< 1 Sa:miuele 3 >

1 Amo eso galu, goihadi Sa: miuele da Ilai hi olelelaleamusu e da Hina Gode Ea hawa: hamosu. Amo esoha, Hina Gode da Ea fi dunuma bagade hame sia: i. Amola esala ba: su bagahamedafa ba: i.
Samuẹli ọmọkùnrin náà ṣe òjíṣẹ́ níwájú Olúwa ní abẹ́ Eli. Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì ọ̀rọ̀ Olúwa ṣọ̀wọ́n: kò sì sí ìran púpọ̀.
2 Ilai ea si da gadenenewane dofoi dagoi ba: i. Gasi afaega e da hina: seseiga golai dialu.
Ní alẹ́ ọjọ́ kan Eli ẹni tí ojú rẹ̀ ti bẹ̀rẹ̀ sí di aláìlágbára, tí kò sì ríran dáradára, ó dùbúlẹ̀ ní ipò rẹ̀ bi ti àtẹ̀yìnwá.
3 Sa: miuele da Gode Ea diasu (amo ganodini da Gode Ea Sema Gousa: su Gagili galu) amo ganodini golai dialu. Hehebolo mabe galu, gamali da nenanobawane,
Nígbà tí iná kò tí ì kú Samuẹli dùbúlẹ̀ nínú tẹmpili Olúwa, níbi tí àpótí Olúwa gbé wà.
4 Hina Gode da Sa: miuelema wele sia: i. E da bu adole i, “Wae!”
Nígbà náà ni Olúwa pe Samuẹli. Samuẹli sì dáhùn, “Èmi nìyí.”
5 Amalu, e da Ilaima hehenaiya asili, ema adole ba: i, “Dia na wele sia: i amo na da wea!” Be Ilai da bu adole i, “Na da di hame wele sia: i. Di bu golala masa.” Amane sia: beba: le, Sa: miuele da bu golala asi.
Ó sì sáré lọ sí ọ̀dọ̀ Eli ó sì wí pé, “Èmi nìyí nítorí pé ìwọ pè mí.” Ṣùgbọ́n Eli wí fún un pé, “Èmi kò pè ọ́; padà lọ dùbúlẹ̀.” Nítorí náà ó lọ ó sì lọ dùbúlẹ̀.
6
Olúwa sì tún pè é, “Samuẹli!” Samuẹli tún dìde ó tọ Eli lọ, ó sì wí pé, “Èmi nìyìí, nítorí tí ìwọ pè mí.” “Ọmọ mi, èmi kò pè ọ́, padà lọ dùbúlẹ̀.”
7 Hina Gode da Sa: miuelema bu eno wele sia: i. Be Sa: miuele da amo da Hina Gode Ea wele sia: sayale hame dawa: i. Bai Hina Gode da musa: ema afae hame sia: su. Amaiba: le, e da wa: legadole, Ilaima asili, amane sia: i, “Dia na wele sia: i amo na da wea.” Be Ilai da bu adole i, “Nagofe! Di na hame wele sia: i. Bu golala masa.”
Ní àkókò yìí Samuẹli kò tí ì mọ̀ Olúwa: bẹ́ẹ̀ ni a kò sì tí ì fi ọ̀rọ̀ Olúwa hàn án.
8 Hina Gode da Sa: miuelema bu osoda wele sia: i. Amaiba: le, e da wa: legadole, Ilaima asili, amane sia: i, “Dia na wele sia: i amo na da wea.” Amalalu, Ilai da Hina Gode da Sa: miuelema wele sia: sa galebeya dawa: digi.
Olúwa pe Samuẹli ní ìgbà kẹta, Samuẹli sì tún dìde, ó sì lọ sọ́dọ̀ Eli ó sì wí pé, “Èmi nìyìí; nítorí tí ìwọ pè mí.” Nígbà náà ni Eli wá mọ̀ pé Olúwa ni ó ń pe ọmọ náà.
9 Amaiba: le, e da Sa: miuelema amane sia: i, “Di bu golala masa. Be Hina Gode da dima bu wele sia: sea, amane sia: ma, “Hina Gode! Dia sia: ma! Dia hawa: hamosu dunu na da Dia sia: lalabolalebe wea.” Amalu Sa: miuele da bu golala asi.
Nítorí náà Eli sọ fún Samuẹli, “Lọ kí o lọ dùbúlẹ̀. Tí o bá sì pè ọ́, sọ wí pé, ‘Máa wí, Olúwa nítorí tí ìránṣẹ́ rẹ ń gbọ́.’” Bẹ́ẹ̀ ni Samuẹli lọ, ó sì lọ dùbúlẹ̀ ní ààyè rẹ̀.
10 Hina Gode da bu misini, lelu. Hi musa: wele sia: i amanewane Sa: miuelema bu wele sia: i. “Sa: miuele! Sa: miuele!” Amalalu Sa: miuele da bu adole i, “Hina Gode! Dia sia: ma! Dia hawa: hamosu dunu da Dia sia: lalabolalebe wea.”
Olúwa wá, ó sì dúró níbẹ̀, ó pè é bí ó ṣe pè é ní ìgbà tí ó kọjá, “Samuẹli! Samuẹli!” Nígbà náà ni Samuẹli dáhùn pé, “Máa wí nítorí tí ìránṣẹ́ rẹ ń gbọ́.”
11 Hina Gode da ema amane sia: i, “Eso afaega, Na da Isala: ili dunu fi ilima se dabe baligili imunu. Dunu huluane da amo hou nababeba: le, dogo giolasimu.
Olúwa sọ fún Samuẹli pé, “Wò ó, èmi ṣetán láti ṣe ohun kan ní Israẹli tí yóò jẹ́ kí etí gbogbo ènìyàn tí ó gbọ́ ọ já gooro.
12 Amo esohaga, Na da Ilai ea sosogo fi ilima gagabusu aligima: ne sia: i, amo huluanedafa hamomu.
Ní ìgbà náà ni èmi yóò mú ohun gbogbo tí mo ti sọ sí ilé Eli ṣẹ láti ìbẹ̀rẹ̀ dé òpin.
13 Na da Ilaima adoi dagoi, Na da ea sosogo fi ilima mae yolele se dabe dafawane gebe ianumu. Bai ea mano da Nama lasogole sia: i. Ilai da amo wadela: i hou hamobe dawa: i galu, be logo hame hedofasu.
Nítorí èmi sọ fún un pé, Èmi yóò ṣe ìdájọ́ fún ilé rẹ̀ títí láé nítorí ìwà ẹ̀ṣẹ̀ wọn tí òun mọ̀ nípa rẹ̀ nítorí àwọn ọmọ rẹ̀ sọ ọ̀rọ̀-òdì, òun kò sì dá wọn lẹ́kun.
14 Amaiba: le Na da Ilai ea sosogo fi ilima dafawanedafa amane sia: sa. Gobele salasu huluane amola udigili iasu huluane da amo wadela: idafa hou gogolema: ne olofomusa: defele hame ba: mu. Ilia da Na se dabe iasu fawane ba: mu.”
Nítorí náà, mo búra sí ilé Eli, ‘Ìwà ẹ̀ṣẹ̀ ilé Eli ni a kì yóò fi ẹbọ tàbí ọrẹ mú kúrò láéláé.’”
15 Sa: miuele da golai dialobawane soge hadigi ba: i. Amalalu, e da wa: legadole, Hina Gode Ea diasu logo dui. E da ea ba: i liligi Ilaima adomu beda: i galu.
Samuẹli dùbúlẹ̀ títí di òwúrọ̀ nígbà náà ó sì ṣí ìlẹ̀kùn ilé Olúwa, ó sì bẹ̀rù láti sọ ìran náà fún Eli.
16 Ilai da Sa: miuelema wele sia: i, “Sa: miuele! Nagofe!” Sa: miuele da bu adole i, “Wae!”
Ṣùgbọ́n Eli pè é, ó sì wí pé, “Samuẹli, ọmọ mi.” Samuẹli sì dáhùn pé, “Èmi nìyìí.”
17 Ilai da ema amane adole ba: i, “Hina Gode da dima adi sia: bela: ? Liligi afae nama mae wamolegema. Dia sia: afae Gode Ea dima adoi amo afae hame adosea, E da dima gasa bagade se dabe imunu.”
Eli béèrè pé, “Kín ni ohun tí ó sọ fún ọ?” “Má ṣe fi pamọ́ fún mi. Kí Ọlọ́run mi ṣe bẹ́ẹ̀ sí ọ àti jù bẹ́ẹ̀ lọ pẹ̀lú, bí ìwọ bá fi ohunkóhun tí ó wí fún ọ pamọ́ fún mi.”
18 Amaiba: le, Sa: miuele da Gode Ea sia: i afae mae wamolegele, e da Gode Ea sia: i liligi huluanedafa Ilaima adodole i. Amalalu, Ilai da amane sia: i, “E da Hina Gode. E da Ea adi hamomusa: dawa: sea, E da hamomu.”
Samuẹli sọ gbogbo rẹ̀ fún un, kò sì fi ohun kankan pamọ́ fún un. Nígbà náà Eli wí pé, “Òun ni Olúwa; jẹ́ kí ó ṣe ohun tí ó dára ní ojú rẹ̀.”
19 Sa: miuele da asigilaloba, Hina Gode da e amola gilisili lalusu. Hina Gode da hamobeba: le, Sa: miuele ea sia: be huluane da defele doaga: su.
Olúwa wà pẹ̀lú Samuẹli bí ó ṣe ń dàgbà, kò sì jẹ́ kí ọ̀kan nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ kùnà.
20 Amaiba: le Isala: ili fi la: idi bega: amola la: idi bega: fifilai, ilia da Sa: miuele da dafawane Hina Gode Ea balofede dunu galebeya dawa: digisu.
Gbogbo Israẹli láti Dani títí dé Beerṣeba mọ̀ pé a ti fa Samuẹli kalẹ̀ gẹ́gẹ́ bí wòlíì Olúwa.
21 Hina Gode da musa: Siailou moilaiga Sa: miuelema misini, ema sia: dasu. Amola E da amogai eso bagohame gebewane doaga: ga: su amola sia: olelelalusu. Amalalu, Sa: miuele da sia: beba: le, Isala: ili dunu huluane da ea sia: nabalusu.
Olúwa sì bẹ̀rẹ̀ sí ní fi ara hàn án ní Ṣilo, nítorí Olúwa ti fi ará hàn án fún Samuẹli ní Ṣilo nípa ọ̀rọ̀ Olúwa.

< 1 Sa:miuele 3 >