi huluane susugui. E da huluanedafa susugui dagoi, amola gouliga hamoi da: igene ga: su, Soloumane ea hamoi liligi, amo huluane susugui.
Nígbà tí Ṣiṣaki ọba Ejibiti dojúkọ Jerusalẹmu, ó gbé àwọn ìṣúra ilé Olúwa, àti àwọn ìṣúra ààfin ọba. Ó gbé gbogbo rẹ̀, pẹ̀lú àwọn àpáta wúrà tí Solomoni dá.
10 Amo buga: ma: ne, Lihouboua: me da eno da: igene ga: su, balasega hamoi. E da amo ouligima: ne, logo ga: su sosodo aligisu dunu ilegei.
Bẹ́ẹ̀ ni, ọba Rehoboamu dá àwọn àpáta idẹ láti fi dípò wọn, ó sì fi èyí lé àwọn alákòóso àti olùṣọ́ tí ó wà ní ẹnu iṣẹ́ ní àbáwọlé ẹnu-ọ̀nà ààfin ọba lọ́wọ́.
11 Eso huluane, Lihouboua: me da Debolo Diasuga ahoasu, sosodo aligisu dunu da da: igene ga: su gaguli ahoasu. Amalu, ilia da bu sosodo aligisu sesei ganodini ligisisu.
Ìgbàkígbà tí ọba bá lọ sí ilé Olúwa, àwọn olùṣọ́ n lọ pẹ̀lú rẹ̀, wọ́n ń gbé àwọn àpáta náà àti lẹ́yìn, wọ́n dá wọn padà sí yàrá ìṣọ́.
12 E da Hina Gode Ea se iasu hame hihiba: le, Hina Gode da e dafawanedafa hame gugunufinisi. Amola Yuda fi da bu hahawane ba: i.
Nítorí ti Rehoboamu rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀, ìbínú Olúwa yí padà kúrò lórí rẹ̀, a kò sì pa á run pátápátá. Nítòótọ́, ìre díẹ̀ wà ní Juda.
13 Lihouboua: me da Yelusalemega esala, ea ouligisu hou hamosu. Ea gasa da bu heda: i. E da lalelegele, ode 45 esalu, Yuda fima ouligisu hou mui, amola e da Yelusalemega esala, ode 17 agoane Yuda fi ouligisu. (Hina Gode da Isala: ili soge ganodini, Ema nodone sia: ne gadosu sogebi, Yelusaleme moilai bai bagade, amo fawane ilegei.) Lihouboua: me ea ame da Na: ima. Na: ima da A: mounaide uda.
Ọba Rehoboamu fi ara rẹ̀ lélẹ̀ gidigidi ní Jerusalẹmu, ó sì tẹ̀síwájú gẹ́gẹ́ bí ọba. Ó jẹ́ ẹni ọdún mọ́kànlélógójì nígbà tí ó di ọba. Ó sì jẹ ọba fún ọdún mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n ní Jerusalẹmu, ìlú ńlá tí Olúwa ti yàn jáde kúrò nínú gbogbo àwọn ẹ̀yà Israẹli ní èyí tí ó fẹ́ fi orúkọ rẹ̀ síbẹ̀. Orúkọ ìyá rẹ̀ ni Naama, ará Ammoni.
14 Lihouboua: me da wadela: le hamosu. Bai e da Hina Gode Ea hanai hou hame hogosu.
O sì ṣe búburú, nítorí tí kò múra nínú ọkàn rẹ̀ láti wá Olúwa.
15 Lihouboua: me ea hou, e da muni hahamona asili dagoi, amola ea sosogo fi ilia hou, amo da “Balofede Dunu Siema: ia ea Hamonanu” meloa dedei amola “Balofede Dunu Idou ea Hamonanu” meloa dedei amo ganodini dedene legei. Lihouboua: me da mae fisili, Yelouboua: mema gegenanu.
Fún tí iṣẹ́ ìjọba Rehoboamu láti ìbẹ̀rẹ̀ dé ìparí, ṣé a kò kọ wọ́n sínú ìwé ìrántí ti Ṣemaiah wòlíì àti ti Iddo, aríran tí ó ní ṣe pẹ̀lú ìtàn ìdílé láti ọ̀dọ̀ àwọn baba ńlá? Ìtẹ̀síwájú ogun jíjà sì wà láàrín Rehoboamu àti Jeroboamu.
16 Lihouboua: me da bogoloba, ilia da ea da: i hodo amo Da: ibidi ea Moilai bai bagadega hina bagade ilia dogonesisu sogebi amoga gele gelaboga sali. Egefe Abaidia da e bagia, Yuda fi dunu ilia hina bagade hamoi.
Rehoboamu sun pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀ a sin ín sínú ìlú ńlá ti Dafidi. Abijah ọmọ rẹ̀ sì rọ́pò rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọba.

< 2 Hou Olelesu 12 >