< 1 Sa:miuele 30 >

1 Eso aduna baligili, Da: ibidi amola ea dunu da Sigela: ge moilai bai bagadega doaga: i. Be A: malege dunu da Yuda ga (south) soge amola Sigela: ge amoga doagala: le, diasu huluane laluga ulagisili nei dagoi, be uda huluane gaguli gagai dagoi ba: i. Ilia da uda amola mano hame fane legei, be yolesili, ilia da huluane oule asi dagoi.
Ó sì ṣe nígbà ti Dafidi àti àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ sì bọ̀ sí Siklagi ní ọjọ́ kẹta, àwọn ará Amaleki sì ti kọlu ìhà gúúsù, àti Siklagi, wọ́n sì ti kùn ún ní iná.
2
Wọ́n sì kó àwọn obìnrin tí ń bẹ nínú rẹ̀ ní ìgbèkùn, wọn kò sì pa ẹnìkan, ọmọdé tàbí àgbà, ṣùgbọ́n wọ́n kó wọn lọ, wọ́n sì bá ọ̀nà tiwọn lọ.
3 Da: ibidi amola ea dunu da doaga: loba, ilia da moilai amo laluga nei amola ilia uda, dunu mano amola uda mano huluane gaguli asi dagoi ba: i.
Dafidi àti àwọn ọmọkùnrin sì wọ ìlú Siklagi, sì wò ó, a ti kùn ún ni iná; àti obìnrin wọn, àti ọmọkùnrin wọn àti ọmọbìnrin wọn ni a kó ni ìgbèkùn lọ.
4 Da: ibidi amola ea dunu da muni hedolo mae yolele dinanawane gasa hamedene goaia: igia: i ba: i.
Dafidi àti àwọn ènìyàn tí ó wà lọ́dọ̀ rẹ̀ sì gbé ohùn wọn sókè, wọ́n sì sọkún títí agbára kò fi sí fún wọn mọ́ láti sọkún.
5 Da: ibidi ea uda aduna (Ahinoume amola A: biga: ile), ela da ele gaguli asi dagoi ba: i.
A sì kó àwọn aya Dafidi méjèèjì nígbèkùn lọ, Ahinoamu ará Jesreeli àti Abigaili aya Nabali ará Karmeli.
6 Bidi hamosu bagadedafa da Da: ibidima doaga: i dagoi. Bai ea dunu da ilia mano fisili gagaiba: le, ilia da baligili da: i dioi galu. Amola ilia Da: ibidi amo igiga fane legemusa: magagi. Da: ibidi da bagadewane da: i dioi, be Hina Gode da ea dogo denesinisi.
Dafidi sì banújẹ́ gidigidi, nítorí pé àwọn ènìyàn náà sì ń sọ̀rọ̀ láti sọ ọ́ lókùúta, nítorí ti inú gbogbo àwọn ènìyàn náà sì bàjẹ́, olúkúlùkù ọkùnrin nítorí ọmọ rẹ̀ ọkùnrin, àti nítorí ọmọ rẹ̀ obìnrin ṣùgbọ́n Dafidi mú ara rẹ̀ lọ́kàn le nínú Olúwa Ọlọ́run rẹ̀.
7 Da: ibidi da gobele salasu dunu Abaia: da (Ahimelege egefe) ema amane sia: i, “‘Ifode’ amo nama gaguli misa!” Abaia: da da amo ema gaguli misi.
Dafidi sì wí fún Abiatari àlùfáà, ọmọ Ahimeleki pé, èmí bẹ̀ ọ́, mú efodu fún mi wá níhìn-ín yìí. Abiatari sì mú efodu náà wá fún Dafidi.
8 Da: ibidi da Hina Godema amane adole ba: i, “Na da amo ha wa: i dunuma fa: no bobogela: dula: ? Amola na da ili baligiama: bela: ?” Hina Gode da bu adole i, “Ilima fa: no bobogema! Dia da ili baligiamu, amola ili huluane gagulaligili bu sasamogemu.”
Dafidi sì béèrè lọ́dọ̀ Olúwa wí pé, “Kí èmi ó lépa ogun yìí bi? Èmi lè bá wọn?” Ó sì dá a lóhùn pé, “Lépa, nítorí pé ni bíbá ìwọ yóò bá wọn, ni gbígbà ìwọ yóò sì rí wọn gbà.”
9 Amaiba: le, Da: ibidi amola ea dunu 600 agoane da muni asili, Biso Hano amoga doaga: le, ea dunu mogili da amogawi ouesalu.
Bẹ́ẹ̀ ni Dafidi àti ẹgbẹ̀ta ọmọkùnrin tí ń bẹ lọ́dọ̀ rẹ̀ sì wá sí ibi àfonífojì Besori, apá kan sì dúró.
10 Da: ibidi amola ea dunu 400 agoane da gebewane ahoanu. Be mogi 200 eno da helebeba: le, hano degemu hamedei ba: i. Amaiba: le, ilia da amogawi ouesalu.
Ṣùgbọ́n Dafidi àti irinwó ọmọkùnrin lépa wọn: igba ènìyàn tí àárẹ̀ mú, tiwọn kò lè kọjá odò Besori sì dúró lẹ́yìn.
11 Da: ibidi ea dunu da Idibidi goi sogega esalebe ba: i. Ilia da e amo Da: ibidima oule asi. Ilia da ema ha: i manu amola hano i.
Wọ́n sì rí ará Ejibiti kan ní oko, wọ́n sì mú un tọ Dafidi wá, wọ́n sì fún un ní oúnjẹ, ó sì jẹ; wọ́n sì fún un ní omi mu.
12 Ilia da figi ifa fage hafoga: i amola waini fage hafoga: i gagabu aduna igili i. Be e da eso udiana ha: i hame mai galuba: le, e da amo ha: i manu i, amo nanoba ea gasa da bu denesi dagoi ba: i.
Wọ́n sì fún un ní àkàrà, èso ọ̀pọ̀tọ́ àti síírí àjàrà gbígbẹ́ méjì: nígbà tí ó sì jẹ ẹ́ tán, ẹ̀mí rẹ̀ sì sọjí: nítorí pé kò jẹ oúnjẹ, bẹ́ẹ̀ ni kò sì mu omi ní ọjọ́ mẹ́ta ní ọ̀sán, àti ní òru.
13 Da: ibidi da ema amane adole ba: i, “Dia hina da nowala: ? Amola di da habidili misibala: ?” E bu adole i, “Na da Idibidi dunu, amola na da A: malege dunu afae ea udigili hawa: hamosu dunu. Na da oloiba: le, eso udiana baligili, na hina da na yolesiagai.
Dafidi sì bi í léèrè pé, “Ọmọ ta ni ìwọ? Àti níbo ni ìwọ ti wá?” Òun sì wí pé, “Ọmọ ará Ejibiti ni èmi, ọmọ ọ̀dọ̀ ọkùnrin kan ará Amaleki. Olúwa mi fi mí sílẹ̀, nítorí pé láti ọjọ́ mẹ́ta ni èmi ti ṣe àìsàn.
14 Amo esoha, ninia da Gelediaide dunu ilia soge (Ga: ilebe fi ilia soge, Yuda ga [south] la: idiga gala) amoga ha wa: i ahoana, Sigela: ge moilai bai bagade amo laluga ulagi.”
Àwa sì gbé ogun lọ sí ìhà gúúsù tí ará Kereti, àti sí ìhà ti Juda, àti sí ìhà gúúsù ti Kalebu; àwa sì kun Siklagi ní iná.”
15 Da: ibidi da ema adole ba: i, “Di da na oule amo ha wa: i dunu asi amo olela masa: bela: ?” Idibidi goi da bu adole i, “Di da Gode Ea Dioba: le na mae fane legele amola na hina ema bu hame imunu ilegele sia: sea, na da bisili dili oule olela masunu.”
Dafidi sì bi í léèrè pé, “Ìwọ lè mú mí sọ̀kalẹ̀ tọ ẹgbẹ́ ogun yìí lọ bí?” Òun sì wí pé, “Fi Ọlọ́run búra fún mi pé, ìwọ kì yóò pa mí, bẹ́ẹ̀ ni ìwọ kì yóò sì fi mi lé olúwa mi lọ́wọ́; èmi yóò sì mú ọ sọ̀kalẹ̀ tọ ẹgbẹ́ ogun náà lọ.”
16 Amalalu, e da Da: ibidi bisili ilima oule asi. A: malege ha wa: i ahoasu dunu da sogebi bagade amo ganodini ha: i naha amola adini naha amola hahawane hamosa afagogoi ba: i. Bai ilia da liligi bagadedafa Filisidini soge amola Yuda soge amoga lai dagoiba: le.
Ó sì mú un sọ̀kalẹ̀, sì wò ó, wọ́n sì tàn ká ilẹ̀, wọ́n ń jẹ, wọ́n ń mu, wọ́n sì ń jó, nítorí ìkógun púpọ̀ tí wọ́n kó láti ilẹ̀ àwọn Filistini wá, àti láti ilẹ̀ Juda.
17 Aya hahabe, eso mabe galu, Da: ibidi da ili doagala: le, ilima gegenana, daeya doaga: i. A: malege goi 400 agoane da ga: mele da: iya fila heda: le, hobea: iba: le, gaga: i dagoi ba: i. Be eno huluane, Da: ibidi amola ea dunu ilia da fane lelegei.
Dafidi sì pa wọ́n láti àfẹ̀mọ́júmọ́ títí ó fi di àṣálẹ́ ọjọ́ kejì: kò sí ẹnìkan tí ó là nínú wọn, bí kọ̀ ṣe irinwó ọmọkùnrin tí wọ́n gun ìbákasẹ tí wọ́n sì sá.
18 Da: ibidi da uda, mano amola liligi huluane amo A: malege dunu ilia lai, amo hulu samogei. Ea uda aduna amola da hi samogei.
Dafidi sì gbà gbogbo nǹkan tí àwọn ará Amaleki ti kó: Dafidi sì gba àwọn obìnrin rẹ̀ méjèèjì.
19 Liligi afae bu hame samogei da hamedafa ba: i. Da: ibidi da ea dunu ilia dunu mano, uda mano amola liligi A: malege dunu ilia lai, amo huluanedafa bu samogei.
Kò sì ṣí nǹkan tí ó kù fún wọn, kékeré tàbí ńlá, ọmọkùnrin tàbí ọmọbìnrin, tàbí ìkógun, tàbí gbogbo nǹkan tí wọ́n ti kó: Dafidi sì gba gbogbo wọn.
20 E da lai ohe wa: i amola huluane bu samogei. Ea dunu da amo ohe wa: i bisilisili sesesela asi. Ilia da amane sia: i, “Amo liligi huluane da Da: ibidi ea: !”
Dafidi sì kó gbogbo àgùntàn, àti màlúù tí àwọn ènìyàn rẹ̀ dà ṣáájú àwọn ẹran ọ̀sìn mìíràn tí wọ́n gbà, wọ́n sì wí pé, “Èyí yìí ni ìkógun ti Dafidi.”
21 Amalalu, Da: ibidi da dunu 200 amo da helebeba: le, mae gegena asili, Biso Hano bega: esafulu, ilima buhagi. Ilia da Da: ibidi amola ea dunu gousa: musa: misi, amola Da: ibidi da ilima asili, hahawane yosia: i.
Dafidi sì wá sọ́dọ̀ igba ọkùnrin tí àárẹ̀ ti mú jú, tiwọn kò lè tọ́ Dafidi lẹ́yìn mọ́, ti òun ti fi sílẹ̀, ni àfonífojì Besori: wọ́n sì lọ pàdé Dafidi, àti láti pàdé àwọn ènìyàn tí ó lọ pẹ̀lú rẹ̀: Dafidi sì pàdé àwọn ènìyàn náà, ó sì kí wọn.
22 Be ea dunu mogili, hedolo mi hahanabe amola hamedei dunu, da Da: ibidima amane sia: i, “Amo dunu 200 da nini hame asiba: le, ninia da ilima liligi lai hame ima: mu. Ilia da ilia uda amola mano amo fawane lale masa: ne sia: ma.”
Gbogbo àwọn ènìyàn búburú àti àwọn ọmọ Beliali nínú àwọn tí o bá Dafidi lọ sì dáhùn, wọ́n sì wí pé, “Bí wọn kò ti bá wa lọ, àwa ki yóò fi nǹkan kan fún wọn nínú ìkógun ti àwa rí gbà bí kò ṣe obìnrin olúkúlùkù wọn, àti ọmọ wọn; ki wọn sì mú wọn, ki wọn sì máa lọ.”
23 Be Da: ibidi da bu adole i, “Nolalali dilia: ! Hina Gode da amo liligi ninima ia dagoiba: le, dilia sia: i defele hamomu da hamedei. E da nini gaga: i, amola ninia ha wa: i ahoabe dunu amo hasalasima: ne hamoi dagoi.
Dafidi sì wí pé, “Ẹ má ṣe bẹ́ẹ̀, ẹ̀yin ara mi: Olúwa ni ó fi nǹkan yìí fún wa, òun ni ó sì pa wá mọ́, òun ni ó sì fi ẹgbẹ́ ogun ti ó dìde sí wa lé wa lọ́wọ́.
24 Nowa da dilia sia: nabima: bela: ? Dunu huluane da liligi defele lamu. Nowa da ninia liligi ouligili esalu galea, ilia da gegena ahoasu dunu ilia labe defele lamu.”
Ta ni yóò gbọ́ tiyín nínú ọ̀ràn yìí? Ṣùgbọ́n bi ìpín ẹni tí ó sọ̀kalẹ̀ lọ si ìjà ti rí, bẹ́ẹ̀ ni ìpín ẹni ti ó dúró ti ẹrù; wọn ó sì pín in bákan náà.”
25 Da: ibidi da amo hou Isala: ili soge ganodini sema dialoma: ne sia: i. Amola amogainini amo sema da Isala: ili sogega diala.
Láti ọjọ́ náà lọ, ó sì pàṣẹ, ó sì sọ ọ di òfin fún Israẹli títí di òní yìí.
26 Da: ibidi da Sigela: ge amoga bu misini, e da ea lai liligi mogili amo ea sama Yuda ouligisu dunu ilima i. E da ilima amane sia: si, “Amo da dilima hahawane udigili iasu liligi. Ninia da amo Hina Gode Ea ha lai ilima lai.”
Dafidi sì padà sí Siklagi, ó sì rán nínú ìkógun náà si àwọn àgbàgbà Juda, àti sí àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀, ó sì wí pé, “Wò ó, èyí ni ẹ̀bùn fún un yín, láti inú ìkógun àwọn ọ̀tá Olúwa wa.”
27 E da amo liligi Bedele dunu amola La: ima (Yuda ga [south] sogega diala) amo dunu, amola Ya: da, Aloua, Sifemode, Esiedemoua, Lagale, Homa, Bolasia: ne, A:ida: ge amola Hibalone amo moilai dunuma i. Amola e da Yilamiele fi dunu amola Ginaide fi dunu amolalima i. E da sogebi amoga e amola ea dunu ilia afufulalusu, ilima I.
Ó sì rán an sí àwọn tí ó wà ni Beteli àti sí àwọn tí ó wà ní gúúsù tí Ramoti, àti sí àwọn tí ó wà ní Jattiri.
Àti sí àwọn tí ó wà ní Aroeri, àti sí àwọn tí ó wà ní Sifimoti, àti sí àwọn tí ó wà ni Eṣitemoa.
Àti si àwọn tí ó wà ni Rakeli, àti sí àwọn tí ó wà ní ìlú àwọn Jerahmeeli, àti sí àwọn tí ó wà ni ìlú àwọn ará Keni,
àti sí àwọn tí ó wà ni Horma, àti sí àwọn ti ó wà ní Bori-Aṣani, àti sí àwọn tí ó wà ni Ataki.
Àti àwọn tí ó wà ni Hebroni, àti sí gbogbo àwọn ìlú ti Dafidi tìkára rẹ̀ àti tí àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ máa ń rìn ká.

< 1 Sa:miuele 30 >